< Micah 7 >

1 Ègbé ni fún mi! Nítorí èmi sì dàbí ẹni tí ń kó èso ẹ̀ẹ̀rùn jọ, ìpèsè ọgbà àjàrà; kò sì ṣí odidi àjàrà kankan láti jẹ, kò sì ṣí àkọ́so ọ̀pọ̀tọ́ nítorí tí ebi ń pa mí.
Na da da: i dioi bagadedafa! Na da ha: i bagade dunu amo da ifa dulu ganabeyale amola waini fage ganabeyale hogole ba: sea, hame ba: sea, da: i diosu agoai galebe. Waini fage amola figi fage hedai nasu huluane da enoga fai dagoi.
2 Àwọn olódodo sì ti kúrò ní ilẹ̀ náà, kò sì ṣí ẹnìkan tí ó ṣẹ́kù tí ó jọ olóòtítọ́; gbogbo wọn sì ń purọ́ ní dídúró nítorí ìtàjẹ̀ sílẹ̀, olúkúlùkù wọ́n sì ń fi àwọ̀n de arákùnrin rẹ̀.
Isala: ili soge amo ganodini da moloidafa dunu afae hame gala. Amola Godema noga: le madelagi dunu afae hame gala. Dunu huluanedafa da medole legemusa: logo hogosa. Dunu huluanedafa da hina: fidafa dunu fane legemusa: desega ahoa.
3 Ọwọ́ wọn méjèèjì ti múra tán láti ṣe búburú; àwọn alákòóso ń béèrè fún ẹ̀bùn, àwọn onídàájọ́ sì ń gba owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ alágbára sì ń pàṣẹ ohun tí wọ́n fẹ́, gbogbo wọn sì jùmọ̀ ń dìtẹ̀.
Ilia huluane da wadela: i hou obenanewane hamonanumusa: dawa: Eagene ouligisu dunu amola fofada: su ouligisu dunu huluane da hano suligili adole ba: sa. Mimogo dunu da ilia hanai ilima adosa. Amaiba: le, ilia huluane da gilisili wadela: le ilegele sia: daha.
4 Ẹni tí ó sàn jùlọ nínú wọn sì dàbí ẹ̀gún, ẹni tí ó jẹ́ olódodo jùlọ burú ju ẹ̀gún ọgbà lọ. Ọjọ́ àwọn olùṣọ́ rẹ̀ ti dé, àti ọjọ́ tí Ọlọ́run bẹ̀ ọ́ wò. Nísinsin yìí ní àkókò ìdààmú wọn.
Amo wadela: i hamosu dunu gilisisu ganodini dunu afae afae da fonobahadi noga: i. Be ilia amola da wadela: i aya: gaga: nomei gisi defele, wadela: idafa. Gode da musa: ilia sosodo aligisu dunu ilia lafidili ilima dawa: digima: ne sisasu. Be ilia da hame nabi. Amaiba: le, eso da misi amoga E da ilima se imunu. Wali ilia da gagaoududala.
5 Ẹ má ṣe gba ọ̀rẹ́ kan gbọ́; ẹ má sì ṣe gbẹ́kẹ̀lé amọ̀nà kankan. Pa ìlẹ̀kùn ẹnu rẹ fún ẹni tí ó sùn ní oókan àyà rẹ.
Dia na: iyado amola dia sama ilia sia: amo dafawaneyale mae dawa: ma! Digoama amola diaudama, ilia da di hohonosa: besa: le, dawa: iwane sia: ma!
6 Nítorí tí ọmọkùnrin kò bọ̀wọ̀ fún baba rẹ̀, ọmọbìnrin sì dìde sí ìyá rẹ̀, aya ọmọ sí ìyá ọkọ rẹ̀, ọ̀tá olúkúlùkù ni àwọn ará ilé rẹ̀.
Wali eso amoga, dunu mano ilia da ilia eda gagaoui dunu agoai ba: sa. Uda mano ilia da emema hagale besia: sa. Uda a: fini da egoamema sia: ga gegesa. Amola dia sosogo fidafa da dima ha lai dagoi.
7 Ṣùgbọ́n ní tèmi, èmi ní ìwòye ní ìrètí sí Olúwa, èmi dúró de Ọlọ́run olùgbàlà mi; Ọlọ́run mi yóò sì tẹ́tí sí mi.
Be na da Hina Gode na fidila misa: ne, oulelumu. Na da Hina Gode na gaga: ma: ne, na da denesini gebewane ouesalumu. Na Gode da na wele sia: be nabimu.
8 Má ṣe yọ̀ mí, ìwọ ọ̀tá mi. Bí mó bá ṣubú, èmi yóò dìde. Nígbà tí mo bá jókòó sínú òkùnkùn Olúwa yóò jẹ́ ìmọ́lẹ̀ fún mi.
Ninima ha lai dunu da ninima da: da: lole sia: mu da bai hame gala. Nini da dafai dagoi be bu wa: legadomu. Ninia da wali gasi ganodini esala. Be Hina Gode da ninima hadigi imunu galebe.
9 Nítorí èmi ti dẹ́ṣẹ̀ sí i, èmi yóò faradà ìbínú Olúwa, títí òun yóò ṣe gba ẹjọ́ mi rò, tí yóò sì ṣe ìdájọ́ mi. Òun yóò sì mú mi wá sínú ìmọ́lẹ̀; èmi yóò sì rí òdodo rẹ̀.
Ninia da Hina Godema wadela: le hamoi. Amaiba: le, ninia da Ea ougi hou wahamusu ba: sa esalumu. Be fa: no dagomusa: , E da nini gaga: mu. Amola ninima wadela: le hamosu dunu amo ilima fofada: ne, ninia moloidafa hou mimogoa heda: mu. E da nini hadigi amoga oule misunu. Ninia da mae bogole esaleawane, Ea gaga: su ba: mu.
10 Nígbà náà ni ọ̀tá mi yóò rí i ìtìjú yóò sì bo ẹni tí ó wí fún mi pé, “Níbo ni Olúwa Ọlọ́run rẹ wà?” Ojú mi yóò rí ìṣubú rẹ̀; nísinsin yìí ni yóò di ìtẹ̀mọ́lẹ̀ bí ẹrẹ̀ òpópó.
Amasea, ninima ha lai dunu da amo hou ba: sea, ilia da gogosiamu. Amo ha lai dunu da musa: ninima amane dodona: gini sia: su, “Dilia Hina Gode da habila: ?” Ninia da ili hasalasi dagoi ba: mu. Ilia da logoba: le ahoana, fafu ososa: gi agoai ba: mu.
11 Ọjọ́ tí a ó mọ odi rẹ yóò dé, ọjọ́ náà ni àṣẹ yóò jìnnà réré.
Yelusaleme fi dunu, dilia! Dilia moilai bai bagade gagoi bu gagomu eso da mana. Amo esoha, dilia soge alalo da ga gasigamu.
12 Ní ọjọ́ náà àwọn ènìyàn yóò wá sọ́dọ̀ rẹ láti Asiria àti ìlú ńlá Ejibiti àní láti Ejibiti dé Eufurate láti Òkun dé Òkun àti láti òkè ńlá dé òkè ńlá.
Dilia fi dunu soge enodini esafulu, da dilima gagadola misunu. Ilia da Asilia (gusudili soge) amola Idibidi (ga [south] soge) amola Iufala: idisi Hano soge amola hano wayabo bagade soge badiliadafa gala amola goumi soge badiliadafa gala, amo sogeganini ilia da dilima gagadola misunu.
13 Ilẹ̀ náà yóò di ahoro fún àwọn olùgbé inú rẹ̀, nítorí èso ìwà wọn.
Be dunu fi amo da osobo bagadega esala, ilia da baligili wadela: le hamonanebeba: le, osobo bagade da bu hafoga: i wadela: idafa soge agoane hamomu.
14 Fi ọ̀pá rẹ bọ́ àwọn ènìyàn, agbo ẹran ìní rẹ, èyí tí ó ń dágbé nínú igbó ní àárín Karmeli. Jẹ́ kí wọn jẹun ní Baṣani àti Gileadi bí ọjọ́ ìgbàanì.
Hina Gode! Dia fi dunu amo Di da ilegei, amo ilima sibi ouligisu defele ouligima! Ilia da wadela: i hafoga: i soge amo ganodini esala. Be ili sisiga: le da nasegagi soge noga: i diala. Ilia da musa: hamoi defele, Ba: isia: ne amola Gilia: de nasegagi gisi soge amoga ha: i na masa: ne, logo doasima.
15 “Bí i ọjọ́ tí ó jáde kúrò ní Ejibiti wá, ni èmi yóò fi ohun ìyanu hàn án.”
Hina Gode! Di da nini Idibidi sogega fisili masa: ne oule ahoanoba, nini fidima: ne, musa: hame ba: su gasa bagade hou hamosu. Amo defele, nini fidima: ne bu hamoma!
16 Orílẹ̀-èdè yóò rí i, ojú yóò sì tì wọ́n, nínú gbogbo agbára wọn. Wọn yóò fi ọwọ́ lé ẹnu wọn, etí wọn yóò sì di.
Fifi asi gala eno da gasa bagade gala. Be ilia da Dia gasa bagade musa: hame ba: su hou ba: sea, ilia hamomu logo ga: iba: le, gogosiamu. Ilia da beda: iba: le, lafi gaduli fimu, amola ge ga: le esalumu.
17 Wọn yóò lá erùpẹ̀ bí ejò, wọn yóò sì jáde kúrò nínú ihò wọn bí ekòló. Wọn yóò bẹ̀rù Olúwa Ọlọ́run wa, wọn yóò sì bẹ̀rù nítorí rẹ̀.
Ilia da sania agoane gulu da: iya sugi masunu. Ilia da ilia gagili sali moilai amo fisili, beda: ga yagugusa misunu. Ilia da beda: iba: le, ninia Hina Godema sinidigimu.
18 Ta ni Ọlọ́run bí rẹ̀, ẹni tí ó dárí ẹ̀ṣẹ̀ jì, tí ó sì fojú fo ìrékọjá èyí tókù ìní rẹ̀? Kì í dúró nínú ìbínú rẹ̀ láéláé nítorí òun ní inú dídùn sí àánú.
Hina Gode! Di agoai eno ‘gode’ da hamedafa gala. Di da Dia fi dunu hame bogoi esalebe, ilia wadela: i hou gogolema: ne olofosa. Di da ougisa, be gebewane ougi hame diala. Be Di da Dia mae fisili asigidafa hou amo ninima hahawane olelelala.
19 Òun yóò tún padà yọ́nú sí wa; òun yóò tẹ àwọn ẹ̀ṣẹ̀ wa mọ́lẹ̀, yóò sì fa gbogbo àìṣedéédéé wa sínú ibú Òkun.
Di da ninima bu olofole asigidafa hou hamonanumu. Di da fedege agoane, ninia wadela: i hou Dia emoga ososa: gilalu, hano wayabo bagade osoga gududafa sanasimu!
20 Ìwọ yóò fi òtítọ́ hàn sí Jakọbu ìwọ yóò sì fi àánú hàn sí Abrahamu, bí ìwọ ṣe búra fún àwọn baba wa láti ọjọ́ ìgbàanì.
Dia fi dunu da A: ibalaha: me amola Ya: igobe elagaga fifi misi esala. Di da ninia aowalali amo ilima mae fisili asigidafa hou hamoma: ne ilegele sia: i. Ninia dawa: Di da amo mae fisili asigidafa hou ninima hamonanumu. Sia: ama dagoi

< Micah 7 >