< Nehemiah 4 >

1 Nígbà tí Sanballati gbọ́ pé àwa ń tún odi náà mọ, ó bínú, ó sì bínú púpọ̀. Ó fi àwọn ará Júù ṣe ẹlẹ́yà,
Ke Sanballat el lohng lah kut mwet Jew mutawauk tari in sifil musai pot uh, el kasrkusrak ac mutawauk in sufan kut.
2 ó sọ níwájú àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ àti níwájú àwọn ọmọ-ogun Samaria pé, “Kí ni àwọn aláìlera Júù wọ̀nyí ń ṣe yìí? Ṣé wọn yóò mú odi wọn padà ni? Ṣé wọn yóò rú ẹbọ ni? Ṣé wọn yóò parí i rẹ̀ lóòjọ́ ni bí? Ṣé wọ́n lè mú òkúta tí a ti sun láti inú òkìtì padà bọ̀ sípò tí ó jóná bí wọ́n ṣe wà?”
El fahk ye mutun mwet lal ac un mwet mweun lun Samaria, “Mea mwet Jew afon inge oru uh? Ya elos nunku in sifil musai siti uh? Ya elos nunku mu ke sripen mwe kisa elos oru inge, ac ku in tari ke len sefanna? Ya elos ku in orek eot in musa ke yol in eot firirla ac mokutkuti?”
3 Tobiah ará Ammoni, ẹni tí ó wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀, wí pé, “Ohun tí wọ́n ń mọ—bí kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ lásán bá gùn ún sókè, yóò fọ́ odi òkúta wọn lulẹ̀!”
Tobiah el tu siskal na el fahk, “Pot fuka se elos ac ku in orala? Finne fox soko, el ac ku in rakinya!”
4 Gbọ́ ti wa, Ọlọ́run wa, nítorí àwa di ẹni ẹ̀gàn. Dá ẹ̀gàn wọn padà sórí ara wọn. Kí o sì fi wọ́n fún ìkógun ní ilẹ̀ ìgbèkùn.
Nga pre ac fahk, “O God, lohng kas in aksruksruk lalos kacsr inge. Lela angonkas lalos in folokyang nu faclos sifacna. Lela tuh ma lalos nukewa in pisreyukla, ac in utukla elos oana luman mwet kapir nu in sie mutunfacl ma elos mwetsac nu we.
5 Má ṣe bo ẹ̀bi wọn tàbí wẹ àwọn ẹ̀ṣẹ̀ wọn nù kúrò níwájú rẹ, nítorí wọ́n mú ọ bínú níwájú àwọn ọ̀mọ̀lé.
Nikmet nunak munas ke ma koluk elos oru, ac nikmet mulkunla ma koluk lalos, ke sripen elos akkolukye kut su musa.”
6 Bẹ́ẹ̀ ni àwa mọ odi náà títí gbogbo rẹ̀ fi dé ìdajì gíga rẹ̀, nítorí àwọn ènìyàn ṣiṣẹ́ pẹ̀lú gbogbo ọkàn an wọn.
Ouinge kut orekma na ke pot uh. Tia paht na sun tafu fulata, ke sripen mwet uh arulana insewowo in orekma.
7 Ṣùgbọ́n nígbà tí Sanballati, Tobiah, àwọn ará Arabia, ará Ammoni, àti àwọn ènìyàn Aṣdodu gbọ́ pé àtúnṣe odi Jerusalẹmu ti ga dé òkè àti pé a ti mọ àwọn ibi tí ó yá dí, inú bí wọn gidigidi.
Sanballat, Tobiah, ac mwet Arabia, mwet Ammon, ac mwet Ashdod elos lohngak lah kilkilukyakna orekma lasr ke pot Jerusalem, ac acn ma soenna kupasreni ke pot ah fahsr in fonfonla, na elos kasrkusrakak.
8 Gbogbo wọn jọ gbìmọ̀ pọ̀ láti wá bá Jerusalẹmu jà àti láti dìde wàhálà sí í.
Ouinge elos nukewa pwapa in tukeni tuku fusauk orekma uh, ac mweuni Jerusalem.
9 Ṣùgbọ́n àwa gbàdúrà sí Ọlọ́run wa, a sì yan olùṣọ́ ọ̀sán àti ti òru láti kojú ìhàlẹ̀ yìí.
Tusruktu kut pre nu sin God lasr, ac filiya mwet in topangi mwet lokoalok ke len ac fong.
10 Lákòókò yìí, àwọn ènìyàn Juda wí pé, “Agbára àwọn òṣìṣẹ́ ti dínkù, àlàpà púpọ̀ ni ó wà tó bẹ́ẹ̀ tí àwa kò fi le è mọ odi náà.”
Mwet Judah elos onkakin on in asor soko inge: “Kut munasla in us ma toasr, Ac puslana kutkut in utukla. Kut ac musai pot uh fuka?”
11 Bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn ọ̀tá wa wí pé, “Kí wọn tó mọ̀ tàbí kí wọn tó rí wa, àwa yóò ti dé àárín wọn, a ó sì pa wọ́n, a ó sì dá iṣẹ́ náà dúró.”
Mwet lokoalok lasr nunku mu kut ac tia liyalos ku etu ma elos akoo nwe ke elos sun kut ac unikuti, in pwanang orekma lasr uh in tui.
12 Nígbà náà ni àwọn Júù tí ó ń gbé ní ẹ̀gbẹ́ wọn wá sọ fún wa ní ìgbà mẹ́wàá pé, “Ibikíbi tí ẹ̀yin bá padà sí, wọn yóò kọlù wá.”
Tusruktu pacl pus, mwet Jew su muta inmasrlon mwet lokoalok lasr, elos fahsr fahk nu sesr ma elos akoo in oru lain kut.
13 Nítorí náà mo dá ènìyàn díẹ̀ dúró níbi tí ó rẹlẹ̀ jù lẹ́yìn odi ní ibi gbangba, mo fi wọ́n síbẹ̀ nípa àwọn ìdílé wọn, pẹ̀lú àwọn idà wọn, àwọn ọ̀kọ̀ wọn àti àwọn ọrun wọn.
Ouinge nga sang cutlass, osra, ac pisr nu sin mwet lasr, ac oakelosi in sou, tuh elos in tu sisken pot uh nu loac, ke acn nukewa ma patpat ac srakna pusisel.
14 Lẹ́yìn ìgbà tí mo wo àwọn nǹkan yíká, mo dìde mo sì wí fún àwọn ọlọ́lá àwọn ìjòyè àti àwọn ènìyàn tókù pé, “Ẹ má ṣe bẹ̀rù u wọn. Ẹ rántí Olúwa, ẹni tí ó tóbi, tí ó sì ní ẹ̀rù, kí ẹ sì jà fún àwọn arákùnrin yín, àwọn ọmọkùnrin yín, àwọn ọmọbìnrin yín, àwọn ìyàwó yín àti àwọn ilé yín.”
Nga akilen lah mwet uh fosrnga, ouinge nga fahk nu selos, ac nu sin mwet kol ac mwet pwapa, “Nik kowos sangeng sin mwet lokoalok lasr. Esam lupan fulat ac ku sakirik lun LEUM GOD, ac kowos in mweun ke mwet wiowos, tulik nutuwos, mutan kiowos, ac acn suwos.”
15 Nígbà tí àwọn ọ̀tá wa gbọ́ pé àwa ti mọ èrò wọn àti wí pé Ọlọ́run ti bà á jẹ́, gbogbo wa padà sí ibi odi, ẹnìkọ̀ọ̀kan sí ibi iṣẹ́ tirẹ̀.
Mwet lokoalok lasr elos lohng lah kut etu tari pwapa lalos, ac elos akilen tuh God El sikulya lemlem lalos. Na kut nukewa folokla in sifil musai pot uh.
16 Láti ọjọ́ náà lọ, ìdajì àwọn ènìyàn ń ṣe iṣẹ́ náà, nígbà tí àwọn ìdajì tókù múra pẹ̀lú ọ̀kọ̀, asà, ọrun àti ìhámọ́ra. Àwọn ìjòyè sì pín ara wọn sẹ́yìn gbogbo ènìyàn Juda.
In pacl sac me, tafu mwet luk uh orekma ke musa, ac tafu topangi mwet lokoalok. Elos nukum nuknuk in mweun ac sruokya osra, mwe loeyuk, ac pisr natulos. Ac mwet kolyasr elos arulana sang ku lalos in akpulaikye mwet
17 Àwọn ẹni tí ó ń mọ odi. Àwọn tí ń ru àwọn ohun èlò ṣe iṣẹ́ náà pẹ̀lú ọwọ́ kan, wọ́n sì fi ọwọ́ kejì di ohun ìjà mú,
su musai pot uh. Finne elos su til kufwen mwe orekma, elos orekma ke la paolos ac ke lac po ngia elos sruok mwe anwuk natulos.
18 olúkúlùkù àwọn ọ̀mọ̀lé fi idà wọn sí ẹ̀gbẹ́ wọn bí wọ́n ṣe ń ṣiṣẹ́. Ṣùgbọ́n ọkùnrin tí ń fọn ìpè dúró pẹ̀lú mi.
Ac mwet musa nukewa elos sripisrya cutlass natulos ke pupalos. Mwet se ma ac sulkakin pacl in mweun ke pusren mwe ukuk el tu na siskuk.
19 Nígbà náà ni mo sọ fún àwọn ọlọ́lá, àwọn ìjòyè àti àwọn ènìyàn tókù pé, “Iṣẹ́ náà fẹ̀ ó sì pọ̀, a sì ti jìnnà sí ara wa púpọ̀ lórí odi.
Nga fahk nu sin mwet uh ac mwet pwapa ac mwet kol lalos, “Ke sripen orekma uh arulana yohk, kut ac muta loes inmasrlosr sie sin sie fin pot uh.
20 Níbikíbi tí ẹ bá ti gbọ́ ohùn ìpè, ẹ da ara pọ̀ mọ́ wa níbẹ̀. Ọlọ́run wa yóò jà fún wa!”
Kowos fin lohng pusren ukuk, aksaye fahsreni nu yuruk. God lasr uh ac fah mweun kacsr.”
21 Bẹ́ẹ̀ ni àwa ṣe iṣẹ́ náà pẹ̀lú àwọn ìdajì ènìyàn tí ó di ọ̀kọ̀ mú, láti òwúrọ̀ kùtùkùtù títí di ìgbà tí ìràwọ̀ yóò fi yọ.
Ouinge len nukewa, mutawauk ke kusrun len uh nwe ke itu uh takak ke fong, tafu sesr orekma ke pot uh, ac tafu tu sruok osra in mweun ac topang mwet lokoalok uh.
22 Ní ìgbà náà mo tún sọ fún àwọn ènìyàn pé, “Jẹ́ kí olúkúlùkù ènìyàn àti olùrànlọ́wọ́ rẹ̀ dúró ní Jerusalẹmu ní òru, nítorí kí wọn le jẹ́ ẹ̀ṣọ́ fún wa ní òru, kí wọn sì le ṣe iṣẹ́ ní ọ̀sán.”
Ke pacl se inge, nga fahk nu sin mwet kol orekma uh lah elos, ac mwet kasru lalos nukewa, in mutana Jerusalem ke fong uh, tuh kut in ku in forfor taran siti uh ke fong, ac orekma ke len.
23 Bẹ́ẹ̀ ni èmi àti àwọn arákùnrin mi àti àwọn ènìyàn mi àti àwọn ẹ̀ṣọ́ tí ó wà pẹ̀lú mi kò bọ́ aṣọ wa, olúkúlùkù wa ní ohun ìjà tirẹ̀, kódà nígbà tí wọ́n bá ń lọ pọn omi.
Nga tiana sarukla nuknuk luk uh, finne ke fong, ac mwet wiyu su kulansupweyu ac karinginyu elos oru oapana. Ac kut nukewa sruok na mwe mweun natusr inpaosr.

< Nehemiah 4 >