< Matthew 28 >

1 Ní kùtùkùtù òwúrọ̀ ọjọ́ kìn-ín-ní ọ̀sẹ̀, bí ilẹ̀ ti ń mọ́, Maria Magdalene àti Maria kejì lọ sí ibojì.
تَتَح پَرَں وِشْرامَوارَسْیَ شیشے سَپْتاہَپْرَتھَمَدِنَسْیَ پْرَبھوتے جاتے مَگْدَلِینِی مَرِیَمْ اَنْیَمَرِیَمْ چَ شْمَشانَں دْرَشْٹُماگَتا۔
2 Wọ́n rí i pé, ìṣẹ̀lẹ̀ ńlá ṣẹ̀ tí ó mú gbogbo ilẹ̀ mì tìtì. Nítorí angẹli Olúwa ti sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run. Ó ti yí òkúta ibojì kúrò. Ó sì jókòó lé e lórí.
تَدا مَہانْ بھُوکَمْپوبھَوَتْ؛ پَرَمیشْوَرِییَدُوتَح سْوَرْگادَوَرُہْیَ شْمَشانَدْواراتْ پاشانَمَپَسارْیَّ تَدُپَرْیُّپَوِویشَ۔
3 Ojú rẹ̀ tàn bí mọ̀nàmọ́ná. Aṣọ rẹ̀ sì jẹ́ funfun bí ẹ̀gbọ̀n òwú.
تَدْوَدَنَں وِدْیُدْوَتْ تیجومَیَں وَسَنَں ہِمَشُبھْرَنْچَ۔
4 Ẹ̀rù ba àwọn olùṣọ́, wọ́n sì wárìrì wọn sì dàbí òkú.
تَدانِیں رَکْشِنَسْتَدْبھَیاتْ کَمْپِتا مرِتَوَدْ بَبھُووَح۔
5 Nígbà náà ni angẹli náà wí fún àwọn obìnrin náà pé, “Ẹ má ṣe bẹ̀rù. Mo mọ̀ pé ẹ̀yin ń wá Jesu tí a kàn mọ́ àgbélébùú.
سَ دُوتو یوشِتو جَگادَ، یُویَں ما بھَیشْٹَ، کْرُشَہَتَیِیشُں مرِگَیَدھْوے تَدَہَں ویدْمِ۔
6 Ṣùgbọ́n kò sí níhìn-ín. Nítorí pé ó ti jíǹde, gẹ́gẹ́ bí òun ti wí. Ẹ wọlé wá wo ibi ti wọ́n tẹ́ ẹ sí.
سوتْرَ ناسْتِ، یَتھاوَدَتْ تَتھوتّھِتَوانْ؛ ایتَتْ پْرَبھوح شَیَنَسْتھانَں پَشْیَتَ۔
7 Nísinsin yìí, ẹ lọ kíákíá láti sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, ‘Ó ti jíǹde kúrò nínú òkú. Àti pé òun ń lọ sí Galili síwájú yín, níbẹ̀ ni ẹ̀yin yóò gbé rí i,’ wò ó, o ti sọ fún yin.”
تُورْنَں گَتْوا تَچّھِشْیانْ اِتِ وَدَتَ، سَ شْمَشانادْ اُدَتِشْٹھَتْ، یُشْماکَمَگْرے گالِیلَں یاسْیَتِ یُویَں تَتْرَ تَں وِیکْشِشْیَدھْوے، پَشْیَتاہَں وارْتّامِماں یُشْمانَوادِشَں۔
8 Àwọn obìnrin náà sáré kúrò ní ibojì pẹ̀lú ìbẹ̀rù àti ayọ̀ ńlá. Wọ́n sáré láti sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn nípa ìròyìn tí angẹli náà fi fún wọn.
تَتَسْتا بھَیاتْ مَہانَنْدانْچَ شْمَشاناتْ تُورْنَں بَہِرْبھُویَ تَچّھِشْیانْ وارْتّاں وَکْتُں دھاوِتَوَتْیَح۔ کِنْتُ شِشْیانْ وارْتّاں وَکْتُں یانْتِ، تَدا یِیشُ رْدَرْشَنَں دَتّوا تا جَگادَ،
9 Bí wọ́n ti ń sáré lọ lójijì Jesu pàdé wọn. Ó wí pé, “Àlàáfíà”, wọ́n wólẹ̀ níwájú rẹ̀. Wọ́n gbá a ní ẹsẹ̀ mú. Wọ́n sì foríbalẹ̀ fún un.
یُشْماکَں کَلْیانَں بھُویاتْ، تَتَسْتا آگَتْیَ تَتْپادَیوح پَتِتْوا پْرَنیمُح۔
10 Nígbà náà, Jesu wí fún wọn pé, “Ẹ má ṣe bẹ̀rù. Ẹ lọ sọ fún àwọn arákùnrin mi pé, ‘Kí wọ́n lọ tààrà sí Galili níbẹ̀ ni wọn yóò gbé rí mi.’”
یِیشُسْتا اَوادِیتْ، ما بِبھِیتَ، یُویَں گَتْوا مَمَ بھْراترِنْ گالِیلَں یاتُں وَدَتَ، تَتْرَ تے ماں دْرَکْشْیَنْتِ۔
11 Bí àwọn obìnrin náà sì ti ń lọ sí ìlú, díẹ̀ nínú àwọn olùṣọ́ tí wọ́n ti ń ṣọ́ ibojì lọ sọ́dọ̀ àwọn olórí àlùfáà.
سْتْرِیو گَچّھَنْتِ، تَدا رَکْشِناں کیچِتْ پُرَں گَتْوا یَدْیَدْ گھَٹِتَں تَتْسَرْوَّں پْرَدھانَیاجَکانْ جْناپِتَوَنْتَح۔
12 Wọ́n sì pe ìpàdé àwọn àgbàgbà Júù. Wọ́n sì fohùn ṣọ̀kan láti fi owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ fún àwọn olùṣọ́.
تے پْراچِینَیح سَمَں سَںسَدَں کرِتْوا مَنْتْرَیَنْتو بَہُمُدْراح سینابھْیو دَتّواوَدَنْ،
13 Wọ́n wí pé, “Ẹ sọ fún àwọn ènìyàn pé, ‘Gbogbo yín sùn nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu wá lóru láti jí òkú rẹ̀.’
اَسْماسُ نِدْرِتیشُ تَچّھِشْیا یامِنْیاماگَتْیَ تَں ہرِتْوانَیَنْ، اِتِ یُویَں پْرَچارَیَتَ۔
14 Bí Pilatu bá sì mọ̀ nípa rẹ̀, àwa yóò ṣe àlàyé tí yóò tẹ́ ẹ lọ́rùn fún un, tí ọ̀rọ̀ náà kì yóò fi lè kó bá yín.”
یَدْییتَدَدھِپَتیح شْروتْرَگوچَرِیبھَویتْ، تَرْہِ تَں بودھَیِتْوا یُشْمانَوِشْیامَح۔
15 Àwọn olùṣọ́ sì gba owó náà. Wọ́n sì ṣe gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti darí wọn. Ìtàn yìí sì tàn ká kíákíá láàrín àwọn Júù. Wọ́n sì gba ìtàn náà gbọ́ títí di òní yìí.
تَتَسْتے مُدْرا گرِہِیتْوا شِکْشانُرُوپَں کَرْمَّ چَکْرُح، یِہُودِییاناں مَدھْیے تَسْیادْیاپِ کِںوَدَنْتِی وِدْیَتے۔
16 Nígbà náà ni àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mọ́kànlá náà lọ sí Galili ní orí òkè níbi tí Jesu sọ pé wọn yóò ti rí òun.
ایکادَشَ شِشْیا یِیشُنِرُوپِتاگالِیلَسْیادْرِں گَتْوا
17 Nígbà tí wọ́n sì rí i, wọ́n foríbalẹ̀ fún un. Ṣùgbọ́n díẹ̀ nínú wọn ṣe iyèméjì bóyá Jesu ni tàbí òun kọ́.
تَتْرَ تَں سَںوِیکْشْیَ پْرَنیمُح، کِنْتُ کیچِتْ سَنْدِگْدھَوَنْتَح۔
18 Nígbà náà ni Jesu wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Gbogbo agbára ni ọ̀run àti ní ayé ni a ti fi fún mi.
یِیشُسْتیشاں سَمِیپَماگَتْیَ وْیاہرِتَوانْ، سْوَرْگَمیدِنْیوح سَرْوّادھِپَتِتْوَبھارو مَیَّرْپِتَ آسْتے۔
19 Nítorí náà, ẹ lọ, ẹ sọ wọ́n di ọmọ-ẹ̀yìn orílẹ̀-èdè gbogbo, ẹ máa bamitiisi wọn ní orúkọ Baba àti ti Ọmọ àti ti Ẹ̀mí Mímọ́.
اَتو یُویَں پْرَیایَ سَرْوَّدیشِییانْ شِشْیانْ کرِتْوا پِتُح پُتْرَسْیَ پَوِتْرَسْیاتْمَنَشْچَ نامْنا تانَوَگاہَیَتَ؛ اَہَں یُشْمانْ یَدْیَدادِشَں تَدَپِ پالَیِتُں تانُپادِشَتَ۔
20 Ẹ kọ́ wọn láti máa kíyèsi ohun gbogbo èyí tí mo ti pàṣẹ fún yín. Nítorí èmi wà pẹ̀lú yín ní ìgbà gbogbo títí tí ó fi dé òpin ayé.” (aiōn g165)
پَشْیَتَ، جَگَدَنْتَں یاوَتْ سَداہَں یُشْمابھِح ساکَں تِشْٹھامِ۔ اِتِ۔ (aiōn g165)

< Matthew 28 >