< Micah 7 >
1 Ègbé ni fún mi! Nítorí èmi sì dàbí ẹni tí ń kó èso ẹ̀ẹ̀rùn jọ, ìpèsè ọgbà àjàrà; kò sì ṣí odidi àjàrà kankan láti jẹ, kò sì ṣí àkọ́so ọ̀pọ̀tọ́ nítorí tí ebi ń pa mí.
Kai loe khosak bing boeh! Kai loe nipui tue ah pakhrik ih thingthai baktih, misurtui takha thung ih misurthaih kanghmat baktiah ni ka oh boeh; caak han misurthaih om ai, ka caak han koeh ih athai tangsuek thingthai doeh om ai.
2 Àwọn olódodo sì ti kúrò ní ilẹ̀ náà, kò sì ṣí ẹnìkan tí ó ṣẹ́kù tí ó jọ olóòtítọ́; gbogbo wọn sì ń purọ́ ní dídúró nítorí ìtàjẹ̀ sílẹ̀, olúkúlùkù wọ́n sì ń fi àwọ̀n de arákùnrin rẹ̀.
Kahoih kaminawk loe long nui hoi anghmat o boih boeh; kaminawk thungah katoeng kami maeto doeh om ai boeh: kaminawk boih athii palong hanah kami to angang o; kami maeto boih mah angmah ih nawkamya to palok hoiah amee o.
3 Ọwọ́ wọn méjèèjì ti múra tán láti ṣe búburú; àwọn alákòóso ń béèrè fún ẹ̀bùn, àwọn onídàájọ́ sì ń gba owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ alágbára sì ń pàṣẹ ohun tí wọ́n fẹ́, gbogbo wọn sì jùmọ̀ ń dìtẹ̀.
Ban loe kahoih ai hmuen sak han kop, ukkungnawk loe tangqum to hnik o, lokcaekkungnawk doeh bokhaih phoisa to caak o; kalen kaminawk loe koeh ih hmuen to hnik o, nihcae loe to tiah nawnto toksak o.
4 Ẹni tí ó sàn jùlọ nínú wọn sì dàbí ẹ̀gún, ẹni tí ó jẹ́ olódodo jùlọ burú ju ẹ̀gún ọgbà lọ. Ọjọ́ àwọn olùṣọ́ rẹ̀ ti dé, àti ọjọ́ tí Ọlọ́run bẹ̀ ọ́ wò. Nísinsin yìí ní àkókò ìdààmú wọn.
Nihcae thung ih kahoih koek kami loe soekhring hoiah anghmong; katoeng koek kami mataeng doeh takha pakaahaih soekhring pongah noet kue; nang toepkungnawk ih ani hoi na paqaihhaih ani loe angzoh boeh; vaihi loe nihcae han anghmang thok atue ah oh.
5 Ẹ má ṣe gba ọ̀rẹ́ kan gbọ́; ẹ má sì ṣe gbẹ́kẹ̀lé amọ̀nà kankan. Pa ìlẹ̀kùn ẹnu rẹ fún ẹni tí ó sùn ní oókan àyà rẹ.
Ampui to oep hmah, loklam patuek kami khaeah amha hmah; na saoek ah amha nongpata khaeah thuih ih lok to angsum ah.
6 Nítorí tí ọmọkùnrin kò bọ̀wọ̀ fún baba rẹ̀, ọmọbìnrin sì dìde sí ìyá rẹ̀, aya ọmọ sí ìyá ọkọ rẹ̀, ọ̀tá olúkúlùkù ni àwọn ará ilé rẹ̀.
Capa mah ampa to saiqat ai, canu mah amno to misa ah suek, langah mah amni to misa ah suek; misa kaom kami loe angmah imthung takoh kaminawk to ni.
7 Ṣùgbọ́n ní tèmi, èmi ní ìwòye ní ìrètí sí Olúwa, èmi dúró de Ọlọ́run olùgbàlà mi; Ọlọ́run mi yóò sì tẹ́tí sí mi.
To pongah Angraeng to ka khet han, kai pahlonghaih Sithaw to ka zing han; ka Sithaw mah na tahngai pae tih.
8 Má ṣe yọ̀ mí, ìwọ ọ̀tá mi. Bí mó bá ṣubú, èmi yóò dìde. Nígbà tí mo bá jókòó sínú òkùnkùn Olúwa yóò jẹ́ ìmọ́lẹ̀ fún mi.
Ka misa nang, ka nuiah anghoe hmah; kai loe amtimh cadoeh, kang thawk let han; vinghaih thungah ka oh cadoeh, Angraeng loe kai aanghaih ah om tih.
9 Nítorí èmi ti dẹ́ṣẹ̀ sí i, èmi yóò faradà ìbínú Olúwa, títí òun yóò ṣe gba ẹjọ́ mi rò, tí yóò sì ṣe ìdájọ́ mi. Òun yóò sì mú mi wá sínú ìmọ́lẹ̀; èmi yóò sì rí òdodo rẹ̀.
A nuiah ka zae boeh pongah, anih mah kai kawng to thuih moe, kai han lok takroekhaih sah ai karoek to, Angraeng palungphuihaih to ka pauep han: Anih mah aanghaih thungah na caehhaih ueloe, a toenghaih to ka hnu tih.
10 Nígbà náà ni ọ̀tá mi yóò rí i ìtìjú yóò sì bo ẹni tí ó wí fún mi pé, “Níbo ni Olúwa Ọlọ́run rẹ wà?” Ojú mi yóò rí ìṣubú rẹ̀; nísinsin yìí ni yóò di ìtẹ̀mọ́lẹ̀ bí ẹrẹ̀ òpópó.
To pacoengah kai khaeah, Na Angraeng Sithaw loe naa ah maw oh? tiah kathui ka misa mah hnu tih, to naah anih loe azathaih mah muek tih, ka mik mah anih to hnu tih; anih loe vaihi loklam ih tangkrok baktiah khok hoiah cawh tih boeh.
11 Ọjọ́ tí a ó mọ odi rẹ yóò dé, ọjọ́ náà ni àṣẹ yóò jìnnà réré.
Nang ih sipae sakhaih ani to angzo tih, to na niah loe na prae to kawk tih boeh.
12 Ní ọjọ́ náà àwọn ènìyàn yóò wá sọ́dọ̀ rẹ láti Asiria àti ìlú ńlá Ejibiti àní láti Ejibiti dé Eufurate láti Òkun dé Òkun àti láti òkè ńlá dé òkè ńlá.
To na niah loe Assyria, kacak Izip vangpuinawk, kacak Izip vangpui hoi tuipui karoek to, tuipui maeto hoi maeto khoek to, mae hae bang hoi ho bangah kaom kaminawk to nang khaeah angzo o tih.
13 Ilẹ̀ náà yóò di ahoro fún àwọn olùgbé inú rẹ̀, nítorí èso ìwà wọn.
To tiah om cadoeh, a sak o ih athaih baktih toengah, a thungah kaom kaminawk pongah prae to pahnawt sut tih boeh.
14 Fi ọ̀pá rẹ bọ́ àwọn ènìyàn, agbo ẹran ìní rẹ, èyí tí ó ń dágbé nínú igbó ní àárín Karmeli. Jẹ́ kí wọn jẹun ní Baṣani àti Gileadi bí ọjọ́ ìgbàanì.
Taw ah kaom, Karmel mae ih qawk ah na toep ih tuunawk hoi nangmah ih kaminawk to nangmah ih cunghet hoiah toep ah; canghnii ah sak ih baktih toengah, nihcae to pacah hanah Bashan hoi Gilead ah caeh haih ah.
15 “Bí i ọjọ́ tí ó jáde kúrò ní Ejibiti wá, ni èmi yóò fi ohun ìyanu hàn án.”
Izip prae thung hoi nang zoh o nathuem ih baktih toengah, nihcae han dawnrai hmuennawk to ka patuek han.
16 Orílẹ̀-èdè yóò rí i, ojú yóò sì tì wọ́n, nínú gbogbo agbára wọn. Wọn yóò fi ọwọ́ lé ẹnu wọn, etí wọn yóò sì di.
Prae kaminawk mah hnuk o naah dawnrai o ueloe, angmacae ih misatuh kaminawk to azat o haih tih; nihcae mah pakha to ban hoi tamuep o tih, lok apae o thai mak ai.
17 Wọn yóò lá erùpẹ̀ bí ejò, wọn yóò sì jáde kúrò nínú ihò wọn bí ekòló. Wọn yóò bẹ̀rù Olúwa Ọlọ́run wa, wọn yóò sì bẹ̀rù nítorí rẹ̀.
Nihcae loe long ah kavak sadong baktiah akhaw thung hoiah tacawt o ueloe, pahui baktiah long to palaek o tih: nang to zii o ueloe, kaicae ih Angraeng Sithaw doeh zii o tih.
18 Ta ni Ọlọ́run bí rẹ̀, ẹni tí ó dárí ẹ̀ṣẹ̀ jì, tí ó sì fojú fo ìrékọjá èyí tókù ìní rẹ̀? Kì í dúró nínú ìbínú rẹ̀ láéláé nítorí òun ní inú dídùn sí àánú.
Anih mah palungnathaih amtuengsak han koeh pongah, palungphui poe ai, zaehaih to tahmen moe, kanghmat angmah ih qawktoep kaminawk sapazaehaih tahmen nang baktih Sithaw mi maw kaom?
19 Òun yóò tún padà yọ́nú sí wa; òun yóò tẹ àwọn ẹ̀ṣẹ̀ wa mọ́lẹ̀, yóò sì fa gbogbo àìṣedéédéé wa sínú ibú Òkun.
Anih loe kaicae nuiah amlunghaih tawn let ueloe, kaicae zaehaihnawk to anih mah payawk tih: kaicae zaehaihnawk to kathuk tuipui thungah na va pae tih.
20 Ìwọ yóò fi òtítọ́ hàn sí Jakọbu ìwọ yóò sì fi àánú hàn sí Abrahamu, bí ìwọ ṣe búra fún àwọn baba wa láti ọjọ́ ìgbàanì.
Canghnii ah kam panawk khaeah lok na kam ih baktih toengah, Jakob khaeah loktang to nam tuengsak ueloe, Abraham khaeah palungnathaih na tawn poe tih.