< Matthew 3 >

1 Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, Johanu onítẹ̀bọmi wá, ó ń wàásù ní aginjù Judea.
Munsiku ejo ejile Yohana unu abhatijaga ejile nalasha mwibhala lya Yuda naikati,”
2 Ó ń wí pé, “Ẹ ronúpìwàdà, nítorí ìjọba ọ̀run kù sí dẹ̀dẹ̀.”
Mute, kulwokubha obhukama bhwa mulwile bhulieyi.
3 Èyí ni ẹni náà ti wòlíì Isaiah sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ pé, “Ohùn ẹni ti ń kígbe ní ijù, ‘Ẹ tún ọ̀nà Olúwa ṣe, ẹ ṣe ojú ọ̀nà rẹ̀ kí ó tọ́.’”
“Kulwokubha unu niwe aikilwe nomulagi Isaya naikati,”Obhulaka bhwo munu unu kabhilikila okusoka mwibhala, muteabhwelu injila ya Nyamuanga, mugolole injila yae.”
4 Aṣọ Johanu náà sì jẹ́ ti irun ìbákasẹ, ó sì di àmùrè awọ sí ẹ̀gbẹ́ rẹ̀. Eṣú àti oyin ìgàn sì ni oúnjẹ rẹ̀.
Oli Yohana afwalaga amakamba ga Ingamila no mukanda gwo lwai muchibhunu chae. Ebhilyo byae byaliga njige no obhuki bhwa mwibhala.
5 Àwọn ènìyàn jáde lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ láti Jerusalẹmu àti gbogbo Judea àti àwọn ènìyàn láti gbogbo ìhà Jordani.
Eile Yerusalemu, Yuda yona, na libhala lyona linu lyeindaga omugela gwa Yorodani nibhaja kumwene.
6 Wọ́n ń jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ wọn, a sì ń bamitiisi wọn ní ọ̀dọ̀ rẹ̀ ní odò Jordani.
Bhaliga nibhabhatijwa nage mumugela gwa Yorodani enu nibhataga ebhibhibhi bhyebhwe.
7 Ṣùgbọ́n nígbà tí ó rí ọ̀pọ̀ àwọn Farisi àti Sadusi tí wọ́n ń wá ṣe ìtẹ̀bọmi, ó wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ọmọ paramọ́lẹ̀! Ta ni ó kìlọ̀ fún yín pé kí ẹ́ sá kúrò nínú ìbínú tí ń bọ̀?
Tali ejile abhalola bhafu bha mafarisayo na masadukayo nibhaja kumwene okubhatijwa, nabhabhilati,”Emwe olwibhulo lwa injoka bhanu muli no bhusungu niga unu amabhaganya okubhilima lisungu linu elija?
8 Ẹ so èso tí ó yẹ fún ìrònúpìwàdà.
Mwibhule amatwasho ganu geile okuta.
9 Kí ẹ má sì ṣe rò nínú ara yin pé, ‘Àwa ní Abrahamu ní baba.’ Èmi wí fún yín, Ọlọ́run lè mu àwọn ọmọ jáde láti inú àwọn òkúta wọ̀nyí wá fún Abrahamu.
Namutajakwiganilisha no kwaikana amwi yemwe,'Chinage Ibrahimu kuti lata weswe.'Kulwokubha nabhabhwilaati Nyamuanga katula okumwimusisha Ibrahimu abhana okusoka kumabhuyi ganu.
10 Nísinsin yìí, a ti fi àáké lè gbòǹgbò igi, àti pé gbogbo igi tí kò bá so èso rere ni a óò ge lulẹ̀ ti a ó sì wọ jù sínú iná.
Naoli inshoka yateweyo kumisi ja liti. Kulwejo bhuli eti linu litakwibhula matwasho gakisi elitemwa no kweswa mumulilo.
11 “Èmi fi omi bamitiisi yín fún ìrònúpìwàdà. Ṣùgbọ́n lẹ́yìn mi ẹnìkan tí ó pọ̀jù mí lọ ń bọ̀, bàtà ẹni tí èmi kò tó gbé. Òun ni yóò fi Ẹ̀mí Mímọ́ àti iná bamitiisi yín.
Enibhabhatija mu manji kulwokuta. Tali unu kaja inyuma yani ni mukulu kukila anye nanye ntakutula ata kugega bhilato bhyae. Omwene kaja okubhabhatija kwo mwoyo mwelu no mulilo.
12 Ẹni ti àmúga ìpakà rẹ̀ ń bẹ ní ọwọ́ rẹ̀, yóò gbá ilẹ̀ ìpakà rẹ̀, yóò kó alikama rẹ̀ sínú àká, ṣùgbọ́n ìyàngbò ni yóò fi iná àjóòkú sun.”
No oluungo lwae luli mumabhoko gae okwesha olubhuga lwae nokukumanya ingano yae muchitala. Tali kagocha amakumbi kwo mulilo gunu gutakutula kusima.
13 Nígbà náà ni Jesu ti Galili wá sí odò Jordani kí Johanu bá à lè ṣe ìtẹ̀bọmi fún un.
Neya Yesu naja okusoka Galilaya nakinga ku mugela gwa Yorodani okubhatijibhwa na Yohana.
14 Ṣùgbọ́n Johanu kò fẹ́ ṣe ìtẹ̀bọmi fún un, ó wí pé, “Ìwọ ni ìbá bamitiisi fún mi, ìwọ sì tọ̀ mí wá?”
Tali Yohana endaga okumuganya naikati,”Anye jinyiile nibhatijibhwe nawe, kawe ona ouja kwanye?
15 Jesu sì dáhùn pé, “Jọ̀wọ́ rẹ̀ bẹ́ẹ̀ náà, nítorí bẹ́ẹ̀ ni ó yẹ fún wa láti mú gbogbo òdodo ṣẹ.” Bẹ́ẹ̀ ni Johanu gbà, ó sì ṣe ìtẹ̀bọmi fún un.
Yesu namusubhya naikati,”Ikilisha oli anu jibhe kutyo, kulwokubha jichiile okukumisha obhulengelesi bhwona.”Eile Yohana namwikilisisha.
16 Bí ó si tí ṣe ìtẹ̀bọmi fún Jesu tán, Ó jáde láti inú omi. Ní àkókò náà ọ̀run ṣí sílẹ̀ fún un, Ó sì rí Ẹ̀mí Ọlọ́run ń sọ̀kalẹ̀ bí àdàbà, ó sì bà lé e.
Ejile amala obhatijwa Yesu nasoka mumanji, nalola, Olwile nilwiguka ku mwene. Namulola mwoyo mwelu wa Nyamuanga natuka kulwolususo lwa inguti nokufung'ama ingulu yae.
17 Ohùn kan láti ọ̀run wá sì wí pé, “Èyí sì ni àyànfẹ́ ọmọ mi, ẹni tí inú mi dùn sí gidigidi.”
Lola obhulaka nibhusoka Mulwile nibhwaika,”Unu ni mwana wani unu nendele unu enikondelwa muno nage.”

< Matthew 3 >