< Nehemiah 4 >
1 Nígbà tí Sanballati gbọ́ pé àwa ń tún odi náà mọ, ó bínú, ó sì bínú púpọ̀. Ó fi àwọn ará Júù ṣe ẹlẹ́yà,
Toe kaicae mah tapang ka thungh o let boeh, tiah Sanballat mah thaih naah, palungphui hmai baktiah amngaeh pae moe, Judahnawk to pahnuithuih.
2 ó sọ níwájú àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ àti níwájú àwọn ọmọ-ogun Samaria pé, “Kí ni àwọn aláìlera Júù wọ̀nyí ń ṣe yìí? Ṣé wọn yóò mú odi wọn padà ni? Ṣé wọn yóò rú ẹbọ ni? Ṣé wọn yóò parí i rẹ̀ lóòjọ́ ni bí? Ṣé wọ́n lè mú òkúta tí a ti sun láti inú òkìtì padà bọ̀ sípò tí ó jóná bí wọ́n ṣe wà?”
Anih mah angmacae ampuinawk hoi Samaria misatuh kaminawk hmaa ah, Thacak ai Judah kaminawk loe timaw sak atim o? Angmacae abuephaih tapang to a sak o moe, angbawnhaih sak han a thuih o maw? Nihcae mah nito thungah tapang to pacoeng o thai tih maw? Hmai mah kangh ih anghnoeng baktiah angpop sut thlung hoiah maw nihcae mah tapang to sah o tih? tiah thuih.
3 Tobiah ará Ammoni, ẹni tí ó wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀, wí pé, “Ohun tí wọ́n ń mọ—bí kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ lásán bá gùn ún sókè, yóò fọ́ odi òkúta wọn lulẹ̀!”
Anih taengah kaom Ammon kami Tobiah mah, Nihcae mah sak ih tapang loe tasui mah mataeng doeh a nui hoiah cawh nahaeloe, amtim rup tih takhae, tiah a naa.
4 Gbọ́ ti wa, Ọlọ́run wa, nítorí àwa di ẹni ẹ̀gàn. Dá ẹ̀gàn wọn padà sórí ara wọn. Kí o sì fi wọ́n fún ìkógun ní ilẹ̀ ìgbèkùn.
Toe Aw kaicae ih Sithaw, tahngai ah; minawk mah hnaphnaehaih ka tongh o boeh: nichae mah padaeng ih lok loe angmacae lu nuiah krah nasoe; nihcae misong ah naehhaih to om nasoe:
5 Má ṣe bo ẹ̀bi wọn tàbí wẹ àwọn ẹ̀ṣẹ̀ wọn nù kúrò níwájú rẹ, nítorí wọ́n mú ọ bínú níwájú àwọn ọ̀mọ̀lé.
nihcae mah tapang sah kaminawk to khet patoek o pongah, a sak o ih zaehaihnawk to pakaa pae hmah; nihcae zaehaih to na hmaa hoiah takhoe pae ving hmah, tiah lawk ka thuih.
6 Bẹ́ẹ̀ ni àwa mọ odi náà títí gbogbo rẹ̀ fi dé ìdajì gíga rẹ̀, nítorí àwọn ènìyàn ṣiṣẹ́ pẹ̀lú gbogbo ọkàn an wọn.
Toe tapang to ka sak o; kaminawk loe toksakhaih bangah palung ang paek o pongah, tapang ahap khoek to sak pacoeng o.
7 Ṣùgbọ́n nígbà tí Sanballati, Tobiah, àwọn ará Arabia, ará Ammoni, àti àwọn ènìyàn Aṣdodu gbọ́ pé àtúnṣe odi Jerusalẹmu ti ga dé òkè àti pé a ti mọ àwọn ibi tí ó yá dí, inú bí wọn gidigidi.
Toe Jerusalem tapang to pathoep o moe, akhawnawk doeh pading o let boeh, tiah Saballat, Tobiah, Arab kaminawk, Ammon kaminawk hoi Ashod kaminawk mah thaih o naah, paroeai palungphui o,
8 Gbogbo wọn jọ gbìmọ̀ pọ̀ láti wá bá Jerusalẹmu jà àti láti dìde wàhálà sí í.
nihcae loe Jerusalem to tuk moe, raihaih paek hanah, amkhueng moe, lok aram o.
9 Ṣùgbọ́n àwa gbàdúrà sí Ọlọ́run wa, a sì yan olùṣọ́ ọ̀sán àti ti òru láti kojú ìhàlẹ̀ yìí.
Toe kaicae loe kaimacae Sithaw khaeah lawk ka thuih o moe, nihcae pongah, aqum athun misa ka toep o.
10 Lákòókò yìí, àwọn ènìyàn Juda wí pé, “Agbára àwọn òṣìṣẹ́ ti dínkù, àlàpà púpọ̀ ni ó wà tó bẹ́ẹ̀ tí àwa kò fi le è mọ odi náà.”
To naah thoemto Judah kaminawk hoi toksah kaminawk loe thazok o, kamro thlung to pop hmoek pongah, tapang to ka sah o thai ai boeh, tiah a thuih o.
11 Bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn ọ̀tá wa wí pé, “Kí wọn tó mọ̀ tàbí kí wọn tó rí wa, àwa yóò ti dé àárín wọn, a ó sì pa wọ́n, a ó sì dá iṣẹ́ náà dúró.”
Ka misanawk mah, Judah kaminawk mah hnuk o han ai, panoek o han ai ah, nihcae salakah akun si loe, nihcae to hum si, to tiah a sak o ih tok to pakaa pae si, tiah a thuih o.
12 Nígbà náà ni àwọn Júù tí ó ń gbé ní ẹ̀gbẹ́ wọn wá sọ fún wa ní ìgbà mẹ́wàá pé, “Ibikíbi tí ẹ̀yin bá padà sí, wọn yóò kọlù wá.”
To naah nihcae taengah kaom Judahnawk to angzoh o moe, misa mah ahmuen kruek hoiah nangcae tuk hanah amsak o, tiah vai hato ang thuih o.
13 Nítorí náà mo dá ènìyàn díẹ̀ dúró níbi tí ó rẹlẹ̀ jù lẹ́yìn odi ní ibi gbangba, mo fi wọ́n síbẹ̀ nípa àwọn ìdílé wọn, pẹ̀lú àwọn idà wọn, àwọn ọ̀kọ̀ wọn àti àwọn ọrun wọn.
To pongah tapang hnuk bang ih ahmuen kahnaem hoi hmuensang ah sumsen, tayae hoi kalii sin kaminawk to angmacae imthung takoh kaminawk hoi nawnto ka ohsak.
14 Lẹ́yìn ìgbà tí mo wo àwọn nǹkan yíká, mo dìde mo sì wí fún àwọn ọlọ́lá àwọn ìjòyè àti àwọn ènìyàn tókù pé, “Ẹ má ṣe bẹ̀rù u wọn. Ẹ rántí Olúwa, ẹni tí ó tóbi, tí ó sì ní ẹ̀rù, kí ẹ sì jà fún àwọn arákùnrin yín, àwọn ọmọkùnrin yín, àwọn ọmọbìnrin yín, àwọn ìyàwó yín àti àwọn ilé yín.”
Hmuennawk ka khet pacoengah, angraengnawk hoi ukkungnawk, kanghmat kaminawk to ka kawk moe, Misanawk to zii o hmah, Lensawk zitthok, Angraeng to panoek oh, nam nawkamyanawk, na capanawk, na canunawk, na zunawk hoi na imthung takohnawk hanah misa to tuh oh, tiah ka thuih pae.
15 Nígbà tí àwọn ọ̀tá wa gbọ́ pé àwa ti mọ èrò wọn àti wí pé Ọlọ́run ti bà á jẹ́, gbogbo wa padà sí ibi odi, ẹnìkọ̀ọ̀kan sí ibi iṣẹ́ tirẹ̀.
Nihcae mah pacaeng ih hmuen to kaicae mah panoek boeh, tiah misanawk mah panoek o naah, Nihcae amsakhaih to Sithaw mah amrosak, to naah tapang sakhaih ahmuen ah kam laem o, kami boih angmacae toksakhaih ahmuen ah caeh o let.
16 Láti ọjọ́ náà lọ, ìdajì àwọn ènìyàn ń ṣe iṣẹ́ náà, nígbà tí àwọn ìdajì tókù múra pẹ̀lú ọ̀kọ̀, asà, ọrun àti ìhámọ́ra. Àwọn ìjòyè sì pín ara wọn sẹ́yìn gbogbo ènìyàn Juda.
To pacoeng hoi kamtong, ka tamna ahap kaminawk toksak o naah, ahap kaminawk mah maiphaw maica, tayae, angvaenghaih aphaw, kalii hoiah misa to toep o; ukkungnawk mah Judahnawk to abomh.
17 Àwọn ẹni tí ó ń mọ odi. Àwọn tí ń ru àwọn ohun èlò ṣe iṣẹ́ náà pẹ̀lú ọwọ́ kan, wọ́n sì fi ọwọ́ kejì di ohun ìjà mú,
Tapang sah kaminawk loe ban maeto hoiah tok to a sak o moe, ban maeto hoiah maiphawmaica to sinh o.
18 olúkúlùkù àwọn ọ̀mọ̀lé fi idà wọn sí ẹ̀gbẹ́ wọn bí wọ́n ṣe ń ṣiṣẹ́. Ṣùgbọ́n ọkùnrin tí ń fọn ìpè dúró pẹ̀lú mi.
Tapang sah kaminawk loe sumsen avak hoiah tapang to a sak o. Toe mongkah ueng kami loe ka taengah oh.
19 Nígbà náà ni mo sọ fún àwọn ọlọ́lá, àwọn ìjòyè àti àwọn ènìyàn tókù pé, “Iṣẹ́ náà fẹ̀ ó sì pọ̀, a sì ti jìnnà sí ara wa púpọ̀ lórí odi.
To naah kai mah, angraengnawk, ukkugnnawk hoi to ah kaom anghmat kaminawk khaeah, Toksakhaih ahmuen paroeai kawk pongah, tapang nuiah toksah kaminawk loe maeto hoi maeto kangthla ah ni na oh o.
20 Níbikíbi tí ẹ bá ti gbọ́ ohùn ìpè, ẹ da ara pọ̀ mọ́ wa níbẹ̀. Ọlọ́run wa yóò jà fún wa!”
Naa ih ahmuen hoiah doeh mongkah lok to na thaih o nahaeloe, kaicae khaeah angcuu oh, aicae ih Sithaw mah aicae hanah misa na tuh pae tih, tiah ka naa.
21 Bẹ́ẹ̀ ni àwa ṣe iṣẹ́ náà pẹ̀lú àwọn ìdajì ènìyàn tí ó di ọ̀kọ̀ mú, láti òwúrọ̀ kùtùkùtù títí di ìgbà tí ìràwọ̀ yóò fi yọ.
To tiah tok ka sak o; thoemto kaminawk loe akhawnbang hoi cakaeh amtueng khoek to tayae sinh hoiah tok to a sak o.
22 Ní ìgbà náà mo tún sọ fún àwọn ènìyàn pé, “Jẹ́ kí olúkúlùkù ènìyàn àti olùrànlọ́wọ́ rẹ̀ dúró ní Jerusalẹmu ní òru, nítorí kí wọn le jẹ́ ẹ̀ṣọ́ fún wa ní òru, kí wọn sì le ṣe iṣẹ́ ní ọ̀sán.”
To naah kaminawk khaeah, Kami boih aqum ah angmah ih tamna hoiah nawnto iip o nasoe, to tiah ni tamnanawk loe athun ah thoksah o ueloe, aqum ah aicae hanah misa toep o tih, tiah ka thuih pae.
23 Bẹ́ẹ̀ ni èmi àti àwọn arákùnrin mi àti àwọn ènìyàn mi àti àwọn ẹ̀ṣọ́ tí ó wà pẹ̀lú mi kò bọ́ aṣọ wa, olúkúlùkù wa ní ohun ìjà tirẹ̀, kódà nígbà tí wọ́n bá ń lọ pọn omi.
Tui amhluk nathuem khue ai ah loe, kai doeh, kam nawkamyanawk, ka tamnanawk hoi ka hnukbang kaminawk doeh, khukbuen kang khring o ai.