< Matthew 12 >
1 Ní àkókò náà ni Jesu ń la àárín oko ọkà kan lọ ní ọjọ́ ìsinmi, ebi sì ń pa àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀. Wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí i ya orí ọkà, wọ́n sì ń jẹ ẹ́.
Ki fiya cuwa, Yecu kwen yam ki kakuk fobka mor tankini. Bibei tomange ceu nuwa wura ti, la ci kwer dor cangero ti citi cai.
2 Nígbà tí àwọn Farisi rí èyí. Wọ́n wí fún pé, “Wò ó! Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ ń ṣe ohun tí kò bá òfin mu ní ọjọ́ ìsinmi.”
La fariciyawa to nyori, cin yii Yecu, “To be bei tomange mweu diker ci matiye werfundo ciyabo a mani ki kakuk fobka.
3 Jesu dáhùn pé, “Ẹ̀yin kò ha ka ohun tí Dafidi ṣe nígbà tí ebi ń pa á àti àwọn tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ̀.
La Yecu yi ci ki ka karanta bo diker Dauda mane kange nobo loce ki fiya cuwo ci nuwa wura tiya?
4 Ó wọ inú ilé Ọlọ́run, òun àti àwọn ènìyàn rẹ̀ jẹ àkàrà tí a yà sọ́tọ̀, èyí tí kò yẹ fún wọn láti jẹ, bí kò ṣe fún àwọn àlùfáà nìkan.
Con doken bi kur kwamar, con ca cari wiye wo werundo ciya cinenbo kange nobo cineneu, ciyam kin nob wabeb koni.
5 Tàbí ẹ̀yin kò ti kà á nínú òfin pé ní ọjọ́ ìsinmi, àwọn àlùfáà tí ó wà ní tẹmpili ń ba ọjọ́ ìsinmi jẹ́ tí wọ́n sì wà láìjẹ̀bi.
Ka mor werfuna, ki kakuk fobka, nob wabbe kwama mor kikur kwamare ma dike werfundo ciyanbe, nyori, ci tacibe ki kero bwia?
6 Ṣùgbọ́n mo wí fún yín, ẹni tí ó pọ̀ ju tẹmpili lọ wà níhìn-ín.
Min yi kom niwo la bikur kwamareu wo fo.
7 Bí ó bá jẹ́ pé ẹ mọ ìtumọ̀ ọ̀rọ̀ yìí, ‘Àánú ni èmi ń fẹ́ kì í ṣe ẹbọ,’ ẹ̀yin kì bá tí dá aláìlẹ́ṣẹ̀ lẹ́bi.
Na ki ka nyimom ye wuro nuntiyeri, 'miki cwi cire duwe kebo twika nuwange ko wucake, no kom ki warbo ker dor niwo man ki bwiran kereu.
8 Nítorí pé Ọmọ Ènìyàn jẹ́ Olúwa ọjọ́ ìsinmi.”
Bibwe nifire co teluwe kakuk fobka ke.
9 Nígbà tí Jesu kúrò níbẹ̀ ó lọ sí Sinagọgu wọn,
La Yecu dubom bikole cuwo, doken bi kur wabbero Urcalimau.
10 ọkùnrin kan tí ọwọ́ rẹ̀ kan rọ wà níbẹ̀. Wọ́n ń wá ọ̀nà láti fi ẹ̀sùn kan Jesu, wọ́n béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Ǹjẹ́ ó tọ́ láti mú ènìyàn láradá ní ọjọ́ ìsinmi?”
wori, nii kange kanko nom nowe wini. Fariciyawa me Yecu dong dongka a twa ni ki kakuk fobka ka? o na cin taco ki ker bwiranke.
11 Ó dá wọn lóhùn pé, “Bí ó bá jẹ́ wí pé bí ẹnikẹ́ni nínú yín bá ní àgùntàn kan ṣoṣo, tí ó sì bọ́ sínú kòtò ní ọjọ́ ìsinmi, ǹjẹ́ kì yóò dìímú, kí ó sì fà á jáde.
Yecu yi ci we fo more kume no kwame ce yarken bouk ki kakuk fobka ri mani a tau ti cokumme?
12 Ǹjẹ́ mélòó mélòó ní ènìyàn ní iye lórí ju àgùntàn kan lọ! Nítorí náà ó yẹ láti ṣe rere ní ọjọ́ ìsinmi.”
Na wine la kece kwame kaka nifir? nyori werfundo ciya a ma diker ken ki kakuk fobka.
13 Nígbà náà, ó sì wí fún ọkùnrin náà pé, “Na ọwọ́ rẹ,” bí òun sì ti nà án, ọwọ́ rẹ̀ sì bọ̀ sí ipò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọwọ́ èkejì.
La Yecu yi niwo, “Taruu kangeko, la con taruu kang ceko, la kango yilaken kwamer na wineu.
14 Síbẹ̀ àwọn Farisi jáde lọ pe ìpàdé láti dìtẹ̀ mú un àti bí wọn yóò ṣe pa Jesu.
La fariciyawa erken kale cin mwer kangi dor Yecu. ciki do nure ciya twalum Yecu tiye.
15 Nígbà tí Jesu sì mọ̀, ó yẹra kúrò níbẹ̀. Ọ̀pọ̀ ìjọ ènìyàn sì ń tọ̀ ọ́ lẹ́yìn, ó sì mú gbogbo àwọn aláìsàn láradá.
Yecu to nyori co ci dubom bi kole cuwe. nuwe. nubo ducce bwanteng ce, con twam ci.
16 Ṣùgbọ́n ó kìlọ̀ fún wọn pé kí wọ́n kí ó má ṣe fi òun hàn.
Con yi ciki nyial ciya yire nii.
17 Èyí jẹ́ ìmúṣẹ àsọtẹ́lẹ̀ èyí tí wòlíì Isaiah sọ nípa rẹ̀ pé,
wo na ci dim dike ci tok nyii nii wabe kwabe Icaya, tokti ki.
18 “Ẹ wo ìránṣẹ́ mi ẹni tí mo yàn. Àyànfẹ́ mi ni ẹni tí inú mi dùn sí gidigidi; èmi yóò fi ẹ̀mí mi fún un. Òun yóò sì ṣe ìdájọ́ àwọn kèfèrí.
Too Yii tomange me wo ma cok ceu, ma bilankange ceu, Man ne co yuwa tangbek miko naci yii nubo wo kebo Yahudawa.
19 Òun kì yóò jà, bẹ́ẹ̀ ni kì yóò kígbe; ẹnikẹ́ni kì yóò gbọ́ ohùn rẹ ní ìgboro.
Mani ca kwobkan ker ti, Mani ca ci wiye ti ki diir, mani a nuwa dircer ti nure.
20 Koríko odò títẹ̀ kan ni òun kì yóò fọ́, àti òwú-fìtílà tí ń jó tan an lọ lòun kì yóò fẹ́ pa. Títí yóò fi mú ìdájọ́ dé ìṣẹ́gun.
Ma ca kyan dike fwinongum ti, ma ca dom kra ko dadom bwiyakau, can ya ki warka turani.
21 Ní orúkọ rẹ̀ ni gbogbo kèfèrí yóò fi ìrètí wọn sí.”
Mor dene ce nubo kumtacile an fiya yim yo neri.
22 Nígbà náà ni wọ́n mú ọkùnrin kan tó ni ẹ̀mí èṣù tọ̀ ọ́ wá, tí ó afọ́jú, tí ó tún ya odi. Jesu sì mú un láradá kí ó le sọ̀rọ̀, ó sì ríran.
Nyori cin bou ki nii kange, fukma, mani nuwa tuu, wiki ninga fiye Yecu wiye. Con twam cona wo Nyori nii cuwo tok ker, ti toi tak.
23 Ẹnu sì ya gbogbo àwọn ènìyàn. Wọ́n wí pé, “Èyí ha lè jẹ́ Ọmọ Dafidi bí?”
Nubo wmerkangum gwamme nuwa nyimangka la me, wo co bibwe Dauda ka?
24 Ṣùgbọ́n nígbà tí àwọn Farisi gbọ́ èyí, wọ́n wí pé, “Nípa Beelsebulu nìkan, tí í ṣe ọba ẹ̀mí èṣù ni ọkùnrin yìí fi lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde.”
La fariciyaa nuwa diker nyimankako Yecu maneri cin yi ki, “Nii wo ki cok ninga kin bahalzabu liya kelkelebe.
25 Jesu tí ó mọ èrò wọn, ó wí fún wọn pé, “Ìjọbakíjọba tí ó bá yapa sí ara rẹ̀ yóò parun, ìlúkílùú tàbí ilékílé tí ó bá yapa sí ara rẹ̀ kì yóò dúró.
La Yecu nyimom dike ci kwati ner cere, yi ci ki, Liyar do wo yalkangum me ri, mani a ti-ti cinar lor tikangum yobe mani a titi, kako luwe fwemme ri, an wurom.
26 Bí èṣù bá sì ń lé èṣù jáde, a jẹ́ wí pé, ó ń yapa sí ara rẹ̀. Ìjọba rẹ yóò ha ṣe le dúró?
No bwekelkele cok bwekele ri ki maa kiiye ki dor cero. La a mangyi na liyar do wo ti?
27 Àti pé, bi èmi bá ń lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde nípa Beelsebulu, nípa ta ni àwọn ènìyàn yín fi ń lé wọn jáde? Nítorí náà ni wọn yóò ṣe má ṣe ìdájọ́ yín.
No miki cok ninga kin Ba'alzabu ri, bi bei kimeu ki cok ki ye? nyori ci ciya yila warka kimek tiye.
28 Ṣùgbọ́n bí ó bá jẹ́ pé nípa Ẹ̀mí Ọlọ́run ni èmi fi ń lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde, a jẹ́ pé ìjọba Ọlọ́run ti dé bá yín.
No miki cok ninga ki yuwa tangbe kwama wucake ri, nangi liyar kwamaro bou kimen.
29 “Tàbí, báwo ni ẹnikẹ́ni ṣe lè wọ ilé alágbára lọ kí ó sì kó ẹrù rẹ̀, bí kò ṣe pé ó kọ́kọ́ di alágbára náà? Nígbà náà ni ó tó lè kó ẹrù rẹ̀ lọ.
A man nyii nii doken lo nii bikwanne na ku kwi, co co bwam cobo ri? na nimre kange me ri ki ma kiiye kange mo, takeu, niwo mwerbo kange me ri, ki watangken.
30 “Ẹni tí kò bá wà pẹ̀lú mi, òun lòdì sí mi, ẹni tí kò bá mi kójọpọ̀ ń fọ́nká.
31 Nítorí èyí, mo wí fún yín, gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ àti ọ̀rọ̀-òdì ni a yóò dárí rẹ̀ jí ènìyàn, ṣùgbọ́n ìsọ̀rọ̀-òdì sí Ẹ̀mí Mímọ́ kò ní ìdáríjì.
Na wori mi yi kom ti, “bwirangke kange dilanka gwam an curanwi. La dilanka yuwatangbeko wucake mani a curang ti wi.
32 Ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ̀rọ̀-òdì sí Ọmọ Ènìyàn, a ó dáríjì í, ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá sọ ọ̀rọ̀-òdì sí Ẹ̀mí Mímọ́, a kì yóò dáríjì í, ìbá à ṣe ní ayé yìí tàbí ní ayé tí ń bọ̀. (aiōn )
Ni wuro tok dikro bwir dor bibwenifireu a cutang wi wo tok kero bwir dor yuwa tangbe wucakeu a curang cinen ti wi fo kale wo kange wo boutiye. (aiōn )
33 “E sọ igi di rere, èso rẹ̀ a sì di rere tàbí kí ẹ sọ igi di búburú, èso rẹ a sì di búburú, nítorí nípa èso igi ni a ó fi mọ̀ igi.
Ywel tiyo a yori, bi tuti ce an yori kaka ywel tiyo a bwira bi tuti ce a bwira.
34 Ẹ̀yin ọmọ paramọ́lẹ̀, báwo ni ẹ̀yin tí ẹ jẹ búburú ṣe lè sọ̀rọ̀ rere? Ọkàn ènìyàn ni ó ń darí irú ọ̀rọ̀ tí ó lè jáde lẹ́nu rẹ̀.
Kom bi bei na cuwe, kom nubobwir a ma nyii ka tok dikero keng tiye? Mor dikero ducce nereu co nyiiyo toktiye.
35 Ẹni rere láti inú yàrá ìṣúra rere ọkàn rẹ̀ ní mú ohun rere jáde wá, àti ẹni búburú láti inú ìṣúra búburú ni; mu ohun búburú jáde wá.
Ni ken ki coku dikero kendo ner cereu, nii bwir ki cok dikero bwir ko ner cereu.
36 Ṣùgbọ́n, mo sọ èyí fún yín, ẹ̀yin yóò jíyìn gbogbo ìsọkúsọ yín ní ọjọ́ ìdájọ́.
Mi yikom ti ki kakuk warka nubo an ne warke dor dikero bwir ko ci toke.
37 Nítorí nípa ọ̀rọ̀ ẹnu yín ni a fi dá yin láre, nípa ọ̀rọ̀ ẹnu yín sì ni a ó fi dá yin lẹ́bi.”
Ki kero nyii mweu an coknen ki kero nyii mweu an kuwa nen.
38 Nígbà náà ni, díẹ̀ nínú àwọn Farisi àti àwọn olùkọ́ òfin wí fún pé “Olùkọ́, àwa fẹ́ rí iṣẹ́ àmì kan lọ́dọ̀ rẹ̀”.
Nyori kangem nob mulang kar kange Fariciyawa ciya Yecu nin ki “nii merangka, nyi cwiti nayi to yirom muneng”
39 Ó sì dá wọn lóhùn wí pé, “Ìran búburú àti ìran panṣágà ń béèrè àmì; ṣùgbọ́n kò sí àmì tí a ó fi fún un, bí kò ṣe àmì Jona wòlíì.
la Yecu yi ci ki, “Kom nubo bwir, kom nob burotumbo kaldo weu, ko do yirom ti mani k fiya ti no kebo ka wo Yunana nii tomangeu ce ri.
40 Bí Jona ti gbé inú ẹja ńlá fún ọ̀sán mẹ́ta àti òru mẹ́ta, bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni ẹ̀mí Ọmọ Ènìyàn yóò gbé ní inú ilẹ̀ fún ọ̀sán mẹ́ta àti òru mẹ́ta.
Nyori Yunana da kuma taar, kakuko taar mor fwer jingi dur, na cuwo bi bwe nii an daa kume taar, kakuko taar mor bitine.
41 Àwọn ará Ninefe yóò dìde pẹ̀lú ìran yìí ní ọjọ́ ìdájọ́. Wọn yóò sì dá a lẹ́bi. Nítorí pé wọ́n ronúpìwàdà nípa ìwàásù Jona. Ṣùgbọ́n báyìí ẹni tí ó pọ̀jù Jona wà níhìn-ín yìí.
Nubo niniba a kweni an tii kange nubo kaldo we ki kakuk wara, ci an kuwa ci wori cin yiloten ki fulen kerek Yunana ro, la to nii kange wo la Yunana wo.
42 Ọbabìnrin gúúsù yóò sì dìde ní ọjọ́ ìdájọ́ sí ìran yìí yóò sì dá a lẹ́bi; nítorí tí ó wá láti ilẹ̀ ìkangun ayé láti gbọ́ ọ̀rọ̀ ọgbọ́n láti ẹnu Solomoni. Ṣùgbọ́n báyìí ẹni tí ó pọ̀jù Solomoni ń bẹ níhìn-ín yìí.
Liya bangeu an kweni kane nobo kaldo, an kuwaa ci. ca bou cile kale wo na ci nuwa yilen Culemanu ro, la to nii kange wo laa Culemanuweu wo.
43 “Nígbà tí ẹ̀mí búburú kan bá jáde lára ènìyàn, a máa rìn ní ibi gbígbẹ́, a máa wá ibi ìsinmi, kò sì ní rí i.
No yuwa tangbe ko bwir cerum nii nen di ki yaya fiyeni wo mwem mani yeu na ci fiya fobke, mani ca fiyati.
44 Nígbà náà ni ẹ̀mí náà yóò wí pé, ‘Èmi yóò padà sí ara ọkùnrin tí èmí ti wá.’ Bí ó bá sì padà, tí ó sì bá ọkàn ọkùnrin náà ni òfìfo, a gbà á mọ́, a sì ṣe é ní ọ̀ṣọ́.
La yi ki man yilaken lomiyo ma cerueweu. No ci yilaken di, can fiya luwa, nyinangum Yulangum yora.
45 Nígbà náà ni yóò lọ, yóò sì mú ẹ̀mí méje mìíràn pẹ̀lú ara rẹ̀, tí ó burú ju òun fúnra rẹ̀ lọ. Gbogbo wọn yóò sì wá sí inú rẹ̀, wọn yóò máa gbé ibẹ̀. Ìgbẹ̀yìn ọkùnrin náà a sì burú ju ìṣáájú rẹ̀ lọ. Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni yóò rí fún ìran búburú yìí pẹ̀lú.”
La con tuten kange kebceb niber wo bwira la ceu bou ciko na ci yi nyo, la cwile nii wo an bwira la wo fiyau, a yila nyo kange kaldo bwir ko wuro.
46 Nígbà tí ó ń sọ̀rọ̀ wọ̀nyí fún àwọn ènìyàn, wò ó, ìyá rẹ̀ àti àwọn arákùnrin rẹ̀ dúró lóde, wọ́n fẹ́ bá a sọ̀rọ̀.
La Yecu dibo tokka kereko nubo mwerum cineneu ri, nece kange yitobcebo bou tim kale, cwiti na cin to co.
47 Nígbà náà ni ẹnìkan wí fún un pé, “Ìyá rẹ àti àwọn arákùnrin rẹ ń dúró dè ọ́ lóde wọ́n ń fẹ́ bá ọ sọ̀rọ̀.”
Kange yico, “To nemwe kange yitub mweb tirangum kale, cwiti na ci tok ker kange mo.
48 Ó sì fún ni èsì pé, “Ta ni ìyá mi? Ta ni àwọn arákùnrin mi?”
Yecu yi co nii wo yico kereu, we nemi, we yitub mibo?
49 Ó nawọ́ sí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó wí pé, “Wò ó, ìyá mi àti àwọn arákùnrin mi ni wọ̀nyí.”
La con taar kang ceko fiye be bei tomange ce nineu yico, “To” buro co nemi kange yitob mibo.
50 Nítorí náà, “Ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe ìfẹ́ Baba mi tí ń bẹ ní ọ̀run, ni arákùnrin mi àti arábìnrin mi àti ìyá mi.”
No nii wo ma diker temi wo di kwama cwitiye ri, nii cuwo co nemi co nemi kange yitob mib.