< Matthew 20 >

1 “Nítorí ìjọba ọ̀run dàbí ọkùnrin tí ó jẹ́ baálé kan, tí ó jíjáde lọ ní kùtùkùtù òwúrọ̀, tí ó gba àwọn alágbàṣe sínú ọgbà àjàrà rẹ̀.
“Rangmong hasong ah arah likhiik. Saasiit mih wasiit ih rangkhano di heh potiik tong moot suh lakbiitte jamsun kata.
2 Òun pinnu láti san dínárì kan fún iṣẹ́ òòjọ́ kan. Lẹ́yìn èyí ó sì rán wọn lọ sínú ọgbà àjàrà rẹ̀.
Heh ih lakbi thaang ah ngunkholok loosiit heh sa doh kotheng ih baat rum ano, heh phekmoot daapkaat rumta.
3 “Ní wákàtí kẹta ọjọ́ bí ó ti ń kọjá níwájú ilé ìgbanisíṣẹ́, ó rí díẹ̀ nínú àwọn aláìríṣẹ́ tí wọ́n dúró ní ọjà.
Heh thaangsang theng ni kaattiktom saapak akhuh di kah adi heh ih mih tumchap ruh ete japtupta,
4 Ó wí fún wọn pé, ‘Ẹ̀yin pàápàá, ẹ lọ ṣiṣẹ́ nínú ọgbà àjàrà mi, bí ó bá sì di òpin ọjọ́, èmi yóò san iye ti ó bá yẹ fún yín.’
eno baat rumta, ‘sen nep nga phek nah potiik tong roongmoot kah an, ngah ih saasiit lakbi thaang koh et rumha.’
5 Wọ́n sì lọ. “Ó tún jáde lọ́sàn án ní nǹkan bí wákàtí kẹfà àti wákàtí kẹsànán, ó túnṣe bákan náà.
Eno karumta. Erah lidi rangnithung saapoot asih nyi di nyia saasong saapoot ejom di nep heh ih mih emamah et daapkaat rumta.
6 Lọ́jọ́ kan náà ní wákàtí kọkànlá ọjọ́, ó tún jáde sí àárín ìlú, ó sì rí àwọn aláìríṣẹ́ mìíràn tí wọ́n dúró. Ó bi wọ́n pé, ‘Èéṣe tí ẹ̀yin kì í ṣiṣẹ́ ní gbogbo ọjọ́?’
Kaandang ko saapoot banga di, heh thaangsang theng ni we kah adi uh emamah mih tumchap ruh eah rah we tupta. ‘Sen aadi nitang ih tumjih uh lare thang ih tumte thaaba lan?’ heh ih cheng rumta.
7 “Wọ́n sì dáhùn pé, ‘Nítorí pé kò sí ẹni tí yóò fún wa ní iṣẹ́ ṣe.’ “Ó tún sọ fún wọn pé, ‘Ẹ̀yin náà ẹ jáde lọ ṣiṣẹ́ pẹ̀lú nínú ọgbà àjàrà mi.’
Seng biite o uh amuk,’ neng ih ngaakbaatta. ‘Ese, erah ang abah sen uh nga potiik tong ah roongmoot kah an.’ heh ih baat rumta.
8 “Nígbà tí ó di àṣálẹ́, ẹni tó ni ọgbà àjàrà sọ fún aṣojú rẹ̀ pé, ‘Pe àwọn òṣìṣẹ́ náà, kí ó san owó iṣẹ́ wọn fún wọn, bẹ̀rẹ̀ láti ẹni ìkẹyìn lọ sí ti ìṣáájú.’
“Rangjaako di, changte ih heh laksuh asuh baatta, ‘Phek mootte loong ah lompoon uno neng lakbi thaang ah korum uh, lithoon ih kaatte dowa phang korum uno jaakhothoon ih kaatte asuh lithoon et koh uh.’
9 “Nígbà tí àwọn ti a pè ní wákàtí kọkànlá ọjọ́ dé, ẹnìkọ̀ọ̀kan gba owó dínárì kan.
Rangsa kaandang angta tokdi kaatte loong asuh ngunkholok loosiit ru et korum uh.
10 Nígbà tí àwọn tí a gbà ṣiṣẹ́ lákọ̀ọ́kọ́ fẹ́ gba owó tiwọn, èrò wọn ni pé àwọn yóò gba jù bẹ́ẹ̀ lọ, ṣùgbọ́n ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn gba owó dínárì kan.
Erah thoidi rangkhano di kaatte loong ah thok rumha no, neng ih seng bah ehan ih chotte ih thun rumta; ang abah uh neng suh uh ngunkholok loosiit ru et korumta.
11 Bí wọ́n ti ń gbà á, wọ́n ń kùn sí onílẹ̀ náà,
Eno neng ih ngun ah thaang rum ano changte wah ah joobaat rumta.
12 pé, ‘Wákàtí kan péré ni àwọn tí a gbà kẹ́yìn fi ṣiṣẹ́, ìwọ sì san iye kan náà fún wọn àti àwa náà ti a fi gbogbo ọjọ́ ṣiṣẹ́ nínú oòrùn gangan.’
‘Neng ame jeng rumta, arah miloong ah lithoondi saapootsiit luulu ba mothukta, seng ah nitang saakhaam adi mootti, ang abah uh an ih seng suh kohali thanthan korum hu nih!’
13 “Ṣùgbọ́n ó dá ọ̀kan nínú wọn lóhùn pé, ‘Ọ̀rẹ́, kò sí aburú nínú nǹkan tí èmi ṣe sí yín. Kì í ha ṣe pé ẹ̀yin gbà láti ṣiṣẹ́ fún owó dínárì kan.
“‘Nga joonwah loong boichaat an, changte ih wasiit asuh liita, ‘Ngah ih sen tamokwaan rumra, sen suh saasiit lakbi ngunkholok loosiit kottheng ih waanti ah ekot et rumhala.
14 Ó ní, gba èyí tí í ṣé tìrẹ, ki ó sì máa lọ. Èmi fẹ́ láti fún ẹni ìkẹyìn gẹ́gẹ́ bí mo ti fi fún ọ.
Amah ih sen lakbi ngun ah thaang ano nok nah wang an. Ngah ih lithoon ih ra taha loong asuh sen thanthan et kotsuh nooklang.
15 Àbí ó lòdì sí òfin pé kí èmi fún ẹnikẹ́ni ní owó mi bí mo bá yàn láti ṣe bẹ́ẹ̀? Kí ni ìdí tí ìwọ ní láti bínú nítorí èmi ṣe ohun rere?’
Ngah ngun ah nga thungthung ih tanih jen maak kang? Adoleh sen ih nga thungpun lam ih kohang asuh tam siikhaam han?’”
16 “Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ẹni ìkẹyìn yóò di ẹni ìṣáájú, ẹni ìṣáájú yóò sì di ẹni ìkẹyìn.”
Eno Jisu ih thoonbaat rumta, “Erah raangtaan ih o mina liwang thoon angla rah jaakhoh ih hoon ah, eno o jaakhoh thoon angte rah liwang thoon ih hoon ah.”
17 Bí Jesu ti ń gòkè lọ sí Jerusalẹmu, ó pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ méjìlá sí apá kan ó sì wí pé,
Jisu Jirusalem ko ih chookwang adi, lam ni asih wanyi heliphante loong ah hiiksiit rum ano husah tiit baat rumta.
18 “Wò ó, àwa ń gòkè lọ sí Jerusalẹmu. Ó sọ fún wọn pé, a ó fi Ọmọ Ènìyàn lé àwọn olórí àlùfáà àti àwọn olùkọ́ òfin lọ́wọ́, wọn yóò sì dá mi lẹ́bi ikú.
“Boichaat an,” “Seng ah Jirusalem ni chookwangli, eno erah nah Mina Sah ah romwah phokhoh nyia Hootthe nyootte loong lak nah jokoh rum ah. Neng ih kaanju ano tek haat rum ah
19 Wọn yóò sì fà á lé àwọn kèfèrí lọ́wọ́ láti fi ṣe ẹlẹ́yà àti láti náà án, àti láti kàn mi mọ́ àgbélébùú, ní ọjọ́ kẹta, yóò jí dìde.”
eno Ranglajatte loong lak nah korum ah, neng ih ngitkhuung rum ah, ruh ih nep buh rum ah, eno bangphak nah tek haat rum ah, enoothong sa jom lidoh we ngaaksaat eah.”
20 Nígbà náà ni ìyá àwọn ọmọ Sebede bá àwọn ọmọ rẹ̀ wá sọ́dọ̀ Jesu, ó wólẹ̀ lórí eékún rẹ̀, o béèrè fún ojúrere rẹ̀.
Eno Jebidi nusah heh sah miwasah nyi ah siit ano wang taha, eno heh lathong ni kotbon ano heh raangtaan ih re thuk suh, Jisu lasih ah jota.
21 Jesu béèrè pé, “Kí ni ìwọ ń fẹ́?” Ó sì dáhùn pé, “Jẹ́ kí àwọn ọmọ mi méjèèjì jókòó ní apá ọ̀tún àti apá òsì lórí ìtẹ́ ìjọba rẹ?”
“An tumjih suh nook uh?” Jisu ih chengta. Minuh rah ih ngaakbaatta, “An ih kakham hang, nga sah miwah sah nyia ah an luungwang ang udoh esiit ah dak hekko, esiit ah jaawah ko ih tongthuk uh.”
22 Ṣùgbọ́n Jesu dáhùn ó sì wí pé, “Ẹ̀yin kò mọ ohun tí ẹ̀yin ń béèrè, ẹ̀yin ha le mu nínú ago tí èmi ó mu?” Wọ́n dáhùn pé, “Àwa lè mu ún.”
“Set ih tumjih suh hansih erah tajat kansih,” nyi suh liita. “Ngah ih marah chamchoh khap dowa jok ang erah ejen roong jok ni et hansih?” “Ejen roong jok heetih,” nyi ih ngaakbaatta.
23 Jesu sì wí fún wọn pé, “Dájúdájú, ẹ̀yin yóò mu nínú ago mi, ṣùgbọ́n èmi kò ní àṣẹ láti sọ irú ènìyàn tí yóò jókòó ní apá ọ̀tún tàbí apá òsì. Baba mi ti pèsè ààyè wọ̀n-ọn-nì sílẹ̀ fún kìkì àwọn tí ó yàn.”
“Jisu ih li nyuuta, setnyi eh ejen roong jok mok et hansih, “enoothong ngah dak hek jaawah o roong tongha erah ngah ih tajen dandje nyuura. Erah bah seng Wah ih o suh ban hoonha erah ba chotong ah.”
24 Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mẹ́wàá ìyókù sì gbọ́ èyí, wọ́n bínú sí àwọn arákùnrin méjì yìí.
Heliphante wah asih loong ih erah chaat rum ano, soophonyi asuh rapne ih khah rumta.
25 Ṣùgbọ́n Jesu pé wọ́n papọ̀, ó wí pé, “Dájúdájú, ẹ̀yin mọ̀ pé àwọn ọba aláìkọlà a máa lo agbára lórí wọn, àwọn ẹni ńlá láàrín wọn a sì máa fi ọlá tẹrí àwọn tí ó wà lábẹ́ wọn ba.
Erah thoidi Jisu ih loongtang lompoon rum ano baat rumta, “Sen ih jat ehan ranglajatte mina loong pante adi jaatrep chaan jeela, eno mihak phokhoh loong adi jirep chaan aphaan jeela.
26 Ṣùgbọ́n èyí yàtọ̀ láàrín yín. Dípò bẹ́ẹ̀, ẹni tí ó bá ń fẹ́ ṣe olórí láàrín yín, ní láti ṣe bí ìránṣẹ́ fún yín ni,
Erah bah uh, sen loong chamchi nah bah lah angjih. Sendung dowa o ih bah uh elong hoon tenthun ang anbah, wahoh laksuh jaatjaat chaak angjih;
27 àti ẹni tí ó bá fẹ́ ṣe olórí nínú yín, ẹ jẹ́ kí ó máa ṣe ọmọ ọ̀dọ̀ yin.
adoleh sendung dowa jaakhoh angsuh thunte je anbah, sen ah wahoh dah elang jaatjaat eejih—
28 Gẹ́gẹ́ bí Ọmọ Ènìyàn kò ṣe wá sí ayé, kí ẹ lè ṣe ìránṣẹ́ fún un, ṣùgbọ́n láti ṣe ìránṣẹ́ fún yín, àti láti fi ẹ̀mí rẹ ṣe ìràpadà ọ̀pọ̀ ènìyàn.”
Mina Sah ah botseh mootkaat thuk suh tara taha, erah nang ih heteewah ah moh suh nyia mina hantek puipang suh ra taha.”
29 Bí Jesu àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ti ń fi ìlú Jeriko sílẹ̀, ọ̀pọ̀ ènìyàn sì wọ́ tẹ̀lé e lẹ́yìn.
Jisu nyi heliphante loong Jeriko nawa dokkhoom rum adi, miloong hantek roong phankhoom rumta.
30 Àwọn ọkùnrin afọ́jú méjì sì jókòó lẹ́bàá ọ̀nà, nígbà tí wọ́n sí gbọ́ pé Jesu ń kọjá lọ, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí í kígbe pé, “Olúwa, Ọmọ Dafidi, ṣàánú fún wa!”
Edook wanyi lamkaang ni tong nyuutta wanyi ah ih Jisu daankhoom ah chaat nyu ano, toonriing nyuuta, “Dewid sah! Sek ah minchan we heetih.
31 Àwọn ènìyàn sí bá wọn wí pé kí wọn dákẹ́, ṣùgbọ́n wọ́n kígbe sókè sí i. “Olúwa, ọmọ Dafidi, ṣàánú fún wa!”
Miloong ih nyi ah kanja rum ano suusu ih tong suh baat rumta. Ang abah uh nyi ah erong rongwah ih boot riing nyuuta, “Dewid sah! Chuupha, Sek ah minchan weehe tih!”
32 Jesu dúró lójú ọ̀nà, ó sì pè wọ́n, Ó béèrè pé, “Kí ni ẹ̀yin fẹ́ kí èmi ṣe fún yín?”
Jisu ih tangchap ano poon nyuuta. “Ngah ih set suh tumjih jen re konyu ha?” heh ih cheng nyuuta.
33 Wọ́n dáhùn pé, “Olúwa, àwa fẹ́ kí a ríran.”
“Chuupha,” sek mik kaasiit jamhiitih!”
34 Àánú wọn sì ṣe Jesu, ó fi ọwọ́ kan ojú wọn. Lójúkan náà, wọ́n sì ríran, wọ́n sì ń tọ̀ ọ́ lẹ́yìn.
Jisu heh minchan ah dong ano nyi mik adi taajota; erah damdam nyi ih laantup ruh ih nyuuta, eno roong phankhoom nyuuta.

< Matthew 20 >