< Matthew 14 >

1 Ní àkókò náà ni Herodu ọba tetrarki gbọ́ nípa òkìkí Jesu,
U qaƣlarda, Ⱨerod ⱨakim Əysaning nam-xɵⱨritidin hǝwǝr tepip,
2 ó wí fún àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ pé, “Dájúdájú Johanu onítẹ̀bọmi ni èyí, ó jíǹde kúrò nínú òkú. Ìdí nìyí tí ó fi ní agbára láti ṣiṣẹ́ ìyanu wọ̀nyí.”
hizmǝtkarlirigǝ: — Bu adǝm qɵmüldürgüqi Yǝⱨya bolidu, u ɵlümdin tirilgǝn bolsa kerǝk. Xuning üqün muxu alaⱨidǝ ⱪudrǝtlǝr uningda küqini kɵrsǝtmǝktǝ, — dedi.
3 Nísinsin yìí Herodu ti mú Johanu, ó fi ẹ̀wọ̀n dè é, ó sì fi sínú túbú, nítorí Herodia aya Filipi arákùnrin rẹ̀,
Ⱨerodning bundaⱪ deyixining sǝwǝbi, u [ɵgǝy] akisi Filipning ayali Ⱨerodiyǝning wǝjidin Yǝⱨyani tutⱪun ⱪilip, zindanƣa taxliƣanidi.
4 nítorí Johanu onítẹ̀bọmi ti sọ fún Herodu pé, “Kò yẹ fún ọ láti fẹ́ obìnrin náà.”
Qünki Yǝⱨya Ⱨerodⱪa [tǝnbiⱨ berip]: «Bu ayalni tartiwelixing Tǝwrat ⱪanuniƣa hilaptur» dǝp kǝlgǝnidi.
5 Herodu fẹ́ pa Johanu, ṣùgbọ́n ó bẹ̀rù àwọn ènìyàn nítorí gbogbo ènìyàn gbàgbọ́ pé wòlíì ni.
Ⱨerod [xu sǝwǝbtin] Yǝⱨyani ɵltürmǝkqi bolƣan bolsimu, biraⱪ halayiⱪtin ⱪorⱪⱪanidi, qünki ular Yǝⱨyani pǝyƣǝmbǝr, dǝp bilǝtti.
6 Ní ọjọ́ àsè ìrántí ọjọ́ ìbí Herodu, ọmọ Herodia obìnrin jó dáradára, ó sì tẹ́ Herodu lọ́run gidigidi.
Əmma Ⱨerodning tuƣulƣan küni tǝbriklǝngǝndǝ, ayali Ⱨerodiyǝning ⱪizi otturiƣa qiⱪip ussul oynap bǝrdi. Bu Ⱨerodⱪa bǝk yaⱪti;
7 Nítorí náà ni ó ṣe fi ìbúra ṣe ìlérí láti fún un ní ohunkóhun ti ó bá béèrè fún.
xuning üqün u uningƣa: — Ⱨǝrnemǝ tilisǝng xuni sanga berǝy, dǝp ⱪǝsǝm ⱪildi.
8 Pẹ̀lú ìmọ̀ràn láti ọ̀dọ̀ ìyá rẹ̀, ó béèrè pé, “Fún mi ni orí Johanu onítẹ̀bọmi nínú àwopọ̀kọ́”.
Lekin ⱪiz anisining küxkürtüxi bilǝn: — Qɵmüldürgüqi Yǝⱨyaning kallisini elip, bir tǝhsigǝ ⱪoyup ǝkǝlsilǝ, — dedi.
9 Inú ọba bàjẹ́ gidigidi, ṣùgbọ́n nítorí ìbúra rẹ̀ àti kí ojú má ba à tì í níwájú àwọn àlejò tó wà ba jẹ àsè, ó pàṣẹ pé kí wọ́n fún un gẹ́gẹ́ bí o ti fẹ́.
Padixaⱨ buningƣa ⱨǝsrǝt qǝkkǝn bolsimu, ⱪǝsǝmliri tüpǝylidin wǝ dastihanda olturƣanlar wǝjidin, [kallisini] elip kelinglar, dǝp buyrudi.
10 Nítorí náà, a bẹ́ orí Johanu onítẹ̀bọmi nínú ilé túbú.
U adǝm ǝwǝtip, zindanda Yǝⱨyaning kallisini aldurdi.
11 A sì gbé orí rẹ̀ jáde láti fi fún ọmọbìnrin náà nínú àwopọ̀kọ́, òun sì gbà á, ó gbé e tọ ìyá rẹ̀ lọ.
Xuning bilǝn kallisi bir tǝhsigǝ ⱪoyulup, ⱪizning aldiƣa elip kelindi. Ⱪiz buni anisining aldiƣa apardi.
12 Lẹ́yìn náà, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Johanu wá gba òkú rẹ̀, wọ́n sì sin ín. Wọ́n sì wá sọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún Jesu.
[Yǝⱨyaning] muhlisliri bolsa berip, jǝsǝtni elip dǝpnǝ ⱪildi; andin berip Əysaƣa bu ixlarni hǝwǝr ⱪildi.
13 Nígbà tí Jesu gbọ́ ìròyìn ìṣẹ̀lẹ̀ náà, ó kúrò níbẹ̀, ó bá ọkọ̀ ojú omi lọ sí ibi kọ́lọ́fín kan ní èbúté láti dá wà níbẹ̀. Nígbà tí wọ́n gbọ́ èyí, ọ̀pọ̀ ènìyàn sì fi ẹsẹ̀ rìn tẹ̀lé e láti ọ̀pọ̀ ìlú wọn.
Əysa bu hǝwǝrni anglap, ɵzi yalƣuz pinⱨan bir jayƣa ketǝy dǝp bir kemigǝ olturup u yǝrdin ayrildi. Halayiⱪ buning hǝwirini tapⱪanda, ǝtraptiki xǝⱨǝrlǝrdin kelixip, uning kǝynidin piyadǝ mangdi.
14 Nígbà ti Jesu gúnlẹ̀, tí ó sì rí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn, inú rẹ̀ yọ́ sí wọn, ó sì mú àwọn aláìsàn láradá.
U [ ⱪirƣaⱪⱪa] qiⱪip kǝtkinidǝ, zor bir top adǝmlǝrni kɵrüwidi, ularƣa iq aƣritip, ularning aƣriⱪlirini saⱪaytti.
15 Nígbà ti ilẹ̀ ń ṣú lọ, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ tọ̀ ọ́ wá, wọ́n sì wí pé, “Ibi yìí jìnnà sí ìlú ilẹ̀ sì ń ṣú lọ. Rán àwọn ènìyàn lọ sí àwọn ìletò kí wọ́n lè ra oúnjẹ jẹ.”
Kǝq kirgǝndǝ, muhlisliri uning yeniƣa kelip: — Bu qɵl bir jay ikǝn, waⱪitmu bir yǝrgǝ berip ⱪaldi. Halayiⱪni yolƣa seliwǝtkǝn bolsang, andin ular kǝntlǝrgǝ berip ɵzlirigǝ ozuⱪ setiwalsun, — dedi.
16 Ṣùgbọ́n Jesu fèsì pé, “Kò nílò kí wọ́n lọ kúrò. Ẹ fún wọn ní oúnjẹ.”
Lekin Əysa ularƣa: — Ularning ketixining ⱨajiti yoⱪ, ɵzünglar ularƣa ozuⱪ beringlar, — dedi.
17 Wọ́n sì dalóhùn pé, “Àwa kò ní ju ìṣù àkàrà márùn-ún àti ẹja méjì lọ níhìn-ín.”
Lekin muhlislar: — Bizdǝ bǝx nan bilǝn ikki danǝ beliⱪtin baxⱪa ⱨeq nǝrsǝ yoⱪ, — deyixti.
18 Ó wí pé, “Ẹ mú wọn wá fún mi níhìn-ín yìí.”
U: — Ularni manga elip kelinglar, dedi.
19 Lẹ́yìn náà, ó wí fún àwọn ènìyàn kí wọ́n jókòó lórí koríko. Lẹ́yìn náà, ó mú ìṣù àkàrà márùn-ún àti ẹja méjì. Ó gbé ojú rẹ̀ sí ọ̀run. Ó béèrè ìbùkún Ọlọ́run lórí oúnjẹ náà, Ó sì bù ú, ó sì fi àkàrà náà fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn láti pín in fún àwọn ènìyàn.
U halayiⱪni qɵplükning üstidǝ olturuxⱪa buyruƣandin keyin, bǝx nan bilǝn ikki beliⱪni ⱪoliƣa elip, asmanƣa ⱪarap [Hudaƣa] tǝxǝkkür eytti. Andin nanlarni oxtup muhlisliriƣa bǝrdi, muhlisliri halayiⱪⱪa ülǝxtürüp bǝrdi.
20 Gbogbo wọn sì jẹ àjẹyó. Lẹ́yìn náà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn kó àjẹkù jọ, ó kún agbọ̀n méjìlá.
Ⱨǝmmǝylǝn yǝp toyundi. [Muhlislar] exip ⱪalƣan parqilarni liⱪ on ikki sewǝtkǝ teriwaldi.
21 Iye àwọn ènìyàn ni ọjọ́ náà jẹ́ ẹgbẹ̀rún márùn-ún ọkùnrin, láìka àwọn obìnrin àti àwọn ọmọdé.
Ozuⱪlanƣanlarning sani ayallar wǝ balilardin baxⱪa tǝhminǝn bǝx ming kixi idi.
22 Lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ lẹ́yìn èyí, Jesu wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ kí wọ́n bọ sínú ọkọ̀ wọn, àti kí wọ́n máa kọjá lọ ṣáájú rẹ̀ sí òdìkejì. Òun náà dúró lẹ́yìn láti tú àwọn ènìyàn ká lọ sí ilé wọn.
Arⱪidila, u muhlisliriƣa: Ɵzüm bu halayiⱪni yolƣa seliwetimǝn, angƣuqǝ silǝr kemigǝ olturup, dengizning ⱪarxi ⱪirƣiⱪiƣa ɵtüp turunglar, dǝp buyrudi.
23 Lẹ́yìn tí ó tú ìjọ ènìyàn ká tán, ó gun orí òkè lọ fúnra rẹ̀ láti lọ gba àdúrà. Nígbà tí ilẹ̀ ṣú, òun wà nìkan níbẹ̀,
Halayiⱪni yolƣa seliwǝtkǝndin keyin, u dua ⱪilix üqün ɵzi hilwǝt taƣⱪa qiⱪti. Kǝq kirgǝndimu u yǝrdǝ yalƣuz ⱪaldi.
24 ní àkókò yìí ọkọ̀ ojú omi náà ti rin jìnnà sí etí bèbè Òkun, tí ìjì omi ń tì í síwá sẹ́yìn, nítorí ìjì ṣe ọwọ́ òdì sí wọn.
Bu qaƣda, kemǝ ⱪirƣaⱪtin heli kɵp qaⱪirim yürgǝnidi, lekin xamal ⱪarxi yɵnlixitin qiⱪiwatⱪaqⱪa, kemǝ dolⱪunlar iqidǝ qayⱪilip turatti.
25 Ní déédé ago mẹ́rin òwúrọ̀, Jesu tọ̀ wọ́n wá, ó ń rìn lórí omi.
Keqǝ tɵtinqǝ jesǝk waⱪtida, u dengizning üstidǝ mengip, muhlisliri tǝrǝpkǝ kǝldi.
26 Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rí i tí ó ń rìn lójú omi, ẹ̀rù ba wọn gidigidi, wọ́n rò pé “iwin ni,” wọ́n kígbe tìbẹ̀rù tìbẹ̀rù.
Muhlislar uning dengizning üstidǝ mengip keliwatⱪanliⱪini kɵrüp, alaⱪzadǝ bolup: — Alwasti ikǝn! — dǝp ⱪorⱪup quⱪan selixti.
27 Lójúkan náà, Jesu wí fún wọn pé, “Ẹ mú ọkàn le! Èmi ni ẹ má ṣe bẹ̀rù.”
Lekin Əysa dǝrⱨal ularƣa: — Yürǝklik bolunglar, bu mǝn, ⱪorⱪmanglar! — dedi.
28 Peteru sì ké sí i pé, “Olúwa, bí ó bá jẹ́ pé ìwọ ni nítòótọ́, sọ pé kí n tọ̀ ọ́ wà lórí omi.”
Petrus buningƣa jawabǝn: — I Rǝb, bu sǝn bolsang, su üstidǝ mengip yeningƣa beriximƣa ǝmr ⱪilƣaysǝn, — dedi.
29 Jesu dá a lóhùn pé, “Ó dára, máa bọ̀ wá.” Nígbà náà ni Peteru sọ̀kalẹ̀ láti inú ọkọ̀. Ó ń rìn lórí omi lọ sí ìhà ọ̀dọ̀ Jesu.
Kǝl, — dedi u. Petrus kemidin qüxüp, su üstidǝ mengip, Əysaƣa ⱪarap ketiwatatti;
30 Nígbà tí ó rí afẹ́fẹ́ líle, ẹ̀rù bà á, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí í rì. Ó kígbe lóhùn rara pé, “Gbà mí, Olúwa.”
lekin boranning ⱪattiⱪ qiⱪiwatⱪanliⱪini kɵrüp ⱪorⱪup, suƣa qɵküxkǝ baxlidi: — Rǝb, meni ⱪutⱪuzuwalƣaysǝn! — dǝp warⱪiridi.
31 Lójúkan náà, Jesu na ọwọ́ rẹ̀, ó dìímú, ó sì gbà á. Ó sì wí fún un pé, “Èéṣe tí ìwọ fi ṣiyèméjì ìwọ onígbàgbọ́ kékeré?”
Əysa dǝrⱨal ⱪolini uzitip, uni tutuwaldi wǝ uningƣa: — Əy ixǝnqi ajiz bǝndǝ, nemixⱪa guman ⱪilding? — dedi.
32 Àti pé, nígbà ti wọ́n sì gòkè sínú ọkọ̀, ìjì náà sì dúró jẹ́ẹ́.
Ular kemigǝ qiⱪⱪanda, xamal tohtidi.
33 Nígbà náà ni àwọn to wà nínú ọkọ̀ náà foríbalẹ̀ fún un wọ́n wí pé, “Nítòótọ́ Ọmọ Ọlọ́run ni ìwọ í ṣe.”
Kemidǝ olturƣanlar uning aldiƣa kelip sǝjdǝ ⱪilip: — Bǝrⱨǝⱪ, sǝn Hudaning Oƣli ikǝnsǝn, — deyixti.
34 Nígbà tí wọn rékọjá sí apá kejì wọ́n gúnlẹ̀ sí Genesareti.
Ular dengizning ⱪarxi tǝripigǝ ɵtkǝndǝ, Ginnisarǝt yurtida [ⱪuruⱪluⱪⱪa] qiⱪti.
35 Nígbà tiwọn mọ̀ pé Jesu ni, wọn sì ránṣẹ́ sí gbogbo ìlú náà yíká. Wọ́n sì gbé gbogbo àwọn aláìsàn tọ̀ ọ́ wá.
U yǝrdiki adǝmlǝr uni tonup ⱪelip, ǝtraptiki barliⱪ jaylarƣa hǝwǝr ǝwǝtti; xuning bilǝn kixilǝr barliⱪ bimarlarni uning aldiƣa elip kǝldi;
36 Àwọn aláìsàn bẹ̀ ẹ́ pé kí ó gba àwọn láyè láti fi ọwọ́ kan ìṣẹ́tí aṣọ rẹ̀, gbogbo àwọn tí ó ṣe bẹ́ẹ̀ sì rí ìwòsàn.
ular uningdin bimarlarning ⱨeqbolmiƣanda uning tonining pexigǝ bolsimu ⱪolini tǝgküzüwelixiƣa yol ⱪoyuxini ɵtündi. Uningƣa ⱪolini tǝgküzgǝnlǝrning ⱨǝmmisi sǝllimaza saⱪaydi.

< Matthew 14 >