< Micah 2 >

1 Ègbé ni fún àwọn tí ń gbèrò àìṣedéédéé tí wọ́n sì ń ṣiṣẹ́ ibi lórí ibùsùn wọn! Nígbà tí ojúmọ́ bá mọ́, wọn yóò gbé e jáde nítorí ó wà ní agbára wọn láti ṣe é.
Amo mae golale sidagane esala wadela: i hou hamomusa: ilegelalebe dunu ilia da se bagade nabimu! Soge da hadigila dasea, ilia da hamomu dibi ba: sea, ilia da ili wadela: i hou hamomusa: ilegei amo defele hamosa.
2 Wọ́n sì ń ṣe ojúkòkòrò oko, wọ́n sì fi agbára wọn gbà wọ́n, àti àwọn ilé, wọ́n sì gbà wọ́n. Wọ́n sì ni ènìyàn àti ilẹ̀ rẹ̀ lára àní ènìyàn àti ohun ìní rẹ̀.
Ilia da soge lamusa: dawa: sea, ilia da amo soge ilia suguli lasa. Ilia da diasu lamusa: dawa: sea, ilia da amo diasu lasa. Dunu afae ea sosogo amola liligi da noga: le dialebe da hamedafa ba: sa.
3 Nítorí náà, Olúwa wí pé: “Èmi ń gbèrò ibi sí àwọn ìdílé wọ̀nyí, nínú èyí tí wọn kì yóò le è gba ara wọn là. Ìwọ kì yóò sì lè máa rìn ní ìgbéraga mọ́, nítorí yóò jẹ́ àkókò ibi.
Amaiba: le Hina Gode da amane sia: sa, “Na da dilima gugunufinisisu hou dilima imunusa: ilegelala, amasea dilia da amoga hobeale masunu logo hamedafa ba: mu. Dilia da dilisu fawane bidi hamosu ganodini esalebe ba: mu, amasea dilia da hahawane hidala ahoasu amo bu hame hamomu.
4 Ní ọjọ́ náà ni ẹnìkan yóò pa òwe kan sí yín; wọn yóò sì pohùnréré ẹkún kíkorò pé: ‘Ní kíkó a ti kó wọn tán; Olúwa ti pín ohun ìní àwọn ènìyàn mi; Ó ti mú un kúrò lọ́dọ̀ mi! Ó fi oko wa lé àwọn ọlọ̀tẹ̀ lọ́wọ́.’”
Amo esoha da doaga: sea, dunu ilia da gugunufinisisu hou dilima doaga: i, dunu eno gugunufinisisu hou dawa: digima: ne ilima adodolalumu, amola ilia dilima hamoi amo dadawa: lu, heawini goe gesami hea: mu; “Nini da dafawanedafa wadela: lesi dagoi. Hina Gode da ninia soge amo lale fasi. Amalu amo soge, bu ninima hohonosu dunu amo iligili iasi dagoi.”
5 Nítorí náà, ìwọ kò ní ní ẹnìkankan tí yóò ta okùn nínú ìjọ Olúwa, tí yóò pín ilẹ̀ nípa ìbò.
Amaiba: le, soge amo da bu Hina Gode Ea fidafa dunu ilima bu imunu esoha doaga: sea, dunu afae diliga da amo soge amoga afae hame lamu.
6 “Ẹ má ṣe sọtẹ́lẹ̀,” ni àwọn wòlíì wọn wí. “Ẹ má ṣe sọtẹ́lẹ̀ nípa nǹkan wọ̀nyí; kí ìtìjú má ṣe le bá wa.”
Dunu ilia da nama olelelala, agoane sia: sa, “Ninima mae olelema! Amo huluane mae olelema! Gode da nini gogosiama: ne hame hamomu!
7 Ṣé kí á sọ ọ́, ìwọ ilé Jakọbu: “Ǹjẹ́ ẹ̀mí Olúwa ha ń bínú bí? Ǹjẹ́ iṣẹ́ rẹ ha nìwọ̀nyí?” “Ǹjẹ́ ọ̀rọ̀ mi kò ha ń ṣe rere fún ẹni tí ń rìn déédé bí?
Dilia dawa: lobada, Isala: ili fi dunu da aligima: ne gagabui amoha esalabala? Hina Gode Ea asaboi hou amo da yolebela: ? E da dafawane amo se iasu liligi hahamoma: bela: ? E da moloidafa hamobe dunu ilima asigili hame sia: nanabela: ?”
8 Láìpẹ́ àwọn ènìyàn mi dìde bí ọ̀tá sí mi. Ìwọ bọ́ aṣọ ọlọ́rọ̀ kúrò lára àwọn tí ń kọjá lọ ní àìléwu, bí àwọn ẹni tí ó padà bọ̀ láti ojú ogun.
Hina Gode da dabe sia: sa, “Dilia da Na dunuma ha lai agoane doagala: sa! Dunu ilia da gegenanu ili diasuga buhagibiba: le ilia da gaga: i dagoi amane dadawa: dudala, be amoga dilia da ilia anegagi abula amo ilia baligidu wamolamusa: oulelefula.
9 Ẹ̀yin sì lé obìnrin àwọn ènìyàn mi kúrò nínú ilé ayọ̀ wọn, ẹ̀yin sì ti gba ògo mi, kúrò lọ́wọ́ àwọn ọmọ wọn láéláé.
Dilia da na fi dunu ilia uda amo huluane ili hanai soge amoga esalu, amo oule sese ahoa, amola dilia da Na eso huluane hahawane fidisu hou amo Na da ilia manoma hamoi, amo lale fasi dagoi.
10 Ẹ dìde, kí ẹ sì máa lọ! Nítorí èyí kì í ṣe ibi ìsinmi yín, nítorí tí a ti sọ ọ́ di àìmọ́ yóò pa yín run, àní ìparun kíkorò.
Wa: legadole masa! Goeguda: da gaga: su hamedafa gala! Dilia da wadela: le hamobeba: le, Na da amo soge gugunufinisimusa: ilegei dagoi!
11 Tí òpùrọ́ àti ẹlẹ́tàn bá wà tí wọ́n sì wí pé, ‘Èmi yóò sọtẹ́lẹ̀ fún ọ nípa ọ̀pọ̀lọpọ̀ wáìnì àti ọtí líle,’ òun ni yóò tilẹ̀ ṣe wòlíì àwọn ènìyàn wọ̀nyí!
Amo dunu ilia da ogogole olelesu balofede dunu hanai gala. Agoai balofede da agoane ba: lala, “Na ba: laloba amo waini hano da dilia moma: ne, hano agoane ai masunu.
12 “Èmi yóò kó gbogbo yín jọ, ìwọ Jakọbu; Èmi yóò gbá ìyókù Israẹli jọ. Èmi yóò kó wọn jọ pọ̀ gẹ́gẹ́ bí àgùntàn nínú agbo ẹran, gẹ́gẹ́ bí ọ̀wọ́ ẹran nínú agbo wọn, ibẹ̀ yóò sì pariwo nítorí ọ̀pọ̀ ènìyàn.
Be Na fi dunu! Na da dili Isala: ili hame bogoi esalebe dunu amo dili gilisilisimu. Sibi da ilia gagoiga buhagibi, amo defele Na da dili gagadole, dilia sogega bu oule masunu. Sibi da gisi noga: i sogebi amogai gilisibi defele, dilia soge da dunu bagohamedafa amoga nabai ba: mu.”
13 Ẹni tí ó ń fọ ọ̀nà yóò lọ sókè níwájú wọn; wọn yóò fọ láti ẹnu ibodè, wọn yóò sì jáde lọ. Àwọn ọba wọn yóò sì kọjá lọ níwájú wọn, Olúwa ni yóò sì ṣe olórí wọn.”
Gode da Ea fidafa ilia buhagima: ne logo doasimu. Ilia mugululi asi amo fisili, Gode Hi da ilima bisili gadili oule masunu. Ilia da moilai logo holei fili asili, hahawane udigili masunu. Ilia Hina Bagade, Hina Gode Hisu, da ili bisili gadili oule masunu.

< Micah 2 >