< Nehemiah 2 >
1 Ní oṣù Nisani, ní ogún ọdún ìjọba ọba Artasasta, nígbà tí a gbé wáìnì wá fún un, mo gbé wáìnì náà, mo fi fún ọba, ìbànújẹ́ kò hàn ní ojú mi rí ní iwájú rẹ̀.
Artaxerxes siangpahrang ah ohhaih saning pumphaeto akoephaih, Nisan khrah thungah, a hmaa ih misurtui to ka lak moe, siangpahrang hanah ka paek; a hmaa ah natuek naah doeh palungsethaih kam tuengsak vai ai vop.
2 Nítorí náà ni ọba béèrè lọ́wọ́ mi pé, “Èéṣe tí ojú rẹ fi fàro nígbà tí kò rẹ̀ ọ́? Èyí kì í ṣe ohun mìíràn bí kò ṣe ìbànújẹ́ ọkàn.” Ẹ̀rù bà mí gidigidi,
To pongah siangpahrang mah lok ang dueng, Ngan na tui to mah, tipongah mikhmai na set loe? Hae loe tidoeh na ai, palungsethaih ah ni oh, tiah ang naa. To naah paroeai ka zit,
3 ṣùgbọ́n mo wí fún ọba pé, “Kí ọba kí ó pẹ́! Èéṣe tí ojú mi ko ṣe ní fàro, nígbà tí ìlú tí a sin àwọn baba mi sí wà ní ahoro, tí a sì ti fi iná run àwọn ibodè rẹ̀?”
Kai mah siangpahrang khaeah, Siangpahrang na hinglung sawk nasoe! Kam panawk aphumhaih, vangpui to amro moe, khongkhanawk hmai mah kang naah, kawbangmaw mikhmai sae ai ah ka om thai tih? tiah ka naa.
4 Ọba wí fún mi pé, “Kí ni ìwọ ń fẹ́?” Nígbà náà, ni mo gbàdúrà sí Ọlọ́run ọ̀run,
Siangpahrang mah kai khaeah, Timaw na koeh? tiah ang naa. To pongah van Sithaw khaeah lawk ka thuih.
5 mo sì dá ọba lóhùn pé, “Ti ó bá wu ọba, tí ìránṣẹ́ rẹ bá sì rí ojúrere ní ojú rẹ, jẹ́ kí ó rán mi lọ sí ìlú náà ní Juda níbi tí a sin àwọn baba mi nítorí kí èmi lè tún un kọ́.”
Siangpahrang khaeah, siangpahrang koehhaih ah ka oh moe, na tamna hae na mikhnukah koeh koiah ka oh nahaeloe, vangpui to ka sak let thai hanah, kam pa aphumhaih, Judah prae ah na patoeh let ah, tiah ka naa.
6 Nígbà náà ni ọba, pẹ̀lú ìyàwó rẹ̀ tí ó jókòó lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀, bi mí pé, “Báwo ni ìrìnàjò náà yóò ṣe pẹ́ ọ tó, nígbà wo sì ni ìwọ yóò padà?” Ó dùn mọ́ ọba láti rán mi lọ, bẹ́ẹ̀ ni mo dá àkókò kan.
Siangpahrang mah, (siangpahrang zu doeh anih taengah anghnut) Kholong na caehhaih nazetto maw akra tih? Natuek naah maw nam laem o let han? tiah ang naa. Siangpahrang mah kai patoeh han poekhaih tawnh pongah, atue to ka pahoe.
7 Mo sì tún wí fún ọba pé, “Bí ó bá wu ọba, kí ó fún mi ní lẹ́tà sí àwọn baálẹ̀ òkè odò Eufurate kí wọ́n le mú mi kọjá títí èmi yóò fi dé Juda láìléwu.
Kai mah anih khaeah, Siangpahrang koeh baktiah om nahaeloe, vapui taeng ih prae ukkungnawk khaeah ca sin pae han ka koeh, to tiah ni Judah prae ka phak khoek to, nihcae mah kamong ah na patoeh o thai tih.
8 Kí èmi sì gba lẹ́tà kan lọ́wọ́ fún Asafu, olùṣọ́ igbó ọba, nítorí kí ó lè fún mi ní igi láti fi ṣe àtẹ́rígbà fún ibodè ilé ìṣọ́ tẹmpili àti fún odi ìlú náà àti fún ilé tí èmi yóò gbé?” Nítorí ọwọ́ àánú Ọlọ́run mi wà lórí mi, ọba fi ìbéèrè mi fún mi.
Siangpahrang ih taw toepkung, Asaph mah im khongkha tung, vangpui tapang, ka ohhaih im sak hanah thing ang paek thai hanah, ca na tarik pae thai tih maw? tiah ka naa. Ka Sithaw tahmenhaih ka ban ah oh pongah, ka hnik ih hmuen to siangpahrang mah ang paek.
9 Bẹ́ẹ̀ ni mo lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn baálẹ̀ agbègbè Eufurate, mo sì fún wọn ní àwọn lẹ́tà ọba. Ọba sì ti rán àwọn ológun àti àwọn ẹlẹ́ṣin ogun pẹ̀lú mi.
To pongah vapui zaeh ih prae ukkungnawk khaeah ka caeh moe, siangpahrang ih ca to ka paek. Siangpahrang mah misatuh angraengnawk hoi hrang angthueng kaminawk to ang patoeh pae.
10 Nígbà tí Sanballati ará Horoni àti Tobiah ará a Ammoni tí wọ́n jẹ́ ìjòyè gbọ́ nípa èyí pé, ẹnìkan wá láti mú ìtẹ̀síwájú bá àlàáfíà àwọn ará Israẹli inú bí wọn gidigidi.
Horon acaeng Sanballat hoi Ammon acaeng toksah angraeng Tobiah hnik mah, to lok to thaih hoi naah, Israel caanawk khosak qoengsak hanah, kami maeto angzoh boeh, tiah a thaih hoi pongah, paroeai poeknawm hoi ai.
11 Mo sì lọ sí Jerusalẹmu, lẹ́yìn ìgbà tí mo dúró níbẹ̀ fún ọjọ́ mẹ́ta.
Jerusalem ah ka caeh moe, to ah ni thumto ka cam pacoengah,
12 Mo jáde ní òru pẹ̀lú àwọn ọkùnrin díẹ̀. Èmi kò sì sọ fún ẹnìkankan ohun tí Ọlọ́run mi ti fi sí ọkàn mi láti ṣe fún Jerusalẹmu. Kò sí ẹranko kankan pẹ̀lú mi, bí kò ṣe ọ̀kan ṣoṣo tí mo gùn.
ka taengah kaom kami zetta hoi nawnto aqum ah kholong ka caeh o; Jerusalem ah toksak hanah Sithaw mah palung thungah ang suek pae ih hmuen to mi khaeah doeh ka thui ai; kang thueng ih hrang khue ai ah loe, kalah hrang om ai.
13 Ní òru, mo jáde lọ sí àfonífojì ibodè sí ìhà kànga Jakali àti sí ẹnu ibodè Ààtàn àti ẹnu ibodè rẹ̀ èyí tí ó ti wó odi Jerusalẹmu tí ó lulẹ̀, tí a ti fi iná sun.
Khoving naah azawn ih khongkha hoi Pahui tuikhaw taeng ih, Anghnoeng khongkha khoek to ka caeh moe, kamtimh Jerusalem tapangnawk hoi hmai mah kangh ih khongkhanawk to ka khet.
14 Nígbà náà ni mo lọ sí ẹnu ibodè orísun àti sí adágún omi ọba, ṣùgbọ́n kò sí ààyè tó fún ẹranko mi láti kọjá;
To pacoengah tuipuek ohhaih khongkha hoi siangpahrang ih tuili ohhaih bangah ka caeh poe; toe hrang caehhaih kakhawt ahmuen to om ai pongah,
15 bẹ́ẹ̀ ni mo gòkè àfonífojì ní òru, mo ń wo odi. Ní ìparí, mo padà sẹ́yìn, mo sì tún wọlé láti ibodè àfonífojì.
aqum ah azawn ah ka caeh moe, tapangnawk to ka khet; kam laem let, azawn bang ih khongkha hoiah ka kun moe, kam laem let.
16 Àwọn olórí kò mọ ibi tí mo lọ tàbí mọ ohun tí mo ń ṣe, nítorí èmi kò tí ì sọ fún àwọn ará Júù tàbí àwọn àlùfáà tàbí àwọn ọlọ́lá tàbí àwọn ìjòyè tàbí ẹnikẹ́ni mìíràn tí yóò máa ṣe iṣẹ́ náà.
Judahnawk, qaimanawk, araengh kasang angraengnawk, ukkungnawk hoi toksah kami, mi kawbaktih khaeah doeh lok ka thui pae ai pongah, naa ah maw ka caeh moe, timaw ka sak, tito ukkungnawk mah panoek o ai.
17 Nígbà náà ni mo sọ fún wọn pé, “Ṣé ẹ rí wàhálà tí a ni: Jerusalẹmu wà nínú ìparun, ibodè rẹ̀ ni a sì ti fi iná jó. Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a tún odi Jerusalẹmu mọ, àwa kò sì ní jẹ́ ẹni ẹ̀gàn mọ́”.
Kam laem let naah loe nihcae khaeah, ka tongh o ih raihaih, Jerusalem amrohaih, hmai mah khongkhanawk kangh boihhaih kawng to ka thuih pae. Angzo oh, kasae thuihaih hoiah a oh o han ai ah, Jerusalem tapang hae sah o let si boeh, tiah ka naa.
18 Èmi sì tún sọ fún wọn nípa bí ọwọ́ àánú Ọlọ́run mi ṣe wà lára mi àti ohun tí ọba ti sọ fún mi. Wọ́n dáhùn wí pé, “Ẹ jẹ́ kí a bẹ̀rẹ̀ àtúnmọ rẹ̀.” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rere yìí.
Sithaw tahmenhaih ka nuiah oh pongah, siangpahrang mah kai khaeah thuih ih loknawk to nihcae khaeah ka thuih pae naah, Nihcae mah, angthawk o si loe, sah o si boeh, tiah thuih o. To pongah tha pathok o moe, kahoih hae tok hae a sak amtong o.
19 Ṣùgbọ́n nígbà tí Sanballati ará a Horoni, Tobiah ara olóyè Ammoni àti Geṣemu ará a Arabia gbọ́ nípa rẹ̀, wọ́n fi wá ṣe ẹlẹ́yà, wọ́n sì fi wá ṣe ẹ̀sín. Wọ́n béèrè pé, “Kí ni èyí tí ẹ ń ṣe yìí? Ṣé ẹ ń ṣọ̀tẹ̀ sí ọba ni?”
Toe Horon kami Sanballat, Ammon kami angraeng Tobiah hoi Arab kami Geshem mah to lok to thaih o naah, kaicae to patoek moe, ang pahnuih hoi thuih. Timaw na sak o loe? Siangpahrang ih lok na aek o han maw? tiah ang naa hoi.
20 Mo dá wọn lóhùn, mo wí fún wọn pé, “Ọlọ́run ọ̀run yóò fún wa ní àṣeyọrí. Àwa ìránṣẹ́ rẹ̀ yóò bẹ̀rẹ̀ láti tún un mọ, ṣùgbọ́n fún un yin, ẹ̀yin kò ní ìpín tàbí ipa tàbí ẹ̀tọ́ ohunkóhun tí ó jẹ mọ́ ìtàn ní Jerusalẹmu.”
Kai mah nihcae khaeah, Kaicae loe van Sithaw mah qoeng sak tih; a tamna ah kaom kaicae loe angthawk moe, ka sak o han; toe nangcae loe Jerusalem ah qawktoep hanah taham na tawn o ai, sakthaihaih doeh na tawn o ai moe, pakuem han koi tidoeh na tawn o ai, tiah ka naa.