< Nehemiah 5 >
1 Nísinsin yìí àwọn ènìyàn àti àwọn ìyàwó wọn kígbe ńlá sókè sí àwọn Júù arákùnrin wọn.
Fa: no, eso afaega, dunu amola uda bagohame da ilia Yu na: iyado dunu ilima ougili fofada: su.
2 Àwọn kan ń wí pé, “Àwa àti àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin wa pọ̀; kí àwa kí ó le è jẹ, kí a sì wà láààyè, a gbọdọ̀ rí oúnjẹ.”
Mogili da amane sia: i, “Ninia da sosogo fi bagade. Amaiba: le, ninima ha: i manu gagoma moma: ne imunu da defea.”
3 Àwọn mìíràn wí pé, “Àwa ti fi oko wa ọgbà àjàrà wa àti ilé wa dógò kí àwa kí ó lè rí oúnjẹ ní àkókò ìyàn.”
Eno mogili da amane sia: i, “Ninia da ha: i mae nawene bogosa: besa: le, ninia ifabi, waini sagai amola gagoma bidi lama: ne, amoga ninia eno dunuma muni lai. Be amo muni lai fa: no dabema: ne iasu dabe hame iasea, ilia da ninia ifabi amola waini sagai huluane samogemu.”
4 Síbẹ̀ àwọn mìíràn wí pé, “Àwa ní láti yá owó láti san ìṣákọ́lẹ̀ fún ọba lórí àwọn oko wa àti àwọn ọgbà àjàrà wa.
Eno mogili da amane sia: i, “Ninia da eagene soge su (da: gisi) ima: ne muni hame gala. Amaiba: le, amo muni ima: ne, ninia da eno dunu amoga muni amo fa: no dabe ima: ne, ilima lai.
5 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a jẹ́ ẹran-ara kan àti ẹ̀jẹ̀ kan gẹ́gẹ́ bí àwọn ará ìlú wa tí àwọn ọmọkùnrin wa sì dára bí í tiwọn, síbẹ̀ àwa ní láti fi àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin wa sí oko ẹrú. Díẹ̀ nínú àwọn ọmọbìnrin wa ti wà lóko ẹrú náà, ṣùgbọ́n àwa kò ní agbára, nítorí àwọn oko àti ọgbà àjàrà wa ti di ti ẹlòmíràn.”
Ninia amola da Yu dunudafa. Ninia mano da eno Yu dunu ilia mano defele esala. Be ninia da muni hameba: le, ninia mano da udigili se dabe hawa: hamoma: ne, ninia da enoma bidi lasa. Ninia uda mano mogili amo ninia bidi lai dagoi. Ninia ifabi amola waini sagai da ilia samogeiba: le, ninia da gasa hame ba: sa.”
6 Èmi bínú gidigidi nígbà tí mo gbọ́ igbe wọn àti àwọn ẹ̀sùn wọ̀nyí.
Na da ilia sia: gesu nababeba: le, ougi bagade ba: i.
7 Mo rò wọ́n wò ní ọkàn mi mo sì fi ẹ̀sùn kan ọlọ́lá àti àwọn ìjòyè. Mo sọ fún wọn pé, ẹ̀yin ń gba owó èlé lọ́wọ́ àwọn ará ìlú u yín! Nítorí náà mo pe àpéjọ ńlá láti bá wọn wí.
Na da amo hou hahamomusa: ilegei. Na da dunu fi ouligisu hina dunu amola ouligisu dunu eno ilima gagabole sia: i, “Dilia da dilia diolalali amo banenesilala,” na amane sia: i. Na da dunu huluane amo hou sia: sa: imusa: gilisima: ne sia: i.
8 Mo sì wí fún wọn pé, “Níbi tí àwa ní agbára mọ, àwa ti ra àwọn Júù arákùnrin wa tí a ti tà fún àwọn tí kì í ṣe Júù padà. Nísinsin yìí ẹ̀yìn ń ta àwọn arákùnrin yín, tí àwa sì tún ní láti rà wọ́n padà!” Wọ́n dákẹ́, nítorí wọn kò rí ohunkóhun sọ.
Na da amane sia: i, “Musa: ninia olalali Yu fi da muni hameba: le, ilisu da ilia da: i hodo amo ga fi dunuma bidi lasu. Be ninia da wali ninia gasa defele, amo dunu bu bidilala. Be wali dilia ouligisu dunu da hame gagui dunu banenesibiba: le, dilia Yu yolalali da ilisu ga fi dunuma hame, be eno Yu dunuma ilia da: i hodo udigili se dabe hawa: hamoma: ne bidi lasa,” na amane gagabole sia: i. Yu ouligisu dunu ilia bu adole imunu gogoleiba: le, ouiya: i.
9 Nítorí náà, mo tẹ̀síwájú pé, “Ohun tí ẹ̀ ń ṣe kò dára. Kò ha yẹ kí ẹ máa rìn nínú ìbẹ̀rù Ọlọ́run bí, láti yẹra fún ẹ̀gàn àwọn orílẹ̀-èdè mìíràn tí í ṣe ọ̀tá wa?
Amalalu, na amane sia: i, “Dilia hou wali hamosu da wadela: i. Dilia Gode Ea sia: nabimu amola moloidafa hou hamomu da defea galu. Amasea, ninima ha lai Dienadaile dunu, ninima oufesega: ma: ne bai hame ba: mu galu.
10 Èmi àti àwọn arákùnrin mi àti àwọn ènìyàn mi, pẹ̀lú ń yá àwọn ènìyàn lówó àti oúnjẹ. Ṣùgbọ́n ẹ jẹ́ kí a dáwọ́ owó èlé gbígbà yìí dúró!
Na da eno dunuma muni amola gagoma amo fa: no dabe bu hame lama: ne i dagoi. Amola na sama amola gilisili hawa: hamosu dunu da amo defele hamoi. Na hanai da ninia bu fa: no dabe lama: ne sia: su yolemu.
11 Ẹ fún wọn ní oko wọn, ọgbà àjàrà wọn, ọgbà olifi wọn àti ilé e wọn pẹ̀lú owó èlé tí ẹ ti gbà lọ́wọ́ wọn ìdá ọgọ́rùn-ún owó, oúnjẹ, wáìnì tuntun àti òróró tí ẹ ti gbà lọ́wọ́ wọn padà kíákíá.”
Ilia da dilima dabe imunu hou-amo muni o gagoma o waini o olife susuligi-amo huluane yolesima. Amola ilia liligi dabe dilia lai huluane ilima bu ima. Wahadafa amo ifabi, waini sagai, olife ifa sagai amola diasu huluane ilima bu ima,” na sia: i.
12 Wọ́n wí pé, “Àwa yóò dá a padà. Àwa kì yóò sì béèrè ohunkóhun lọ́wọ́ wọn mọ́. Àwa yóò ṣe bí o ti wí.” Nígbà náà mo pe àwọn àlùfáà, mo sì mú kí àwọn ọlọ́lá àti àwọn ìjòyè búra láti jẹ́ kí wọ́n ṣe ohun tí wọ́n ti ṣe ìlérí.
Ouligisu dunu ilia bu adole i, “Defea! Dia sia: ninia nabi dagoi. Ninia da liligi lai bu ianu, dabe lamu galea amo dabe hame lamu.” Na da gobele salasu dunu misa: ne sia: i. Amola gobele salasu dunu ba: ma: ne, ouligisu dunu da amo hou dafawane hamoma: ne, Hina Gode Ea Dio: ba: le ilegele sia: musa: , na da sia: i.
13 Mo sì gbọn ìṣẹ́tí aṣọ mi, mo wí pé, “Báyìí ni kí Ọlọ́run gbọn olúkúlùkù ènìyàn tí kò bá pa ìlérí yìí mọ́ jáde kúrò ní ilẹ̀ ìní i rẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni kí a gbọn irú ẹni bẹ́ẹ̀ jáde kí ó sì ṣófo!” Gbogbo ìjọ ènìyàn sì wí pé, “Àmín,” wọ́n sì fi ìyìn fún Olúwa. Àwọn ènìyàn náà sì ṣe bí wọ́n ti ṣe ìlérí.
Amalalu, na da abula beano fonobahadi buluyale idinigi amo fadegale fasili, duduli fasi. Na da amane sia: i, “Nowa dunu da ea dafawane waha sia: i liligi hame hamosea, Gode da amo defele duduli fasimu. Gode da dilia diasu amola dilia gagui liligi huluane samogele, dilia da da: i nabado agoane ba: mu,” na amane sia: i. Dunu huluane gilisili esalu da “Ama” sia: i amola Godema nodoi. Amola Yu ouligisu dunu da ilia dafawane ilegele sia: i defele hamosu.
14 Síwájú sí í, láti ogún ọdún ọba Artasasta, nígbà tí a ti yàn mí láti jẹ́ baálẹ̀ wọn ní ilẹ̀ Juda, títí di ọdún kejìlélọ́gbọ̀n ìjọba rẹ̀—ọdún méjìlá, èmi àti àwọn arákùnrin mi kò jẹ oúnjẹ baálẹ̀.
Ode fagoyale gala, amo da Adasegesisi da Besia sogega hina bagade esalu ea ouligisu hou da ode 20 gidigi amo ode mui asili Adasegesisi ea ouligisu ode 32 gidigi, ode fagoyale amoga na da Yu sogega eagene ouligisudafa dunu esalu. Na amola na sosogo fi da ha: i manu amo eagene ouligisu ilima ilegei, amo manu da defea galu. Be ninia da hame nasu.
15 Ṣùgbọ́n àwọn baálẹ̀ ìṣáájú—tí ó ti wà ṣáájú mi—gbe àjàgà wúwo lé àwọn ènìyàn lórí yàtọ̀ fún oúnjẹ àti wáìnì wọ́n sì tún gba ogójì ṣékélì fàdákà lọ́wọ́ wọn. Kódà àwọn ìránṣẹ́ wọn tún jẹ gàba lórí wọn. Ṣùgbọ́n èmi kò ṣe bẹ́ẹ̀ nítorí ìbẹ̀rù Ọlọ́run.
Eagene ouligisu dunu musa: na mae aligili, ilia hou hamoiba: le, Yu dunu da da: i dioi bagade nabi. Ilia da Yu dunuma eso huluane silifa muni fage 40 agoane ilia ha: i manu amola waini lamusa: edegesu. Ilia hawa: hamosu dunu amola da Yu dunu banenisisu. Be na hou da hisu hamoi. Bai na da Godema nodone fa: no bobogei.
16 Dípò bẹ́ẹ̀, mo fi ara mi jì fún iṣẹ́ lórí odi yìí. Gbogbo àwọn ènìyàn mi péjọ síbẹ̀ fún iṣẹ́ náà; a kò sì gba ilẹ̀ kankan.
Na da gagoi mugului amo bu gagomusa: fawane dawa: i galu. Na da soge lamu hame dawa: i galu. Na hawa: hamosu dunu amola da moilai gagoi fidi.
17 Síwájú sí í, àádọ́jọ àwọn Júù àti àwọn ìjòyè jẹun lórí tábìlì mi, àti pẹ̀lú àwọn tí wọ́n wá bá wa láti àwọn orílẹ̀-èdè tí ó yí wa ká.
Eso huluane, Yu dunu 150 amola ilia ouligisu dunu da na diasuga ha: i namasu. Amola, ninia na: iyado ga fi dunu bagohame da misini, na diasuga ha: i nasu.
18 Ní ọjọ́ kọ̀ọ̀kan ni a máa ń pèsè màlúù kan, ààyò àgùntàn mẹ́fà àti adìyẹ fún mi àti lẹ́ẹ̀kan ní ọjọ́ mẹ́wàá ni wọ́n máa ń pèsè onírúurú wáìnì tí ó pọ̀ fún mi. Fún gbogbo èyí, èmi kò béèrè oúnjẹ baálẹ̀, nítorí ohun ti a ń béèrè lọ́wọ́ àwọn ènìyàn wọ̀nyí pọ̀ jọjọ.
Eso huluane, na da bulamagau afae, sibi noga: idafa gafeyale amola gagala bagohame gobele moma: ne iasu. Be na da dunu ilia da: i diomu amo dawa: beba: le, eagene muni nama ilegei amo hame lasu.
19 Rántí mi, Ọlọ́run mi, fún rere, nítorí fún gbogbo ohun tí mo ti ṣe fún àwọn ènìyàn yìí.
Gode! Na da dima sia: ne gadosa. Na da dunu huluane fidima: ne hawa: hamosu amo mae gogolema. Amola nama hahawane ima.