< Matthew 17 >

1 Lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́fà, Jesu mú Peteru, Jakọbu àti Johanu arákùnrin rẹ̀, ó mú wọn lọ sí orí òkè gíga kan tí ó dádúró.
Eso gafeyale aligili, Yesu da Bida, Ya: mese amola Yone, ili oule asili, ilisu goumiba: le heda: le, esalu.
2 Níbẹ̀ ara rẹ̀ yí padà níwájú wọn. Ojú rẹ̀ sì ràn bí oòrùn, aṣọ rẹ̀ sì funfun bí ìmọ́lẹ̀.
Ilia ba: loba, Yesu Ea da: i da afadenene, Ea odagi da eso ea hadigi agoai ba: i. Ea abula amola da ahea: ia: i hadigi bagade agoane hamobe ba: i.
3 Lójijì, Mose àti Elijah fi ara hàn, wọ́n sì ń bá Jesu sọ̀rọ̀.
Ilia ba: loba, Mousese amola Elaidia, Yesu ili sia: dalebe ba: i.
4 Peteru sọ fún Jesu pé, “Olúwa, jẹ́ kí a kúkú máa gbé níhìn-ín yìí. Bí ìwọ bá fẹ́, èmi yóò pa àgọ́ mẹ́ta, ọ̀kan fún ọ, ọ̀kan fún Mose, àti ọ̀kan fún Elijah.”
Bida da Yesuma amane sia: i, “Hina! Ninia guiguda: esalebeba: le hahawane bagade. Di da nama sia: sea, na da diasu udiana gagumu, Di, Mousese amola Elaidia golama: ne, na da diligili hiougimu.”
5 Bí Peteru ti sọ̀rọ̀ tán, àwọsánmọ̀ dídán síji bò wọ́n, láti inú rẹ̀ ohùn kan wí pé, “Èyí ni àyànfẹ́ ọmọ mi, ẹni ti inú mi dùn sí gidigidi. Ẹ máa gbọ́ tirẹ̀!”
Ea amane sia: nanoba, mumobi hadigiwane sa: ili, ili huluane uligi dagoi. Mumobi ganodini, sia: bagade nabi amo, “Go da Na dogolegei Manodafa. Ea sia: nabima!”
6 Bí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn ti gbọ́ èyí, wọ́n dojúbolẹ̀. Ẹ̀rù sì bà wọ́n gidigidi.
Amo sia: nabaloba, Yesu Ea ado ba: su dunu da beda: iba: le, osoboga gala: la sa: i
7 Ṣùgbọ́n Jesu sì tọ̀ wọ́n wá. Ó fi ọwọ́ kàn wọ́n, ó wí pé, “Ẹ dìde, ẹ má ṣe bẹ̀rù.”
Be Yesu da misini, ilia da: i digili ba: i. E da ilima amane sia: i, “Dilia wa: legadoma! Mae beda: ma!”
8 Nígbà tí wọ́n sì gbé ojú wọn sókè, tí wọ́n sì wò ó, Jesu nìkan ni wọn rí.
Ilia da si ba: le gadoloba, Yesu fawane ba: i.
9 Bí wọ́n sì ti ń sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè, Jesu pàṣẹ fún wọn pé, “Ẹ kò gbọdọ̀ sọ fún ẹnikẹ́ni ohun tí ẹ rí, títí Ọmọ Ènìyàn yóò fi jí dìde kúrò nínú òkú.”
Ilia da goumiba: le bu daloba, Yesu da ilima amane sia: i, “Dilia waha ba: i liligi eno dunu ilima mae adoma! Dunu Egefe da bogole, bu wa: legadolesi ba: sea, amo esoga fawane olelema.”
10 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ béèrè lọ́wọ́ rẹ́ pé, “Kí ni ó fà á tí àwọn olùkọ́ òfin fi ń wí pé, Elijah ní láti kọ́ padà wá?”
Yesu Ea ado ba: su dunu da Ema amane adole ba: i, “Sema sia: olelesu dunu da abuliba: le, Elaidia da hidadea misunu, amo olelesala: ?”
11 Jesu sì dáhùn pé, “Dájúdájú òtítọ́ ni wọ́n ń sọ. Elijah wá láti fi gbogbo nǹkan sí ipò.
Yesu E bu adole i, “Dafawane! Elaidia da hidadea logo fodomusa: misunu.
12 Ṣùgbọ́n èmi wí fún yín lóòótọ́; Elijah ti dé. Ṣùgbọ́n wọn kò mọ̀ ọ́n, ọ̀pọ̀ tilẹ̀ hu ìwà búburú sí i. Bákan náà, Ọmọ Ènìyàn náà yóò jìyà lọ́wọ́ wọn pẹ̀lú.”
Be Na da dilima sia: sa. Elaidia da bu misi dagoi. Be osobo bagade dunu da ea misi hame dawa: i galu. Ilia da ili hanai asigi dawa: su hou amoga ema hamoi dagoi. Amo hou defele ilia da Dunu Egefe Ema hamomuba: le, E da se nabimu.”
13 Nígbà náà, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mọ̀ pé ó n sọ̀rọ̀ nípa Johanu onítẹ̀bọmi fún wọn ni.
Amalalu, Ea ado ba: su dunu da E da Yone Ba: bodaise ea hou ilima olelei, amo ilia da dawa: i galu.
14 Nígbà tí wọ́n sì dé ọ̀dọ̀ ìjọ ènìyàn, ọkùnrin kan tọ̀ Jesu wá, ó sì wólẹ̀ níwájú rẹ̀, ó wí pé,
Yesu amola Ea ado ba: su dunu da eno dunu gilisibi amoga doaga: i. Dunu afadafa da Yesuma misini, muguni bugili,
15 “Olúwa, ṣàánú fún ọmọ mi, nítorí tí ó ní wárápá. Ó sì ń joró gidigidi, nígbà púpọ̀ ni ó máa ń ṣubú sínú iná tàbí sínú omi.
Yesuma amane sia: i, “Hina! Di da nagofema asigima! E da sidisu hamobeba: le, e da eso enoga nasuba dafasa, enoga hanoa sidina daha.
16 Mo sì ti mú un tọ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ, ṣùgbọ́n wọn kò lè wò ó sàn.”
Na mano amo Dia ado ba: su dunuma uhima: ne oule misi. Be ilia sia: ne ba: loba hamedei galu.”
17 Jesu sì dáhùn wí pé, “A! Ẹ̀yìn alágídí ọkàn àti aláìgbàgbọ́ ènìyàn, èmi yóò ti bá yín gbé pẹ́ tó? Èmi ó sì ti fi ara dà á fún yín tó? Ẹ mú un wá sọ́dọ̀ mi níhìn-ín yìí.”
Yesu E amane sia: i, “Dilia da dafawaneyale hame dawa: su amola giadofasu fi dunu! Na da eso habodayane dili amola guiguda: esaloma: bela: ? Na da eso habodayane dilia giadofasu hou ba: ma: bela: ? Amo mano Nama oule misa!”
18 Nígbà náà ni Jesu bá ẹ̀mí èṣù tí ó ń bẹ nínú ọmọkùnrin náà wí, ó sì fi í sílẹ̀, à mú ọmọkùnrin náà láradá láti ìgbà náà lọ.
Yesu E da Fio liligi amo mano ea dogo ganodini esalu, amoma gasawane sia: i. Amalalu, Fio liligi da fadegale fasi dagoi. Goi da bu uhinisi dagoi ba: i.
19 Lẹ́yìn èyí, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì bi Jesu níkọ̀kọ̀ pé, “Èéṣe tí àwa kò lè lé ẹ̀mí èṣù náà jáde?”
Fa: no, Yesu Ea ado ba: su dunu da wamowane Ema misini, amane sia: i, “Ninia da wadela: i liligi fadegale fasimu da abuli hamedebela: ?”
20 Jesu sọ fún wọn pé, “Nítorí ìgbàgbọ́ yín kéré. Lóòótọ́ ni mo wí fún yin, bí ẹ bá ni ìgbàgbọ́, bí ó tilẹ̀ kéré bí hóró musitadi, ẹ̀yin lè wí fún òkè yìí pé, ‘Sípò kúrò níhìn-ín yìí,’ òun yóò sì ṣí ipò. Kò sì ní sí ohun tí kò ní í ṣe é ṣe fún yín.”
E amane sia: i, “Dilia dafawaneyale dawa: su hou da fonobahadiba: le, dilia fadegamu da hamedei ba: i. Na da dafawane sia: sa! Dilia dafawaneyale dawa: su hou da masada ea hawa: defele ba: sea, dilia da amo goumi ea dialebe sogebi yolesili eno sogega masa: ne sia: sea, goumi da dilia sia: i nabawane hamomu. Dilia da liligi huludafa hamomu defele ba: mu.
Be ha: i mae nawane bagade sia: ne gadosea fawane da gasa bagade Fio waha ba: i da mugulumu.
22 Nígbà tí wọ́n sì ti wà ní Galili, Jesu sọ fún wọn pé, “Láìpẹ́ yìí a ó fi Ọmọ Ènìyàn lé àwọn ènìyàn lọ́wọ́.
Yesu amola Ea ado ba: su dunu da gilisili Ga: lili sogega ahoana, E da ilima amane sia: i, “Dunu afae da Dunu Egefe amo hohonone, eno osobo bagade dunu ilima imunu.
23 Wọn yóò sì pa á, ní ọjọ́ kẹta lẹ́yìn èyí, yóò sì jí dìde sí ìyè.” Ọkàn àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì kún fún ìbànújẹ́ gidigidi.
Amasea, ilia da Dunu Egefe medole legemu. E da eso udiana aligili bu uhini wa: legadomu.” Amo sia: nabaloba, ilia da da: i dioi bagade nabi.
24 Nígbà tí Jesu àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì dé Kapernaumu, àwọn agbowó òde tí ń gba owó idẹ méjì tó jẹ́ owó tẹmpili tọ Peteru wá wọ́n sì bí i pé, “Ǹjẹ́ olùkọ́ yín ń san owó tẹmpili?”
Yesu amola Ea ado ba: su dunu da Gabena: ia: me moilaiga doaga: loba, Debolo Diasu su lidisu dunu ilia da Bidama misini, ema amane sia: i, “Dia olelesu dunu da Debolo Diasu su iahala: ?”
25 Peteru sì dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, ó ń san.” Nígbà tí Peteru wọ ilé láti bá Jesu sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀, Jesu ni ó kọ́kọ́ sọ̀rọ̀, Jesu bí i pé, “Kí ni ìwọ rò, Simoni? Ǹjẹ́ àwọn ọba ayé ń gba owó orí lọ́wọ́ àwọn ọmọ wọn tàbí lọ́wọ́ àwọn àlejò?”
Bida da bu adole i, “Ma!” E da bu diasu ganodini ahoanoba, Yesu da hidadea ema sia: i, “Saimone! Di adi dawa: bela: ? Osobo bagade hina bagade dunu ilia da nowama su (da: gisi) labala? Ilia da ilia mano ilima labala? O eno dunuma labala?”
26 Peteru dáhùn pé, “Lọ́wọ́ àwọn àlejò ni.” Jesu sì tún wí pé, “Èyí jẹ́ wí pé àwọn ọmọ onílẹ̀ kì í san owó òde?
Bida da bu adole i, “Ilia da eno dunuma laha.” Yesu E amane sia: i, “Amaiba: le, ilia mano da su hame imunu.
27 Síbẹ̀síbẹ̀, àwa kò fẹ́ mú wọn bínú. Nítorí náà, ẹ lọ sí etí Òkun, kí ẹ sì sọ ìwọ̀ sí omi. Ẹ mú ẹja àkọ́kọ́ tí ẹ kọ́ fà sókè, ẹ ya ẹnu rẹ̀, ẹ̀yin yóò sì rí owó idẹ kan níbẹ̀, ki ẹ fi fún wọn fún owó orí tèmi àti tirẹ̀.”
Be su lidisu dunu da udigili fofogadigisa: besa: le, di hanoga sa: ili, dimani adoma. Menabo hiougisia, ea lafi dagale, ganodini muni fage ba: mu. Amo fage lale, su lidisu dunuma dia su iasu amola Na su iasu defele ima.”

< Matthew 17 >