< Micah 4 >

1 Ní ọjọ́ ìkẹyìn a ó fi òkè ilé Olúwa lélẹ̀ lórí àwọn òkè ńlá, a ó sì gbé e ga ju àwọn òkè kéékèèké lọ, àwọn ènìyàn yóò sì máa wọ̀ sínú rẹ̀.
Matukũ-inĩ ma kũrigĩrĩria, kĩrĩma kĩrĩa kĩa hekarũ ya Jehova nĩgĩkahaandwo kĩrĩ kĩo kĩnene gatagatĩ ka irĩma iria ingĩ; nĩgĩkambarario igũrũ rĩa tũrĩma tũrĩa tũngĩ, nao andũ a ndũrĩrĩ nĩkuo magaathiiaga.
2 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè yóò wá, wọn yóò sì wí pé, “Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí á gòkè ńlá Olúwa, àti sí ilé Ọlọ́run Jakọbu. Òun yóò sì kọ́ wa ní ọ̀nà rẹ̀, kí àwa kí ó lè rìn ní ọ̀nà rẹ̀.” Òfin yóò jáde láti Sioni wá, àti ọ̀rọ̀ Olúwa láti Jerusalẹmu.
Ndũrĩrĩ nyingĩ igaathiĩ kuo, ikiugaga atĩrĩ, “Ũkai twambate tũthiĩ kĩrĩma‑inĩ kĩa Jehova, tũthiĩ nyũmba ya Ngai wa Jakubu. Nĩagatũruta ũhoro wa mĩthiĩre yake, nĩgeetha tũgeragĩre njĩra ciake.” Nĩgũkorwo Zayuni nĩgũkoima ũtaarani, nakuo Jerusalemu kuume ndũmĩrĩri ya Jehova.
3 Òun yóò sì ṣe ìdájọ́ láàrín ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn, yóò sì parí aáwọ̀ fún orílẹ̀-èdè alágbára jíjìn réré. Wọn yóò sì fi idà wọn rọ ohun èlò ìtulẹ̀ àti ọ̀kọ̀ wọn di dòjé orílẹ̀-èdè kì yóò gbé idà sókè sí orílẹ̀-èdè mọ́, bẹ́ẹ̀ ni wọn kì yóò kọ́ ogun jíjà mọ́.
Nĩagatuithania ndũrĩrĩ nyingĩ ciira, nacio ndũrĩrĩ iria irĩ hinya cia kuuma kũraya aciiguithanie. Magaatura hiũ ciao cia njora ituĩke hiũ cia mĩraũ, namo matimũ mao maturwo hiũ cia gũceeha mĩtĩ. Gũtirĩ rũrĩrĩ rũgaacooka kũrũa na rũrĩa rũngĩ na hiũ cia njora, kana rũcooke kwĩruta ũhoro wa mbaara rĩngĩ.
4 Ṣùgbọ́n olúkúlùkù yóò jókòó lábẹ́ àjàrà rẹ̀ àti lábẹ́ igi ọ̀pọ̀tọ́ rẹ̀, ẹnìkan kì yóò sì dẹ́rùbà wọ́n, nítorí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti sọ̀rọ̀.
O mũndũ agaikaraga gĩtina-inĩ kĩa mũthabibũ wake na aikarage gĩtina-inĩ kĩa mũkũyũ wake, na gũtirĩ mũndũ ũkaamamakia, nĩgũkorwo ũguo nĩguo Jehova Mwene-Hinya-Wothe oigĩte.
5 Gbogbo àwọn ènìyàn ń rìn, olúkúlùkù ni orúkọ ọlọ́run tirẹ̀, ṣùgbọ́n àwa yóò máa rìn ní orúkọ Olúwa. Ọlọ́run wa láé àti láéláé.
Andũ a ndũrĩrĩ ciothe no marũmĩrĩre kĩrĩra kĩa ngai ciao; no ithuĩ tũrĩrũmagĩrĩra kĩrĩra kĩa Jehova Ngai witũ nginya tene na tene.
6 “Ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa wí, “Èmi yóò kó àwọn arọ jọ; èmi yóò sì ṣà àwọn tí a lé kúrò ní ìlú jọ, àti àwọn ẹni tí èmi ti pọ́n lójú.
Jehova ekuuga atĩrĩ: “Mũthenya ũcio-rĩ, nĩngacookanĩrĩria ithua; na nĩngacookanĩrĩria arĩa matahĩtwo, o na arĩa nyariirithĩtie.
7 Èmi yóò dá àwọn arọ sí fún èyí tókù, èmi yóò sì sọ àwọn tí a lé kúrò ní ìlú di orílẹ̀-èdè alágbára. Olúwa yóò sì jẹ ọba lórí wọn ní òkè ńlá Sioni láti ìsinsin yìí lọ àti títí láéláé.
Ithua nĩngacitua matigari, na arĩa maingatĩtwo ndĩmatue rũrĩrĩ rũrĩ hinya. Jehova nĩwe ũkamaathaga arĩ Kĩrĩma-inĩ gĩa Zayuni, kuuma mũthenya ũcio nginya tene.
8 Ní ti ìwọ, ilé ìṣọ́ agbo àgùntàn, odi alágbára ọmọbìnrin Sioni, a ó mú ìjọba ìṣáájú padà bọ̀ sípò fún un yín; ìjọba yóò sì wà sí ọ̀dọ̀ ọmọbìnrin Jerusalẹmu.”
Ha ũhoro waku, wee mũthiringo ũyũ mũraihu na igũrũ wa kũrangĩra rũũru rwa mbũri, o wee kĩĩhitho kĩrũmu kĩa Mwarĩ wa Zayuni-rĩ, wathani ũrĩa warĩ naguo mbere nĩũgagũcookerera; naguo ũthamaki wa Mwarĩ wa Jerusalemu ũmũcookerere.”
9 Kí ni ìwọ ha ń kígbe sókè sí nísinsin yìí? Ǹjẹ́ ìwọ kò ní ọba bí? Àwọn ìgbìmọ̀ rẹ ṣègbé bí? Nítorí ìrora ti dì ọ́ mú bí obìnrin tí ń rọbí.
Atĩrĩrĩ, nĩkĩ kĩratũma ũrĩre wanĩrĩire, kaĩ ũtarĩ na mũthamaki? Kaĩ ũkuĩrĩirwo nĩ mũkũhei kĩrĩra, tondũ wanyiitwo nĩ ruo rũhaana ta rwa mũndũ-wa-nja akĩrũmwo?
10 Máa yí síyìn-ín sọ́hùn-ún nínú ìrora, ìwọ obìnrin Sioni, bí ẹni tí ń rọbí, nítorí nísinsin yìí ìwọ yóò jáde lọ kúrò ní ìlú, ìwọ yóò sì máa gbé inú igbó. Ìwọ yóò lọ sí Babeli; níbẹ̀ ni ìwọ yóò sì ti rí ìgbàlà. Níbẹ̀ ni Olúwa yóò ti rà ọ́ padà kúrò lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá rẹ.
Wĩnyogonde nĩ ruo, wee Mwarĩ wa Zayuni, o ta mũndũ-wa-nja akĩrũmwo, nĩgũkorwo rĩu no nginya uume itũũra inene ũgaikare nja werũ-inĩ. Nĩũgathiĩ Babuloni; kũu nĩkuo ũkaahonokerio. Kũu nĩkuo Jehova agaagũkũũra kuuma guoko-inĩ gwa thũ ciaku.
11 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ọ̀pọ̀lọpọ̀ Orílẹ̀-èdè kó ara wọn jọ sí ọ. Wọ́n sì wí pé, “Ẹ jẹ́ kí a sọ ọ́ di àìmọ́, ẹ jẹ́ kí ojú wa kí ó wo Sioni!”
No rĩrĩ, ndũrĩrĩ nyingĩ nĩicookanĩrĩire, igũũkĩrĩre. Iroiga atĩrĩ, “Rekei anyiitwo nĩ thaahu, rekei maitho maitũ mathekerere Zayuni!”
12 Ṣùgbọ́n wọn kò mọ èrò inú Olúwa; bẹ́ẹ̀ ni òye ìmọ̀ rẹ̀ kò yé wọn, nítorí ó ti kó wọn jọ bí i ìtí sínú ìpakà.
No cio itingĩmenya meciiria ma Jehova; o na itiũĩ mũbango wake, o we ũrĩa ũcicookanagĩrĩria ta itĩĩa cia ngano kĩhũrĩro-inĩ.
13 “Dìde, kí ó sì máa pa ọkà ìwọ ọmọbìnrin Sioni, nítorí èmi yóò sọ ìwo rẹ̀ di irin, èmi yóò sì sọ pátákò rẹ̀ di idẹ ìwọ yóò run ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè pátápátá.” Èmi yóò sì ya èrè wọn sọ́tọ̀ fún Olúwa àti ọrọ̀ wọn sí Olúwa gbogbo ayé.
“Arahũka, wee Mwarĩ wa Zayuni, ũhũũre ngano ĩyo, nĩgũkorwo nĩngakũhe hĩa cia kĩgera; nĩngakũhe mahũngũ ma gĩcango nawe nĩũkahehenja ndũrĩrĩ nyingĩ.” Uumithio ũcio meyoeire na njĩra ĩtarĩ ya kĩhooto nĩũkawamũrĩra Jehova, ũtonga wao ũwamũrĩre Mwathani wa thĩ yothe.

< Micah 4 >