< Matthew 3 >
1 Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, Johanu onítẹ̀bọmi wá, ó ń wàásù ní aginjù Judea.
Munsiku zila u Yohana Umwozyo ahinzile alumbilile hunyika iya hu Yuda ahaga,
2 Ó ń wí pé, “Ẹ ronúpìwàdà, nítorí ìjọba ọ̀run kù sí dẹ̀dẹ̀.”
“Mulambe pipo ubhumwini uwahumwanya bhusojeliye.”
3 Èyí ni ẹni náà ti wòlíì Isaiah sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ pé, “Ohùn ẹni ti ń kígbe ní ijù, ‘Ẹ tún ọ̀nà Olúwa ṣe, ẹ ṣe ojú ọ̀nà rẹ̀ kí ó tọ́.’”
Pipo unu yahayangwilwe nukuwa u Isaya ahaga, “Izwi lya muntu ya kwizya afume hujangwani; 'mubhishe tayari idala lya gosi, mugagoloshe amashilo gakwe.”
4 Aṣọ Johanu náà sì jẹ́ ti irun ìbákasẹ, ó sì di àmùrè awọ sí ẹ̀gbẹ́ rẹ̀. Eṣú àti oyin ìgàn sì ni oúnjẹ rẹ̀.
Ishi Uyohana ahakwite amasepe agingamia ni lamba ilyingozi musana wakwe, ishalye shakwe shahali nzije nu woshi uwa mwisengo.
5 Àwọn ènìyàn jáde lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ láti Jerusalẹmu àti gbogbo Judea àti àwọn ènìyàn láti gbogbo ìhà Jordani.
Habhili Muyerusalemu, Iyuda yonti, ni sehemu yonti yeyahazyangulile isoho Iyordani bhahabhala hukwakwe.
6 Wọ́n ń jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ wọn, a sì ń bamitiisi wọn ní ọ̀dọ̀ rẹ̀ ní odò Jordani.
Bhahozewaga nawo mwisoho mu Yordani bhalambaga hwangwubhi imbibhi zyabho.
7 Ṣùgbọ́n nígbà tí ó rí ọ̀pọ̀ àwọn Farisi àti Sadusi tí wọ́n ń wá ṣe ìtẹ̀bọmi, ó wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ọmọ paramọ́lẹ̀! Ta ni ó kìlọ̀ fún yín pé kí ẹ́ sá kúrò nínú ìbínú tí ń bọ̀?
Lwahabhalola abhinji abhamafalisayo na masadukayo lwebhahwuzya, “Amwe mwimpapo izyi nzoha izyi sumu wenu yabhasoshile huyishimbile inkuni yihwinza?
8 Ẹ so èso tí ó yẹ fún ìrònúpìwàdà.
Mupape amadondo gegahwanziwa alaabe.
9 Kí ẹ má sì ṣe rò nínú ara yin pé, ‘Àwa ní Abrahamu ní baba.’ Èmi wí fún yín, Ọlọ́run lè mu àwọn ọmọ jáde láti inú àwọn òkúta wọ̀nyí wá fún Abrahamu.
Mgandi asibhe na ayanjizanye hulimwe mwe, 'Tulinawo u Ibrahimu ye yise witu.' Pipo imbabhuzya aje Ungulubhi angamwimishizya u Ibrahimu abhana afumilane na mawe iga.
10 Nísinsin yìí, a ti fi àáké lè gbòǹgbò igi, àti pé gbogbo igi tí kò bá so èso rere ni a óò ge lulẹ̀ ti a ó sì wọ jù sínú iná.
Intemu iliho ibhihwile hunzizi ugwi kwi. Ishi ikwi lyolyonti lyesalipapa amadondo lidumulwa na tajilwe mu mwoto.
11 “Èmi fi omi bamitiisi yín fún ìrònúpìwàdà. Ṣùgbọ́n lẹ́yìn mi ẹnìkan tí ó pọ̀jù mí lọ ń bọ̀, bàtà ẹni tí èmi kò tó gbé. Òun ni yóò fi Ẹ̀mí Mímọ́ àti iná bamitiisi yín.
Ihubhozya na manzi hunongwa ya lambe. Ishi umwene yahwinza badala yani ngosi kuliko ani. Nanisihwanziwa abhusye iyilyatu vyakwe. Umwene asibhozye hwa mpepo umfinjile na humwoto.
12 Ẹni ti àmúga ìpakà rẹ̀ ń bẹ ní ọwọ́ rẹ̀, yóò gbá ilẹ̀ ìpakà rẹ̀, yóò kó alikama rẹ̀ sínú àká, ṣùgbọ́n ìyàngbò ni yóò fi iná àjóòkú sun.”
Na ulupapike lwakwe lulimunyobhe zyakwe lupepeta nziila na hwozye na abhunganye ingano zyakwe mushanga. Nantele abhapembe amakapi mumwoto wesebhuzimiha.
13 Nígbà náà ni Jesu ti Galili wá sí odò Jordani kí Johanu bá à lè ṣe ìtẹ̀bọmi fún un.
Nantele u Yesu ahinza afume hu Galilaya mpaka mwisoho Iyorodani ahwozewe nu Yohana.
14 Ṣùgbọ́n Johanu kò fẹ́ ṣe ìtẹ̀bọmi fún un, ó wí pé, “Ìwọ ni ìbá bamitiisi fún mi, ìwọ sì tọ̀ mí wá?”
Uyohana ahandaga akhane aje, “Asahamwozye pipo u Yesu gosi ashile u Yohana?”
15 Jesu sì dáhùn pé, “Jọ̀wọ́ rẹ̀ bẹ́ẹ̀ náà, nítorí bẹ́ẹ̀ ni ó yẹ fún wa láti mú gbogbo òdodo ṣẹ.” Bẹ́ẹ̀ ni Johanu gbà, ó sì ṣe ìtẹ̀bọmi fún un.
U Yesu ahayanga ahaga, “Nini ihurusu awe unozye, maana ihwanziwa aje inkamilisye ilyoli yonti.” U Yohana pa ahamwozya u Yesu.
16 Bí ó si tí ṣe ìtẹ̀bọmi fún Jesu tán, Ó jáde láti inú omi. Ní àkókò náà ọ̀run ṣí sílẹ̀ fún un, Ó sì rí Ẹ̀mí Ọlọ́run ń sọ̀kalẹ̀ bí àdàbà, ó sì bà lé e.
Baada ya hwozewe u Yesu ahafumile muminzi ahenya imwaaya zyahamwigushiye, nantele ahanola umpepo wa Ngulubhi ahwiha hushifwani shinjibha na ahwimilile pamwanya yakwe.
17 Ohùn kan láti ọ̀run wá sì wí pé, “Èyí sì ni àyànfẹ́ ọmọ mi, ẹni tí inú mi dùn sí gidigidi.”
Izwi, lyahafumile humwanya lyahaga, “Unu mwana wani uganwa. Indi ni insungwo nawo hani.”