< Micah 2 >

1 Ègbé ni fún àwọn tí ń gbèrò àìṣedéédéé tí wọ́n sì ń ṣiṣẹ́ ibi lórí ibùsùn wọn! Nígbà tí ojúmọ́ bá mọ́, wọn yóò gbé e jáde nítorí ó wà ní agbára wọn láti ṣe é.
Angsonghaih iihkhun nui hoi kasae sak han pacaeng kaminawk loe khosak bing o! Nihcae loe to baktih hmuen sak thaihaih tawnh o pongah, akhawnbang khodai naah loe na tim o ih hmuen to na sak o.
2 Wọ́n sì ń ṣe ojúkòkòrò oko, wọ́n sì fi agbára wọn gbà wọ́n, àti àwọn ilé, wọ́n sì gbà wọ́n. Wọ́n sì ni ènìyàn àti ilẹ̀ rẹ̀ lára àní ènìyàn àti ohun ìní rẹ̀.
Minawk ih lawk hmuen to a khit o moe, tha patoh hoiah a lomh pae o; imnawk doeh a khit o moe, lak pae o ving. Kami hoi imthung takohnawk to pacaekthlaek o moe, kami hoi a tawnh ih hmuennawk to lak pae o.
3 Nítorí náà, Olúwa wí pé: “Èmi ń gbèrò ibi sí àwọn ìdílé wọ̀nyí, nínú èyí tí wọn kì yóò le è gba ara wọn là. Ìwọ kì yóò sì lè máa rìn ní ìgbéraga mọ́, nítorí yóò jẹ́ àkókò ibi.
To pongah Angraeng mah, Khenah, hae imthung takoh nuiah raihaih phaksak hanah ka poek, to naah tahnong nang qoi thai mak ai; to atue loe kasae tue ah oh pongah, nam oek thai mak ai.
4 Ní ọjọ́ náà ni ẹnìkan yóò pa òwe kan sí yín; wọn yóò sì pohùnréré ẹkún kíkorò pé: ‘Ní kíkó a ti kó wọn tán; Olúwa ti pín ohun ìní àwọn ènìyàn mi; Ó ti mú un kúrò lọ́dọ̀ mi! Ó fi oko wa lé àwọn ọlọ̀tẹ̀ lọ́wọ́.’”
To na niah kaminawk mah nang misa haih lok to thui o ueloe, paroeai palungsethaih hoiah na qah o haih tih: kam ro o boeh! Anih mah kai kaminawk ih taham to lak ving boeh: kawbang maw kai ih hmuen to a lak ving halat! Kaicae ih lawknawk doeh minawk han a paek ving boeh, tiah thui o tih.
5 Nítorí náà, ìwọ kò ní ní ẹnìkankan tí yóò ta okùn nínú ìjọ Olúwa, tí yóò pín ilẹ̀ nípa ìbò.
To pongah Angraeng ih kaminawk amkhuenghaih ahmuen ah, taham khethaih phoisa to vah moe, prae kawng thuih hanah kami maeto doeh na tawn o mak ai.
6 “Ẹ má ṣe sọtẹ́lẹ̀,” ni àwọn wòlíì wọn wí. “Ẹ má ṣe sọtẹ́lẹ̀ nípa nǹkan wọ̀nyí; kí ìtìjú má ṣe le bá wa.”
Nihcae mah lok taphong kaminawk khaeah, Lok thui hmah lai ah: nihcae loe azat o ueloe, lok thui o mak ai boeh, tiah thuih o.
7 Ṣé kí á sọ ọ́, ìwọ ilé Jakọbu: “Ǹjẹ́ ẹ̀mí Olúwa ha ń bínú bí? Ǹjẹ́ iṣẹ́ rẹ ha nìwọ̀nyí?” “Ǹjẹ́ ọ̀rọ̀ mi kò ha ń ṣe rere fún ẹni tí ń rìn déédé bí?
Aw Jakob imthung takohnawk, Angraeng loe poek amthueng maw? Anih mah hae baktih hmuennawk hae sak maw? Ka thuih ih loknawk baktiah loklam toeng pazui kami khaeah kahoih hmuen to sah ai maw?
8 Láìpẹ́ àwọn ènìyàn mi dìde bí ọ̀tá sí mi. Ìwọ bọ́ aṣọ ọlọ́rọ̀ kúrò lára àwọn tí ń kọjá lọ ní àìléwu, bí àwọn ẹni tí ó padà bọ̀ láti ojú ogun.
Kai ih kaminawk loe canghnii ah misa angthawk o; misatukhaih ahmuen hoi zithaih tawn ai ah kamlaem kaminawk ih kahoih khukbuennawk to a khring pae o.
9 Ẹ̀yin sì lé obìnrin àwọn ènìyàn mi kúrò nínú ilé ayọ̀ wọn, ẹ̀yin sì ti gba ògo mi, kúrò lọ́wọ́ àwọn ọmọ wọn láéláé.
Kahoih angmacae ohhaih imthung hoiah kai ih kami nongpatanawk to na haek o; nihcae ih caa khae hoiah ka lensawkhaih to dungzan khoek to na lak pae o ving boeh.
10 Ẹ dìde, kí ẹ sì máa lọ! Nítorí èyí kì í ṣe ibi ìsinmi yín, nítorí tí a ti sọ ọ́ di àìmọ́ yóò pa yín run, àní ìparun kíkorò.
Angthawk ah loe, caeh o lai ah, hae ahmuen loe nangcae anghakhaih ahmuen na ai ni; amhnong boeh pongah kanung parai amrohaih hoiah nam ro tih boeh.
11 Tí òpùrọ́ àti ẹlẹ́tàn bá wà tí wọ́n sì wí pé, ‘Èmi yóò sọtẹ́lẹ̀ fún ọ nípa ọ̀pọ̀lọpọ̀ wáìnì àti ọtí líle,’ òun ni yóò tilẹ̀ ṣe wòlíì àwọn ènìyàn wọ̀nyí!
Amsawnlok thui kami hoi aling thaih kami mah, Kai loe nangcae khaeah misurtui hoi mu kawng to ka thuih han, tiah na naa o tih; nangcae loe to baktih tahmaa to ni na koeh o.
12 “Èmi yóò kó gbogbo yín jọ, ìwọ Jakọbu; Èmi yóò gbá ìyókù Israẹli jọ. Èmi yóò kó wọn jọ pọ̀ gẹ́gẹ́ bí àgùntàn nínú agbo ẹran, gẹ́gẹ́ bí ọ̀wọ́ ẹran nínú agbo wọn, ibẹ̀ yóò sì pariwo nítorí ọ̀pọ̀ ènìyàn.
Aw Jakob, kai mah kang pakhueng o boih han; kanghmat Israel kaminawk to kam khuengsak han; Bozrah ih tuu baktiah nawnto ka pakhueng han, tuu khongkha thung ih tuunawk baktiah ka suek han, kami paroeai pop pongah hraw o parai tih.
13 Ẹni tí ó ń fọ ọ̀nà yóò lọ sókè níwájú wọn; wọn yóò fọ láti ẹnu ibodè, wọn yóò sì jáde lọ. Àwọn ọba wọn yóò sì kọjá lọ níwájú wọn, Olúwa ni yóò sì ṣe olórí wọn.”
Khongkha phrae kami loe nihcae hmaa ah caeh tih; khongkha to phraek o, khongkha thung hoiah tacawt o moe, a caeh o: nihcae ih siangpahrang loe nihcae hma ah caeh tih, Angraeng loe nihcae hma ah caeh tih.

< Micah 2 >