< Nehemiah 6 >

1 Nígbà tí Sanballati, Tobiah Geṣemu ará Arabia àti àwọn ọ̀tá wa tókù gbọ́ pé, mo ti tún odi náà mọ, kò sì sí àlàfo kankan tí ó ṣẹ́kù nínú rẹ̀—bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé èmi kò ì tí ì ri àwọn ìlẹ̀kùn ibodè ní àkókò náà.
Vongtung ka sak uh te Sanballat, Tobiah, Arab Geshem neh kaimih thunkha coihpaih loh a yaak. Te vaengah a khuikah a puut tah hmaai voel pawt dae te vaeng tue hil vongka ah thohkhaih ka buen hlan.
2 Sanballati àti Geṣemu rán iṣẹ́ yìí sí mi pé, “Wá jẹ́ kí a jọ pàdé pọ̀ nínú ọ̀kan lára àwọn ìletò ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Ono.” Ṣùgbọ́n wọ́n ń gbèrò láti ṣe mí ní ibi;
Te dongah Sanballat neh Geshem loh kai taengla ol han tah tih, “Ha lo lamtah Ono kolbawn kah sathuengca ah tuentah uh rhoi sih,” a ti. Tedae amih te kai taengah boethae huet hamla cai uh.
3 bẹ́ẹ̀ ni mo rán oníṣẹ́ padà pẹ̀lú èsì yìí pé, “Èmi ń ṣe iṣẹ́ ńlá kan, èmi kò le è sọ̀kalẹ̀ wá. Èéṣe tí iṣẹ́ náà yóò fi dúró, nígbà tí mo bá fi í sílẹ̀ tí mo sì sọ̀kalẹ̀ tọ̀ yín wá?”
Amih rhoi taengla puencawn rhoek te ka tueih tih, “Bibi tung he ka saii dongah suntlak ham ka coeng moenih. Balae tih bitat he ka toeng eh? Te te ka hlong vetih nang taengla ka suntla aya?
4 Wọ́n rán iṣẹ́ náà sí mi nígbà mẹ́rin ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀, mo sì fún wọn ní èsì bákan náà fún ìgbà kọ̀ọ̀kan.
He ol he kai taengla voei li ham pat uh coeng dae amih te he tlam ni ol ka mael.
5 Ní ìgbà karùn-ún, Sanballati rán ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ sí mi pẹ̀lú irú iṣẹ́ kan náà, lẹ́tà kan tí a kò fi sínú àpò ìwé wà ní ọwọ́ rẹ̀
A voei nga nah dongah khaw he kah ol bangla Sanballat loh kai taengla a taengca kut neh ham pat dae ca te a kut dongah a ong coeng.
6 tí a kọ sínú un rẹ̀ pé, “A ròyìn rẹ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, Geṣemu sì sọ pé, òtítọ́ ni, pé ìwọ àti àwọn Júù ń gbèrò láti ṣọ̀tẹ̀, nítorí náà ni ẹ ṣe ń mọ odi. Síwájú sí i, gẹ́gẹ́ bí ìròyìn yìí, ìwọ sì ń gbèrò láti di ọba wọn
A khuikah a daek te namtom lakli neh Geshem te a yaak sak tih, “Nang neh Judah rhoek hlang tah tloelh ham ka moeh eh na ti rhoi. He dongah ni nang loh vongtung he na tlaih. Nang te he kah ol bangla amih taengah manghai la na om la te.
7 àti pé ó ti yan àwọn wòlíì kí wọn lè kéde nípa rẹ̀ ní Jerusalẹmu: ‘Ọba kan wà ní Juda!’ Nísinsin yìí, ìròyìn yìí yóò padà sí ọ̀dọ̀ ọba; nítorí náà wá, jẹ́ kí a bá ara wa sọ̀rọ̀.”
Tonghma rhoek pataeng Jerusalem ah nang kawng aka doek la, Judah ah manghai om tih he ol bangla manghai taengah yaak sak pawn saeh, halo lamtah tun dawt uh thae pawn sih,’ aka ti hamla na pai sak,”.
8 Mo dá èsì yìí padà sí i pé, “Kò sí ohun kan nínú irú ohun tí ìwọ sọ tí ó ṣẹlẹ̀; ìwọ kàn rò wọ́n ní orí ara rẹ ni.”
Te vaengah anih te ol ka pat tih, “Na thui ol bang he a om noek moenih. Tedae te te na lungbuei lamkah na thainawn,” ka ti nah.
9 Gbogbo wọn múra láti dẹ́rùbà wá, wọ́n ń rò ó wí pé, “Ọwọ́ wọn kò ní ran iṣẹ́ náà, àti wí pé wọn kò ní parí rẹ̀.” Ṣùgbọ́n mo gbàdúrà pé, “Nísinsin yìí Ọlọ́run fi agbára fún ọwọ́ mi.”
A pum la kaimih n'hih uh tih, “Bibi dongah a kut kha uh vetih saii uh mahpawh,” ti mai cakhaw ka kut he ham moem laeh.
10 Ní ọjọ́ kan mo lọ sí ilé Ṣemaiah ọmọ Delaiah, ọmọ Mehetabeeli, ẹni tí a há mọ́ sínú ilé rẹ̀. Ó wí pé, “Jẹ́ kí a pàdé ní ilé Ọlọ́run nínú tẹmpili, kí o sì jẹ́ kí a pa àwọn ìlẹ̀kùn tẹmpili dé, nítorí àwọn ènìyàn ń bọ̀ láti pa ọ́, ní òru ni wọn yóò wá láti pa ọ́.”
Te phoeiah kamah te Mehetabel koca, Delaiah capa Shemaiah im la ka pawk. Te vaengah anih te ying tih, “Bawkim khui kah Pathen im ah hum uh rhoi sih. Nang aka ngawn ham te ha pawk dongah bawkim thohkhaih te khai sih. Khoyin ah khaw nang aka ngawn ham hlang te ha pawk,” a ti.
11 Ṣùgbọ́n mo wí pé, “Ǹjẹ́ ó yẹ kí irú ènìyàn bí èmi sálọ? Tàbí kí ènìyàn bí èmi sálọ sínú tẹmpili láti gba ẹ̀mí ara rẹ̀ là? Èmi kò ní lọ!”
Tedae, “Kai bang hlang he yong a? Kai bang he unim bawkim khuila kun vetih a hing eh? Ka kun mahpawh,” ka ti nah.
12 Èmi wòye pé Ọlọ́run kò rán an, ṣùgbọ́n ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí mi nítorí Tobiah àti Sanballati ti bẹ̀ ẹ́ ní ọ̀wẹ̀.
Te vaengah Pathen loh anih tueih pawt la he tila ka hmat. Tedae anih te Tobiah neh Sanballat loh a paang dongah ni kai taengah tonghma ol a thui.
13 Wọ́n bẹ̀ ẹ́ ní ọ̀wẹ̀ láti dẹ́rùbà mí nítorí kí èmi lè dẹ́ṣẹ̀ nípa ṣíṣe èyí, kí wọn lè bà mí lórúkọ jẹ́, kí n sì di ẹni ẹ̀gàn.
Kai hih tih he tla ka saii vaengah kai tholh sak ham neh amih taengah ming thae la om sak ham anih te a paang tangloeng, kai he m'veet uh tangloeng.
14 A! Ọlọ́run mi, rántí Tobiah àti Sanballati, nítorí ohun tí wọ́n ti ṣe; kí o sì tún rántí Noadiah wòlíì obìnrin àti àwọn wòlíì tókù tí wọ́n ń gbèrò láti dẹ́rùbà mí.
Ka Pathen aw, Tobiah taeng neh Sanballat taengah khaw, tonghmanu Noadiah taeng neh tonghma a noi rhoek taengah kaw, a khoboe bangla thoelh pah. Amih te kai aka hih rhoek ni.
15 Bẹ́ẹ̀ ni a parí odi náà ní ọjọ́ kẹẹdọ́gbọ̀n oṣù Eluli, láàrín ọjọ́ méjìléláàádọ́ta.
Te cakhaw Elul pakul panga kah sawmnga neh hnin nit vaengah tah vongtung a khah uh.
16 Nígbà tí àwọn ọ̀tá wa gbọ́ èyí, gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí ó yí wa ká bẹ̀rù jìnnìjìnnì sì mú wọn, nítorí wọ́n wòye pé iṣẹ́ yìí di ṣíṣe pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ Ọlọ́run wa.
Ka thunkha boeih loh a yaak uh tih kaimih kaep kah namtom boeih loh a rhih dongah a maelhmai rhep a buenglueng uh. Bitat a saii he kaimih kah Pathen taeng lamkah ni tila a ming uh.
17 Bákan náà, ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì àwọn ọlọ́lá Juda ń kọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ lẹ́tà ránṣẹ́ sí Tobiah, èsì láti ọ̀dọ̀ Tobiah sì ń wá sí ọ̀dọ̀ wọn.
Te vaeng khohnin ah Judah hlangcoelh rhoek loh amih ca te Tobiah taengla muep a pha sak tih Tobiah taeng lamkah te khaw amih taengla cet.
18 Nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn Juda ti mulẹ̀ pẹ̀lú rẹ̀, nítorí tí ó jẹ́ àna Ṣekaniah ọmọ Arah (Sanballati fẹ́ ọmọ Ṣekaniah), ọmọ rẹ̀ Jehohanani sì tún fẹ́ ọmọbìnrin Meṣullamu ọmọ Berekiah.
Arah capa Shekaniah loh Tobiah a cava nah tih a capa Jehohanan long khaw Berekiah capa Meshullam canu te a loh dongah Judah kah boei rhoek khaw anih taengah olhlo neh muep omuh.
19 Síwájú sí í, wọ́n túbọ̀ ń ròyìn iṣẹ́ rere rẹ̀ fún mi, wọ́n sì ń sọ ohun tí mo sọ fún un. Tobiah sì ń kọ àwọn lẹ́tà ránṣẹ́ sí mi láti dẹ́rùbà mí.
Ka mikhmuh ah a then aka thui khaw om uh tih a taengla kai ol aka thak khaw om uh. Tobiah long khaw kai hih hamla ca ham pat.

< Nehemiah 6 >