< Nahum 1 >
1 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ nípa Ninefe. Ìwé ìran Nahumu ará Elkoṣi.
Wach Nyasaye kuom Nineve. Kitap fweny mar Nahum ja-Elkosh.
2 Ọlọ́run ń jẹ owú, ó sì ń gbẹ̀san, Olúwa ń gbẹ̀san, ó sì kún fún ìbínú. Olúwa ń gbẹ̀san lára àwọn ọ̀tá rẹ̀. Ìbínú rẹ̀ kò sì yí padà lórí àwọn ọ̀tá rẹ̀.
Jehova Nyasaye en Nyasaye ma janyiego kendo machulo kuor. Jehova Nyasaye chulo kuor kendo en gi mirima. Jehova Nyasaye chulo kuor ne joma kwede kendo kumne osiko kuom jowasike.
3 Olúwa lọ́ra láti bínú, ó sì tóbi ní agbára; Olúwa kì yóò fi àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ sílẹ̀ láìjìyà. Ọ̀nà rẹ̀ wà nínú afẹ́fẹ́ àti nínú ìjì, ìkùùkuu sánmọ̀ sì ni eruku ẹsẹ̀ rẹ̀.
Jehova Nyasaye iye ok wangʼ piyo kendo en gi teko maduongʼ. Jehova Nyasaye ok nowe joketho ma ok okumo. Yore moluwo ni ei kalausi gi ahiti, bende boche polo gin buch tiende.
4 Ó bá òkun wí, ó sì mú kí ó gbẹ; Ó sìsọ gbogbo odò di gbígbẹ. Baṣani àti Karmeli sì rọ. Ìtànná Lebanoni sì rẹ̀ sílẹ̀.
Ogolo chik to nam mi nam tuo, kendo aore duto dwono. Lege mabeyo mag Bashan gi Karmel tuo, kendo yiende mag Lebanon bende ner.
5 Àwọn òkè ńlá wárìrì níwájú rẹ̀, àwọn òkè kéékèèké sì di yíyọ́, ilẹ̀ ayé sì jóná níwájú rẹ̀, àní ayé àti gbogbo àwọn tí ń gbé inú rẹ̀.
Gode madongo yiengni e nyime kendo thuche leny nono. Piny tetni e nyime, piny kod ji duto madakie tetni.
6 Ta ni ó lé dúró níwájú ìbínú rẹ̀? Ta ni ó lé faradà gbígbóná ìbínú rẹ̀? Ìbínú rẹ̀ tú jáde bí iná; àwọn àpáta sì fọ́ túútúú níwájú rẹ̀.
Ere ngʼat manyalo siro mirimbe? Koso en ngʼa manyalo siro mirimbe mager? Mirimbe mager oolo mana ka mach. Lwendni barore e nyime.
7 Rere ni Olúwa, òun ni ààbò ní ọjọ́ ìpọ́njú. Òun sì tọ́jú àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé e,
Jehova Nyasaye ber, Jehova Nyasaye e kar pondo e kinde mag chandruok, orito joma ogeno kuome.
8 ṣùgbọ́n pẹ̀lú ìkún omi ńlá ní òun yóò fi ṣe ìparun láti ibẹ̀ dé òpin; òkùnkùn yóò sì máa lépa àwọn ọ̀tá rẹ̀.
Nineve to obiro ywero, gi ohula maduongʼ motiek chuth; obiro lawo joma kwede nyaka e mudho mandiwa.
9 Kí ni ẹ̀yìn ń gbìmọ̀ lòdì sí Olúwa? Òun yóò fi òpin sí i, ìpọ́njú kì yóò wáyé ní ìgbà kejì.
Gimoro amora marach ma gichano timo ni Jehova Nyasaye obiro tieko; bende chandruok ok nobedie kendo.
10 Wọn yóò sì lọ́lù papọ̀ bí ẹ̀gún òṣùṣú wọn yóò sì mu àmupara nínú ọtí wáìnì wọn a ó sì run wọn gẹ́gẹ́ bi àgékù koríko gbígbẹ.
Gibiro moko e kind kuthe kendo gibiro mer gi divai mag-gi, bende ibiro wangʼ-gi ka lum motwo.
11 Láti ọ̀dọ̀ rẹ, ìwọ Ninefe, ni ẹnìkan ti jáde wá tí ó ń gbèrò ibi sí Olúwa ti ó sì ń gbìmọ̀ búburú.
Ngʼat machano gik maricho kuom Jehova Nyasaye wuok mana kuomi, yaye Nineve, en e ngʼat mamiyo ji donjo e ketho.
12 Báyìí ni Olúwa wí: “Bí wọ́n tilẹ̀ ni ìfọwọ́sowọ́pọ̀, tí wọ́n sì pọ̀ níye, ṣùgbọ́n, báyìí ní a ó ké wọn lulẹ̀, nígbà tí òun ó bá kọjá. Bí mo tilẹ̀ ti pọ́n ọ lójú ìwọ Juda, èmi kì yóò pọ́n ọ lójúmọ́.
Jehova Nyasaye wacho kama: “Kata obedo ni gingʼeny kendo gin gi joma konyogi, ibiro ngʼad kargi oko mi gilal nono. Kata obedo ni asesandi, yaye Juda, ok anachak sandi kendo.
13 Nísinsin yìí ni èmi yóò já àjàgà wọn kúrò ní ọrùn rẹ èmi yóò já ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ rẹ dànù.”
Koro abiro turo jok ma giketo e ngʼuti kendo abiro chodo nyororo motweyigo.”
14 Olúwa ti fi àṣẹ kan lélẹ̀ nítorí tìrẹ Ninefe: “Ìwọ kì yóò ni irú-ọmọ láti máa jẹ́ orúkọ rẹ mọ́, Èmi yóò pa ère fínfín àti ère dídà run tí ó wà nínú tẹmpili àwọn ọlọ́run rẹ. Èmi yóò wa ibojì rẹ, nítorí ẹ̀gbin ni ìwọ.”
Jehova Nyasaye osegolo chik kuomi, in Nineve, kowacho niya: “Ok inibed gi nyikwayi mabiro tingʼo nyingi. Abiro tieko nyisecheu manono mopa kaachiel gi mochwe gi lowo manie uteu mag lemo. Abiro kunyonu bur miyikoue nikech un joma timbegi richo.”
15 Wò ó, lórí àwọn òkè, àwọn ẹsẹ̀ ẹni tí ó mú ìròyìn ayọ̀ wá, ẹni tí ó ń kéde àlàáfíà. Ìwọ Juda, pa àṣẹ rẹ tí ó ní ìrònú mọ́, kí ó sì san àwọn ẹ̀jẹ́ rẹ. Àwọn ènìyàn búburú kì yóò sì gbóguntì ọ́ mọ́; wọn yóò sì parun pátápátá.
Tingʼ wangʼi, ineye tiende ngʼat makelo Injili, kendo malando kwe ewi gode! Tim nyasi mar mor, yaye Juda, chopuru singruoku. Jomaricho ok nochak omonju kendo; nikech ibiro tiekgi pep.