< Matthew 23 >
1 Nígbà náà ni Jesu wí fún ọ̀pọ̀ ènìyàn àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé,
I'see cəmə'ətık'leyiy Cune telebabışik'le eyhen:
2 “Àwọn olùkọ́ òfin àti àwọn Farisi jókòó ní ipò Mose,
– Q'aanunne mə'əllimaaşeyiy fariseyaaşe Mısayne doyule xət qa'a ıxha.
3 nítorí náà, ẹ gbọdọ̀ gbọ́ tiwọn, kí ẹ sì ṣe ohun gbogbo tí wọ́n bá sọ fún yín. Ṣùgbọ́n ẹ má ṣe ohun tí wọ́n ṣe, nítorí àwọn pàápàá kì í ṣe ohun tí wọn kọ́ yín láti ṣe.
Şu mançil-allad manbışe eyhençil k'ırı alixhxhı, şok'le uvhuyn gırgın he'e. Saccu manbışe ha'an şu hıma'a, manbışe uvhiyn ha'a deş.
4 Wọ́n á di ẹrù wúwo tí ó sì ṣòro láti rù, wọ́n a sì gbé e le àwọn ènìyàn léjìká, ṣùgbọ́n àwọn tìkára wọn kò jẹ́ fi ìka wọn kan an.
Manbışe yı'q'ı'n, haqqas dağamda eyxhen karbı insanaaşine yı'q'əlqa iliyxhe. Come man xev cigeençe ı'ğiykar ha'asvaxheyib, t'ub ı'ğviykar haa'a deş.
5 “Ohun gbogbo tí wọ́n ń ṣe, wọ́n ń ṣe é kí àwọn ènìyàn ba à lè rí wọn ni. Wọ́n ń sọ filakteri wọn di gbígbòòrò. Wọ́n tilẹ̀ ń bùkún ìṣẹ́tí aṣọ oyè wọn nígbà gbogbo kí ó ba à lè máa tóbi sí i.
Gırgıncad manbışe insanaaşik'le g'acecenva ha'a. Mançınemeeyid manbışe colyna q'ut əq', tanalinçilin bağar xıliy qa'a.
6 Wọ́n fẹ́ ipò ọlá ní ibi àsè, àti níbi ìjókòó ìyàsọ́tọ̀ ni Sinagọgu.
Manbışis otxhan-ulyoğane cigabışeeyiy sinagogbışee nekke qoma gyuv'aras,
7 Wọ́n fẹ́ kí ènìyàn máa kí wọn ní ọjà, kí àwọn ènìyàn máa pè wọ́n ní ‘Rabbi.’
maydambışee salam alyapt'as, insanaaşe cok'le «Mə'əllimva» uvhiy geedxhe ıkkiykan.
8 “Ṣùgbọ́n kí a má ṣe pè yín ni Rabbi, nítorí pé ẹnìkan ni Olùkọ́ yín, àní Kristi, ará sì ni gbogbo yín.
Vuşun gırgınbıb çocar vob. Şoqar sa Mə'əllim vor. Mançil-allad hasre şolqa şavaacad «Mə'əllimva» on hıma'acen.
9 Ẹ má ṣe pe ẹnikẹ́ni ní baba yín ni ayé yìí, nítorí baba kan náà ni ẹ ní tí ó ń bẹ ní ọ̀run.
Şoqa sa Dek vor, Vucur Xəybışee vor. Mançil-allad ç'iyene aq'val şavuk'lecad «Dekva» immeyhe.
10 Kí a má sì ṣe pè yín ní Olùkọ́ nítorí Olùkọ́ kan ṣoṣo ni ẹ̀yin ní, òun náà ni Kristi.
Şoqa sa Rəhbər vor, Manar Masixh vor. Şok'le hasre şavaacad «rəhbərva» immeyhecen.
11 Ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá pọ̀jù nínú yín, ni yóò jẹ́ ìránṣẹ́ yín.
Vuşde yı'q'neene nekke xərıng'vee hasre şos k'ılyvalla he'ecen.
12 Ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni tí ó bá gbé ara rẹ̀ ga ni a ó sì rẹ̀ sílẹ̀, ẹnikẹ́ni tí ó bá sì rẹ ara wọn sílẹ̀ ni a ó gbéga.
Vucecar vuc axtı qa'ana Allahee avqa qa'as, vucecar vuc avqa qa'anar Allahee axtı qaa'as.
13 “Ègbé ni fún yín, ẹ̀yin olùkọ́ òfin àti Farisi, ẹ̀yin àgàbàgebè! Ẹ̀yin sé ìjọba ọ̀run mọ́ àwọn ènìyàn nítorí ẹ̀yin tìkára yín kò wọlé, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin kò jẹ́ kí àwọn tí ó fẹ́ wọlé ó wọlé.
Şolqa ver ooxas, q'öbvalla haa'an Q'aanunun mə'əllimariy fariseyar! Şu Xəybışeene Paççahiyvalin akkabı insanaaşine aq'vabışeeqa qa'a. Maqa şunab ikkəə deş, ikkeepçes vukkananbıb havaysar deş.
15 “Ègbé ni fún yín, ẹ̀yin olùkọ́ òfin àti Farisi, ẹ̀yin àgàbàgebè! Nítorí ẹ̀yin rin yí ilẹ̀ àti òkun ká láti yí ẹnìkan lọ́kàn padà, ṣùgbọ́n ẹ̀yin ń sọ ọ́ di ọmọ ọ̀run àpáàdì ní ìlọ́po méjì ju ẹ̀yin pàápàá. (Geenna )
Şolqa ver ooxas, q'öbvalla haa'an Q'aanunun mə'əllimariy fariseyar! Şu çiyebı-deryahbı gits'idaxhva dinılqa sa xheyir insan sak'ala'asva. Dinılqa sak'al hı'ımeeyir, şu məxrına insan şole q'önəqqees geer cehinyamıs avak'ı ha'a. (Geenna )
16 “Ègbé ni fún yín, ẹ̀yin afọ́jú ti ń fi ọ̀nà han afọ́jú! Tí ó wí pé, ‘Ẹnikẹ́ni tí ó ba fi tẹmpili búra kò sí nǹkan kan, ṣùgbọ́n bí ẹnikẹ́ni bá fi wúrà inú tẹmpili búra, ó di ajigbèsè.’
Şolqa ver ooxas, bı'rq'ı'n rəhbərar! Şu eyhen: «Şavaayiy Allahne xal k'ın g'iysar, man k'ın eyxhe deş. De'eş, Allahne xaane k'ınəəğəl g'assıreene, man eyxhen».
17 Ẹ̀yin aláìmòye afọ́jú: èwo ni ó ga jù, wúrà tàbí tẹmpili tí ó ń sọ wúrà di mímọ́?
Ay ək'el deşin bı'rq'ı'nbı! Allahne xaadın k'ınəəğəne yugda, deşxhee Allahın xavne, man k'ınəəğə muq'addasın ha'an?
18 Àti pé, ẹnikẹ́ni tó bá fi pẹpẹ búra, kò jámọ́ nǹkan, ṣùgbọ́n bí ẹnikẹ́ni tí ó ba fi ẹ̀bùn tí ó wà lórí rẹ̀ búra, ó di ajigbèsè.
Şucad meed eyhe: «Şavaamecad q'urbanbı allya'ane cigaylen k'ın g'assıreene, man k'ın eyxhe deş. De'eş, ablya'ane q'urbanılqan k'ın g'assıreene, man eyxhen».
19 Ẹ̀yin aláìmòye afọ́jú wọ̀nyí! Èwo ni ó pọ̀jù: ẹ̀bùn tí ó wà lórí pẹpẹ ni tàbí pẹpẹ fúnra rẹ̀ tí ó sọ ẹ̀bùn náà di mímọ́?
Ay bı'rq'ı'nbı, q'urbanne yugba, deşxhee, q'urbanbı allya'an cigane, mana q'urban muq'addasna ha'an?
20 Nítorí náà ẹnikẹ́ni tí ó bá ń fi pẹpẹ búra, ó fi í búra àti gbogbo ohun tí ó wà lórí rẹ̀.
Q'urban ablyaa'ane cigayle k'ın g'iysarang'vee, mançilqayiy mançilyne gırgıne karalqacad k'ın g'iysar xhinne eyxhe.
21 Àti pé, ẹni tí ó bá fi tẹmpili búra, ó fi í búra àti ẹni tí ń gbé inú rẹ̀.
Allahne xaalqa k'ın g'iysarang'veeyid, mançilqad, mançine Arıng'ulqad çikana k'ın g'iysaran xhinne eyxhe.
22 Àti pé, ẹni tí ó bá sì fi ọ̀run búra, ó fi ìtẹ́ Ọlọ́run àti ẹni tí ó jókòó lórí rẹ̀ búra.
Xəybışilen k'ın g'iysarang'veeyid Allahne taxtılqaniy mançil Gyu'uring'ulqad k'ın g'iysaran xhinne eyxhe.
23 “Ègbé ni fún yín ẹ̀yin olùkọ́ òfin àti Farisi, ẹ̀yin àgàbàgebè! Nítorí ẹ̀yin ń gba ìdámẹ́wàá minti, dili àti kumini, ẹ̀yin sì ti fi ohun tí ó ṣe pàtàkì jùlọ nínú òfin sílẹ̀ láìṣe, ìdájọ́, àánú àti ìgbàgbọ́. Wọ̀nyí ni ó tọ́ tí ẹ̀yin ìbá ṣe, ẹ̀yin kò bá fi wọ̀n-ọn-nì sílẹ̀ láìṣe.
Şolqa ver ooxas, q'öbvalla haa'an Q'aanunun mə'əllimariy fariseyar! Şu naaneyna, şyuyutna, zirayna yits'ınçina sa pay Allahıs quveeyib, Q'aanunee otk'unin nekke ç'ak'ın işbı ha'a deş: şu qopkuvalla, rəhı'm, inyam yik'elycad hixan ha'a. Şu şençika sacigee inıd ha'askanniy.
24 Ẹ̀yin afọ́jú tó ń fi afọ́jú mọ̀nà! Ẹ tu kòkòrò-kantíkantí tó bọ́ sì yín lẹ́nu nù, ẹ gbé ìbákasẹ mì.
Ay bı'rq'ı'n rəhbərar! Şu ulyoğasın kar miçak curaa'asva vexhxheençe alğayhe, devamee bıkırbacab k'ööğə.
25 “Ègbé ni fún yín ẹ̀yin Farisi àti ẹ̀yin olùkọ́ òfin, ẹ̀yin àgàbàgebè. Ẹ̀yin ń fọ òde ago àti àwo ṣùgbọ́n inú rẹ̀ kún fún ìrẹ́jẹ àti ẹ̀gbin gbogbo.
Şolqa ver ooxas, q'öbvalla haa'an Q'aanunun mə'əllimariy fariseyar! Şu k'olayiy g'ab g'adğançe hoyğal, adğançemee manbı vuşde q'ı'rq'ı't'iyvalika, mıssıne uleka sı'iyne karaka gyatsts'ı vod.
26 Ìwọ afọ́jú Farisi, tètè kọ́ fọ inú ago àti àwo, gbogbo ago náà yóò sì di mímọ́.
Bı'rq'ı'na farisey, ğu ts'etta k'olayiy g'ab adğançe hoğle, manke manbı g'adğançed məttı qeetxhesınbı.
27 “Ègbé ni fún yín ẹ̀yin Farisi àti ẹ̀yin olùkọ́ òfin, ẹ̀yin àgàbàgebè. Ẹ dàbí ibojì funfun tí ó dára ní wíwò, ṣùgbọ́n tí ó kún fún egungun ènìyàn àti fún ẹ̀gbin àti ìbàjẹ́.
Şolqa ver ooxas, q'öbvalla haa'an Q'aanunun mə'əllimariy fariseyar! Şu g'abğançe cagvara qav'uyne micagba g'oocene mağareene nyuq'nek akar. Mana micagba g'abğançe vuxheeyib, abğançe hapt'ıynbışde bark'vbışikayiy nəxdıne ıxheeyid mı'q'ı'ne karbışika gyavts'u vooxhe.
28 Ẹ̀yin gbìyànjú láti farahàn bí ènìyàn mímọ́, olódodo, lábẹ́ aṣọ mímọ́ yín ni ọkàn tí ó kún fún ìbàjẹ́ pẹ̀lú oríṣìíríṣìí àgàbàgebè àti ẹ̀ṣẹ̀ wà.
Şunab həməxüb insanaaşik'le g'abğançe qopkuba g'avceeyib, yik'ee şu q'öbvalla haa'a, pisın işbı g'ece.
29 “Ègbé ni fún yín ẹ̀yin olùkọ́ òfin àti Farisi, ẹ̀yin àgàbàgebè, nítorí ẹ̀yin kọ́ ibojì àwọn wòlíì tí í ṣe ibojì àwọn olódodo ní ọ̀ṣọ́.
Şolqa ver ooxas, q'öbvalla haa'an Q'aanunun mə'əllimariy fariseyar! Şu peyğambaraaşine nyaq'vbışil mavzoleybı alya'a, qopkuynbışinbıd gutsybı uftan qa'a.
30 Ẹ̀yin sì wí pé, ‘Àwa ìbá wà ní àsìkò àwọn baba wa, àwa kì bá ní ọwọ́ nínú ẹ̀jẹ̀ àwọn wòlíì’.
Qiyğad şu eyhen: «Şi baba-dideeşine gahıl vuxhaynbıxhiy, manbışika sacigee peyğambaraaşina eb k'yaa'as deşdiy».
31 Ǹjẹ́ ẹ̀yin ni ẹlẹ́rìí fún ara yín pé, ẹ̀yin ni ọmọ àwọn tí ó pa àwọn wòlíì.
Məxüd şu peyğambarar gyapt'ıynbışin uşaxar vuxhay gardanaqa alyaat'a.
32 Àti pé, ẹ̀yin ń tẹ̀lé ìṣísẹ̀ àwọn baba yín. Ẹ̀yin ń kún òsùwọ̀n ìwà búburú wọn dé òkè.
Məxüdxheene, baba-dideeşe gibğılna iş şu g'attivxhan hee'e!
33 “Ẹ̀yin ejò! Ẹ̀yin paramọ́lẹ̀! Ẹ̀yin yóò ti ṣe yọ nínú ẹ̀bi ọ̀run àpáàdì? (Geenna )
Şu xoçebışike g'adıyn xoçebı vod! Nəxübne şu cehinyamıke g'attivxhvanas? (Geenna )
34 Nítorí náà èmi yóò rán àwọn wòlíì àti àwọn ọlọ́gbọ́n ọkùnrin tí ó kún fún ẹ̀mí mímọ́, àti àwọn akọ̀wé sí yín. Ẹ̀yin yóò pa àwọn kan nínú wọn nípa kíkàn wọ́n mọ́ àgbélébùú. Ẹ̀yin yóò fi pàṣán na àwọn ẹlòmíràn nínú Sinagọgu yín, tí ẹ̀yin yóò sì ṣe inúnibíni sí wọn láti ìlú dé ìlú.
Mançil-allab Zı şos peyğambarar, k'orana ək'elynan insanar, mə'əllimar g'uxoole. Şunab, manbışin sabarabı gyapt'asınbı, çarmıxılqa ts'ıts'aa'as. Mansanbıb vuşde sinagogbışee çümqüqqa huvu, şahareençe şahareeqa g'e'eepşes.
35 Kí ẹ̀yin lè jẹ̀bi gbogbo ẹ̀jẹ̀ àwọn olódodo tí ẹ ta sílẹ̀ ní ayé, láti ẹ̀jẹ̀ Abeli títí dé ẹ̀jẹ̀ Sekariah ọmọ Berekiah ẹni tí ẹ pa nínú tẹmpili láàrín ibi pẹpẹ àti ibi ti ẹ yà sí mímọ́ fún Ọlọ́run.
Mançil-allab ç'iyeyne aq'val gyapt'ıyne gırgıne qopkuyne insanaaşine ebal-alla şu cuvab qeles. Şu Habilile gibğıl Berekiyeyna dix Zakariyelqameen qopkuyn insanar gyabat'a vuxha. Mana Zakariyır şu Allahne xaaneyiy q'urbanbı allya'ane cigayne yı'q'nee gik'u.
36 Lóòótọ́ ni mo wí fún yín, gbogbo nǹkan wọ̀nyí yóò wà sórí ìran yìí.
Zı şok'le hək'edacad eyhe, mane gırgıne karbışil-allana caza mane gahıne insanaaşilqa gyuvxhas.
37 “Jerusalẹmu, Jerusalẹmu, ìlú tí ó pa àwọn wòlíì, tí ó sì sọ òkúta lu àwọn tí a rán sí i. Ọ̀pọ̀ ìgbà ni èmi tí ń fẹ́ kó àwọn ọmọ rẹ jọ pọ̀ gẹ́gẹ́ bí àgbébọ̀ adìyẹ ti í dáàbò bo àwọn ọmọ rẹ̀ lábẹ́ ìyẹ́ rẹ, ṣùgbọ́n ẹ̀yin kọ̀.
Ay İyerusalim, İyerusalim, peyğambarar gyabat'ana, vasqa g'axuvuynbı g'ayeqqa hoolena şahar! Xhulene yəqqeesne şit'en çin şit'yaler, xılibışik avqa saa'anbı xhinne Zas yiğın insanar sa'as vukkiykın! Şosmee man ıkkiykın deş!
38 Wò ó, a fi ilé yín sílẹ̀ fún yín ní ahoro.
Həşde ilyaake, vuşun xav g'ulyottul axvas.
39 Nítorí èmi sọ èyí fún yín, ẹ̀yin kì yóò rí mi mọ́, títí ẹ̀yin yóò fi sọ pé, ‘Olùbùkún ni ẹni tó ń bọ̀ ní orúkọ Olúwa.’”
Zımee şokl'e eyhen: «Rəbbine doyuka Qarıyng'us şukur vuxhenava!» şu eyhesmee, şok'le Zı g'aces deş.