< Matthew 16 >

1 Àwọn Farisi àti àwọn Sadusi wá láti dán Jesu wò. Wọ́n ní kí ó fi àmì ńlá kan hàn àwọn ní ojú ọ̀run.
Pharise avang ja Sadukee law u lü Jesuh ami mhnütnak vaia Pamhnam naw ning ksingki ti a ngsingnak vaia, müncankse jah mhnuha” ti lü täkie.
2 Ó dá wọn lóhùn pé, “Nígbà tí ó bá di àṣálẹ́, ẹ ó sọ pé, ‘Ìbá dára kí ojú ọ̀run pọ́n.’
Jesuh naw jah msang lü, “Khaw kyak law hlü üng, ‘Khankhaw mliki khawngawi ta khaw sen hlü ve’ nami ti khawiki.”
3 Ní òwúrọ̀, ‘Ẹ̀yin yóò wí pé ọjọ́ kì yóò dára lónìí, nítorí ti ojú ọ̀run pọ́n, ó sì ṣú dẹ̀dẹ̀,’ ẹ̀yin àgàbàgebè, ẹ̀yin le sọ àmì ojú ọ̀run, ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò le mọ àmì àwọn àkókò wọ̀nyí.
Ngawilama, “Khaw ngmei lü anghmüp law üng, tuhngawi ta khaw ah hlü ve,” nami ti khawiki. Khawa sen vai ja a ak vai cun khankhaw teng lü nami ksing kyawkie. Cunüngpi akcünmka üng sängeikia müncanksee ta am ksing khawh uki.
4 Ìran búburú aláìgbàgbọ́ yìí ń béèrè àmì àjèjì mélòó kàn ni ojú sánmọ̀, ṣùgbọ́n a kí yóò fún ẹnìkankan ní àmì bí kò ṣe àmì Jona.” Nígbà náà ni Jesu fi wọ́n sílẹ̀, ó sì bá tirẹ̀ lọ.
“Tuh kän khyang he ihlawka se lü mtuihmlehkie ni. Nangmi naw müncankse nami täkie aw? Jonaha müncanksea thea i käh ning jah mhnuh vai” ti lü a jah ceh tak.
5 Nígbà tí wọ́n dé apá kejì adágún, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ṣàkíyèsí pé wọ́n ti gbàgbé láti mú àkàrà kankan lọ́wọ́.
Acunüng, axüisaw he tuilia cayea ami law üng, muk law vai ami mhnih.
6 Jesu sì kìlọ̀ fún wọn pé, “Ẹ kíyèsára, ẹ sì ṣọ́ra, ní ti ìwúkàrà àwọn Farisi àti àwọn Sadusi.”
Jesuh naw, “Pharise he ja Sadukeea nghngen nami jah cäieinak vai,” a ti.
7 Wọ́n ń sọ eléyìí ni àárín ara wọn wí pé, “Nítorí tí àwa kò mú àkàrà lọ́wọ́ ni.”
Animäte naw ngai u lü, “Ahin hin muk am mi lawpüia phäha kya ngaiki,” ami ti.
8 Nígbà tí ó gbọ́ ohun ti wọ́n ń sọ, Jesu béèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Ẹ̀yin onígbàgbọ́ kékeré, èéṣe tí ẹ̀yin ń dààmú ara yín pé ẹ̀yin kò mú oúnjẹ lọ́wọ́?
Jesuh naw ami pyen ksing lü, “Jumeinak ngcekia khyang he aw, i nami sumkyamkie ni. Ise muk am nami taka phäh vaia nami ngaikie ni?
9 Tàbí ọ̀rọ̀ kò yé yín di ìsinsin yìí? Ẹ̀yin kò rántí pé mo bọ́ ẹgbẹ̀rún márùn-ún ènìyàn pẹ̀lú ìṣù àkàrà márùn-ún àti iye agbọ̀n tí ẹ kójọ bí àjẹkù?
Muk mhma pacawng thawng mhmaa phäh ka bo cen am nami sümkie aw? Cä ikän ja nami msap law? Am nami ksing hamkie aw?
10 Ẹ kò sì tún rántí ìṣù méje tí mo fi bọ́ ẹgbàajì ènìyàn àti iye agbọ̀n tí ẹ̀yín kójọ?
Muk khyüh khyang thawng kphyü naw ei u se, cä ikän hläiki ti am nami sümkie aw?
11 Èéha ṣe tí kò fi yé yín pé èmi kò sọ̀rọ̀ nípa ti àkàrà? Lẹ́ẹ̀kan sí i, mo wí fún yín, ẹ ṣọ́ra fún ìwúkàrà àwọn Farisi àti ti Sadusi.”
“Eia mawng ka ning jah mthehki am ni, ise am nami ksing u ni? Pharise he ja Sadukeea ngneikse nami cäieinak vaia ka ning jah mthehki ni,” a ti.
12 Nígbà náà ni ó ṣẹ̀ṣẹ̀ wáyé wọn pé, kì í ṣe nípa ti ìwúkàrà ní ó sọ wí pé kí wọ́n kíyèsára, bí kò ṣe tí ẹ̀kọ́ àwọn Farisi àti Sadusi.
Acunüng muk üng ami kcaw nghngen a pyen am ni, Pharise he ja Sadukeea jah mtheimthangnak ami cäieinak vaia a jah mtheh tia ami ksing.
13 Nígbà tí Jesu sì dé Kesarea-Filipi, ó bi àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Ta ni àwọn ènìyàn ń fi Ọmọ Ènìyàn pè?”
Jesuh Kesari Philipih mlüh pei cit lü acuia axüisaw he üng, “Khyang he naw Khyanga Capa hin u ami pyen ni,” ti lü a jah kthäh.
14 Wọ́n dá a lóhùn pé, “Àwọn kan ni Johanu onítẹ̀bọmi ni, àwọn mìíràn wí pé, Elijah ni, àwọn mìíràn wí pé, Jeremiah ni, tàbí ọ̀kan nínú àwọn wòlíì.”
“Amsah naw Baptican Johan, amsah naw Elijah, amsah naw Jeramih, am ani üng sahma mat mat va ni khai ti ve u,” ami ti.
15 “Ṣùgbọ́n ẹyin ń kọ?” Ó bi í léèrè pé, “Ta ni ẹ̀yin ń fi mi pè?”
Jesuh naw, “Nangmi naw mä ua jah nami na ngaih?” a ti.
16 Simoni Peteru dáhùn pé, “Ìwọ ni Kristi náà, Ọmọ Ọlọ́run alààyè.”
Sihmon Pita naw, “Nang cun Khritaw, xüngseiki Pamhnama Capa ni,” a ti.
17 Jesu sì wí fún un pé, “Alábùkún fún ni ìwọ Simoni ọmọ Jona, nítorí ẹran-ara àti ẹ̀jẹ̀ kọ́ ló fi èyí hàn bí kò ṣe Baba mi tí ó ń bẹ ní ọ̀run.
Jesuh naw msang lü“Johana ca Sihmon, na jo daw ve. Isetiüng ta, ahin hin khyanga ning mtheh am ni, khana ka Pa naw a ning mtheh ni.”
18 Èmi wí fún ọ, ìwọ ni Peteru àti pé orí àpáta yìí ni èmi yóò kọ́ ìjọ mi lé, àti ẹnu-ọ̀nà ipò òkú kì yóò lè borí rẹ̀. (Hadēs g86)
Ka ning mthehki, Pita aw nang lung ni, ahina lunga khana ka sangcim ka mdüih khai, thihnak naw pi käh näng khai ni. (Hadēs g86)
19 Èmi yóò fún ní àwọn kọ́kọ́rọ́ ìjọba Ọ̀run; ohun tí ìwọ bá dè ní ayé, òun ni a ó dè ní ọ̀run. Ohunkóhun tí ìwọ bá sì tú ní ayé yìí, a ó sì tú ní ọ̀run.”
Khankhaw Pe tawhe ka ning pe khai, aipi khawmdek khana am na mhlät naküt cun khankhawa pi mhläta am kya, ai naküt pi khawmdek khana na mhlät cun khankhawa pi mhläta kya khai,” a ti.
20 Nígbà náà ó kìlọ̀ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé wọn kò gbọdọ̀ sọ fún ẹnikẹ́ni pé Òun ni Kristi náà.
Acunüng axüisaw he üng Khritaw a ninak u üng pi käh ami mtheh vaia a jah mtheh.
21 Láti ìgbà yìí lọ, Jesu bẹ̀rẹ̀ sí ṣàlàyé fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ kedere nípa lílọ sí Jerusalẹmu láti jẹ ọ̀pọ̀ ìyà lọ́wọ́ àwọn àgbàgbà, àwọn olórí àlùfáà àti àwọn akọ̀wé, kí a sì pa òun, àti ní ọjọ́ kẹta, kí ó sì jíǹde.
Acunüng tünei lü Jesuh naw “Jerusalema ka cit khai, axüe, ktaiyü he ja thumksingea mkhuimkhanak ka khamei khai. Na hnim khaie, cunüngpi amhnüp kthum üng ka tho be khai” ti lü axüisaw he üng a jah mtheh.
22 Peteru mú Jesu sí ẹ̀gbẹ́ kan, ó bẹ̀rẹ̀ sí í bá a wí pé, “Kí a má rí i Olúwa! Èyí kì yóò ṣẹlẹ̀ sí Ọ!”
Pita naw akcea khü lü, “Bawipa aw, acukba käh kya khai, na khana acukba käh thawn yah khai,” ti lü Jesuh a pyen.
23 Jesu pa ojú dà, ó sì wí fún Peteru pé, “Kúrò lẹ́yìn mi, Satani! Ohun ìkọ̀sẹ̀ ni ìwọ jẹ́ fún mi; ìwọ kò ro ohun tí i ṣe ti Ọlọ́run, bí kò ṣe èyí ti ṣe ti ènìyàn.”
Jesuh naw nghlat law lü Pita üng, “Khawyam aw, ka peia käh vea, nang hin ka kyukngtängnak vaia na kyaki ni. Isetiakyaküng, na ngaihnak hin Mhnam üngka naw lawki am ni, khyang üngka naw lawki ni,” a ti.
24 Nígbà náà ni Jesu wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Bí ẹnikẹ́ni bá fẹ́ tọ̀ mí lẹ́yìn, kí ó sẹ́ ara rẹ̀, kí ó sì gbé àgbélébùú rẹ̀, kí ó sì máa tọ̀ mí lẹ́yìn.
Jesuh naw axüisaw he üng, “Nangmi üngka mat naw ka hnu läk khaia a bü üng a hlükaw naküt hawih lü, amäta kutlamktung kawt lü na läk law se.”
25 Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ gba ẹ̀mí rẹ̀ là, yóò sọ ẹ̀mí rẹ̀ nù ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ ẹ̀mí rẹ̀ nù nítorí mi, yóò rí i.
Na sak küinak khaia na bü üng sak am yahki, cunüngpi keia phäha na sak tawn khaia na bü üng ta angsäi xünnak na yah khai,” a ti.
26 Èrè kí ni ó jẹ́ fún ènìyàn bí ó bá jèrè gbogbo ayé yìí, tí ó sì sọ ẹ̀mí rẹ̀ nù? Tàbí kí ni ènìyàn yóò fi dípò ẹ̀mí rẹ̀?
Khyang naw khawmdeknu avan ka na lü, a ngmüimkhya xünnak am a yah üng i am ni a thawnei be thei kawm?
27 Nítorí Ọmọ Ènìyàn yóò wá nínú ògo baba rẹ pẹ̀lú àwọn angẹli rẹ̀, nígbà náà ni yóò sì san án fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀.
Khyanga Capa, a pa hlüngtainak ja a khankhawngsä he am law be hnühki, khyang naküt cun khut a pawha kba jah kheng khai.
28 “Lóòótọ́ ni mo wí fún yín. Ẹlòmíràn wà nínú àwọn tí ó wà níhìn-ín yìí, tí kì yóò ri ikú títí wọn ó fi rí Ọmọ Ènìyàn tí yóò máa bọ̀ ní ìjọba rẹ̀.”
Akcanga ka ning jah mthehki, “Ahin üng awmki he avang naw am thih ham u lü, Khyanga Capa Sangpuxanga kba law be se hmuh khaie,” a ti.

< Matthew 16 >