< Nahum 1 >

1 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ nípa Ninefe. Ìwé ìran Nahumu ará Elkoṣi.
Ĩno nĩyo ndũmĩrĩri nditũ ĩkoniĩ Nineve. Rĩĩrĩ nĩrĩo ibuku rĩa kĩoneki kĩa Nahumu, ũrĩa Mũelikoshi.
2 Ọlọ́run ń jẹ owú, ó sì ń gbẹ̀san, Olúwa ń gbẹ̀san, ó sì kún fún ìbínú. Olúwa ń gbẹ̀san lára àwọn ọ̀tá rẹ̀. Ìbínú rẹ̀ kò sì yí padà lórí àwọn ọ̀tá rẹ̀.
Jehova nĩ Mũrungu ũrĩ ũiru na mwĩrĩhĩria; Jehova nĩerĩhagĩria na akaiyũrwo nĩ mangʼũrĩ. Jehova nĩerĩhagĩria harĩ thũ ciake, na agatũũria mangʼũrĩ make harĩ amuku ake.
3 Olúwa lọ́ra láti bínú, ó sì tóbi ní agbára; Olúwa kì yóò fi àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ sílẹ̀ láìjìyà. Ọ̀nà rẹ̀ wà nínú afẹ́fẹ́ àti nínú ìjì, ìkùùkuu sánmọ̀ sì ni eruku ẹsẹ̀ rẹ̀.
Jehova ndahiũhaga kũrakara na nĩarĩ hinya mũnene; Jehova ndakaaga kũherithia mũndũ mwaganu. Njĩra yake ĩrĩ thĩinĩ wa rũhuho rũnene na thĩinĩ wa kĩhuhũkanio, matu namo nĩ rũkũngũ rwa makinya make.
4 Ó bá òkun wí, ó sì mú kí ó gbẹ; Ó sìsọ gbogbo odò di gbígbẹ. Baṣani àti Karmeli sì rọ. Ìtànná Lebanoni sì rẹ̀ sílẹ̀.
Akũũmaga iria, agatũma rĩhũe; ahũithagia njũũĩ ciothe. Bashani na Karimeli nĩkũhoohete, na kĩro kĩa Lebanoni gĩkaragatha.
5 Àwọn òkè ńlá wárìrì níwájú rẹ̀, àwọn òkè kéékèèké sì di yíyọ́, ilẹ̀ ayé sì jóná níwájú rẹ̀, àní ayé àti gbogbo àwọn tí ń gbé inú rẹ̀.
Irĩma ithingithaga mbere yake, natuo tũrĩma tũgatweka. Thĩ ĩinainaga ĩrĩ mbere yake, o na mabũrũri mothe makainaina, na arĩa othe matũũraga kuo.
6 Ta ni ó lé dúró níwájú ìbínú rẹ̀? Ta ni ó lé faradà gbígbóná ìbínú rẹ̀? Ìbínú rẹ̀ tú jáde bí iná; àwọn àpáta sì fọ́ túútúú níwájú rẹ̀.
Nũũ ũngĩĩtiiria mathirĩ make? Nũũ ũngĩkĩũmĩrĩria marakara make mahiũ? Mangʼũrĩ make-rĩ, maitĩkaga ta mwaki; ndwaro cia mahiga igathethereka mbere yake.
7 Rere ni Olúwa, òun ni ààbò ní ọjọ́ ìpọ́njú. Òun sì tọ́jú àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé e,
Jehova nĩ mwega, nĩ kĩĩhitho hĩndĩ ya thĩĩna. Arĩa mamwĩhokete-rĩ, nĩamamenyagĩrĩra,
8 ṣùgbọ́n pẹ̀lú ìkún omi ńlá ní òun yóò fi ṣe ìparun láti ibẹ̀ dé òpin; òkùnkùn yóò sì máa lépa àwọn ọ̀tá rẹ̀.
no rĩrĩ, nĩakaniina Nineve na kĩguũ kĩnene kĩa maaĩ; nĩakaingata thũ ciake nginya nduma-inĩ.
9 Kí ni ẹ̀yìn ń gbìmọ̀ lòdì sí Olúwa? Òun yóò fi òpin sí i, ìpọ́njú kì yóò wáyé ní ìgbà kejì.
Ũrĩa wothe magaaciirĩra gwĩka Jehova-rĩ, we nĩakaũniina; o na thĩĩna ndũgooka hĩndĩ ya keerĩ.
10 Wọn yóò sì lọ́lù papọ̀ bí ẹ̀gún òṣùṣú wọn yóò sì mu àmupara nínú ọtí wáìnì wọn a ó sì run wọn gẹ́gẹ́ bi àgékù koríko gbígbẹ.
Makaarigiicwo mĩigua-inĩ na marĩĩo nĩ ndibei yao; nao magaacinwo ta maragara momũ.
11 Láti ọ̀dọ̀ rẹ, ìwọ Ninefe, ni ẹnìkan ti jáde wá tí ó ń gbèrò ibi sí Olúwa ti ó sì ń gbìmọ̀ búburú.
Nĩ harĩ ũmwe wĩyumĩrĩtie thĩinĩ waku wee Nineve, ũrĩa ũthugundaga ũũru wa gũũkĩrĩra Jehova, na akaheanaga irĩra cia waganu.
12 Báyìí ni Olúwa wí: “Bí wọ́n tilẹ̀ ni ìfọwọ́sowọ́pọ̀, tí wọ́n sì pọ̀ níye, ṣùgbọ́n, báyìí ní a ó ké wọn lulẹ̀, nígbà tí òun ó bá kọjá. Bí mo tilẹ̀ ti pọ́n ọ lójú ìwọ Juda, èmi kì yóò pọ́n ọ lójúmọ́.
Jehova ekuuga atĩrĩ: “O na aakorwo marĩ na arata, na nĩ aingĩ mũno-rĩ, nĩmakaniinwo, meherio. O na aakorwo nĩngũnyariirĩte, wee Juda-rĩ, ndigacooka gũkũnyariira rĩngĩ.
13 Nísinsin yìí ni èmi yóò já àjàgà wọn kúrò ní ọrùn rẹ èmi yóò já ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ rẹ dànù.”
Na rĩrĩ, nĩnguunanga icooki rĩao riume ngingo-inĩ yaku, na nduange mĩnyororo ĩrĩa woheetwo nayo.”
14 Olúwa ti fi àṣẹ kan lélẹ̀ nítorí tìrẹ Ninefe: “Ìwọ kì yóò ni irú-ọmọ láti máa jẹ́ orúkọ rẹ mọ́, Èmi yóò pa ère fínfín àti ère dídà run tí ó wà nínú tẹmpili àwọn ọlọ́run rẹ. Èmi yóò wa ibojì rẹ, nítorí ẹ̀gbin ni ìwọ.”
Jehova nĩarutĩte watho ũgũkoniĩ, wee Nineve, akoiga atĩrĩ, “Ndũkagĩa na njiaro cia gũtũũria rĩĩtwa rĩaku. Nĩngananga mĩhianano ĩyo mĩicũhie o na ĩyo ya gũtwekio ĩrĩa ĩrĩ kũu hekarũ ya ngai ciaku. Nĩngũhaarĩria mbĩrĩra yaku, nĩgũkorwo ũrĩ kĩndũ kĩũru biũ.”
15 Wò ó, lórí àwọn òkè, àwọn ẹsẹ̀ ẹni tí ó mú ìròyìn ayọ̀ wá, ẹni tí ó ń kéde àlàáfíà. Ìwọ Juda, pa àṣẹ rẹ tí ó ní ìrònú mọ́, kí ó sì san àwọn ẹ̀jẹ́ rẹ. Àwọn ènìyàn búburú kì yóò sì gbóguntì ọ́ mọ́; wọn yóò sì parun pátápátá.
Ta cũthĩrĩriai kũũrĩa irĩma-igũrũ, muone magũrũ ma mũndũ ũrĩa ũrarehe ũhoro mwega, ũrĩa wanagĩrĩra thayũ! Wee Juda-rĩ, kũngũĩra ciathĩ ciaku, na ũhingie mĩĩhĩtwa yaku. Andũ aaganu matigagũtharĩkĩra rĩngĩ, nĩgũkorwo nĩmakaniinwo biũ.

< Nahum 1 >