< Matthew 11 >
1 Lẹ́yìn ìgbà tí Jesu sì ti parí ọ̀rọ̀ tí ó ń sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ méjìlá, ó ti ibẹ̀ rékọjá láti máa kọ́ni àti láti máa wàásù ní àwọn ìlú Galili gbogbo.
ⲁ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲥϣⲱⲡⲓ ⳿ⲉⲧⲁ Ⲓⲏ̅ⲥ̅ ⲕⲏⲛ ⲉϥⲟⲩⲁϩⲥⲁϩⲛⲓ ⳿ⲉⲧⲟⲧϥ ⳿ⲙⲡⲉϥ ⲓ̅ⲃ̅ ⳿ⲙⲙⲁⲑⲏⲧⲏⲥ ⲁϥⲟⲩ⳿ⲱⲧⲉⲃ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲙⲙⲁⲩ ⲉⲑⲣⲉϥϯ⳿ⲥⲃⲱ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲧⲉϥϩⲓⲱⲓϣ ⳿ⲛ⳿ϩⲣⲏⲓ ϧⲉⲛ ⲛⲟⲩⲃⲁⲕⲓ.
2 Nígbà tí Johanu gbọ́ ohun tí Kristi ṣe nínú ẹ̀wọ̀n, ó rán àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀
ⲃ̅Ⲓⲱⲁⲛⲛⲏⲥ ⲇⲉ ⳿ⲉⲧⲁϥⲥⲱⲧⲉⲙ ⲉϥⲭⲏ ϧⲉⲛ ⲡⲓ⳿ϣⲧⲉⲕⲟ ⲉⲑⲃⲉ ⲛⲓ⳿ϩⲃⲏⲟⲩⲓ ⳿ⲛⲧⲉ Ⲡⲭ̅ⲥ̅ ⲁϥⲟⲩⲱⲣⲡ ⳿ⲛⲃ̅ ⳿ⲉⲃⲟⲗϧⲉⲛ ⲛⲉϥⲙⲁⲑⲏⲧⲏⲥ.
3 láti béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Ṣe ìwọ ni ẹni tó ń bọ̀ wá tàbí kí a máa retí ẹlòmíràn?”
ⲅ̅ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲁϥ ϫⲉ ⳿ⲛⲑⲟⲕ ⲡⲉ ⲫⲏⲉⲑⲛⲏⲟⲩ ϣⲁⲛ ⳿ⲛⲧⲉⲛϫⲟⲩϣⲧ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲁϫⲱϥ ⳿ⲛⲕⲉⲟⲩⲁⲓ.
4 Jesu dáhùn ó wí pé, “Ẹ padà lọ, ẹ sì sọ fún Johanu ohun tí ẹ̀yin gbọ́, àti èyí tí ẹ̀yin rí.
ⲇ̅ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉⲧⲁϥ⳿ⲉⲣⲟⲩ⳿ⲱ ⳿ⲛϫⲉ Ⲓⲏ̅ⲥ̅ ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲱⲟⲩ ϫⲉ ⲙⲁϣⲉⲛⲱⲧⲉⲛ ⲙⲁⲧⲁⲙⲉ Ⲓⲱⲁⲛⲛⲏⲥ ⳿ⲉⲛⲏ⳿ⲉⲧⲉⲧⲉⲛⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲣⲱⲟⲩ ⲛⲉⲙ ⲛⲏ⳿ⲉⲧⲉⲧⲉⲛⲥⲱⲧⲉⲙ ⳿ⲉⲣⲱⲟⲩ.
5 Àwọn afọ́jú ń ríran, àwọn amúnkùn ún rìn, a ń wẹ àwọn adẹ́tẹ̀ mọ́ kúrò nínú ẹ̀tẹ̀ wọn, àwọn adití ń gbọ́rọ̀, a ń jí àwọn òkú dìde, a sì ń wàásù ìyìnrere fún àwọn òtòṣì.
ⲉ̅ϫⲉ ⲛⲓⲃⲉⲗⲗⲉⲩ ⲥⲉⲛⲁⲩ ⳿ⲙⲃⲟⲗ ⲛⲓϭⲁⲗⲉⲩ ⲥⲉⲙⲟϣⲓ ⲛⲓⲕⲁⲕⲥⲉϩⲧ ⲥⲉⲧⲟⲩⲃⲏⲟⲩⲧ ⲛⲓⲕⲟⲩⲣ ⲥⲉⲥⲱⲧⲉⲙ ⲛⲓⲣⲉϥⲙⲱⲟⲩⲧ ⲥⲉⲧⲱⲟⲩⲛⲟⲩ ⲛⲓϩⲏⲕⲓ ⲥⲉϩⲓϣⲉⲛⲛⲟⲩϥⲓ ⲛⲱⲟⲩ.
6 Alábùkún fún ni ẹni tí kò rí ohun ìkọ̀sẹ̀ nípa mi.”
ⲋ̅ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲱⲟⲩⲛⲓⲁⲧϥ ⳿ⲙⲫⲏ⳿ⲉⲧⲉ⳿ⲛ⳿ϥⲛⲁⲉⲣ⳿ⲥⲕⲁⲛⲇⲁⲗⲓⲍⲉⲥⲑⲉ ⲁⲛ ⳿ⲛϧⲏⲧ.
7 Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Johanu ti lọ tán, Jesu bẹ̀rẹ̀ sí í sọ fún ọ̀pọ̀ ènìyàn nípa ti Johanu: “Kí ni ẹ̀yin jáde lọ wò ní aginjù? Ewéko tí afẹ́fẹ́ ń mi?
ⲍ̅ⲛⲁⲓ ⲇⲉ ⲉⲩⲛⲁϣⲉⲛⲱⲟⲩ ⲁϥⲉⲣϩⲏⲧⲥ ⳿ⲛϫⲉ Ⲓⲏ̅ⲥ̅ ⳿ⲛϫⲟⲥ ⳿ⲛⲛⲓⲙⲏϣ ⲉⲑⲃⲉ Ⲓⲱⲁⲛⲛⲏⲥ ϫⲉ ⳿ⲉⲧⲁⲣⲉⲧⲉⲛ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲉ⳿ⲡϣⲁϥⲉ ⳿ⲉⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲟⲩ ⳿ⲉⲟⲩⲕⲁϣ ⳿ⲉⲣⲉ ⲡⲓⲑⲏⲟⲩ ⲕⲓⲙ ⳿ⲉⲣⲟϥ.
8 Bí kò bá ṣe bẹ́ẹ̀, kí ni ẹ̀yin lọ òde lọ í wò? Ọkùnrin tí a wọ̀ ni aṣọ dáradára? Rárá àwọn ti ó wọ aṣọ dáradára wà ní ààfin ọba.
ⲏ̅ⲁⲗⲗⲁ ⳿ⲉⲧⲁⲣⲉⲧⲉⲛ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲉⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲟⲩ ⳿ⲉⲟⲩⲣⲱⲙⲓ ⲉϥⲭⲏ ϧⲉⲛ ϩⲁⲛϭⲓ⳿ϩⲃⲱⲥ ⳿ⲛϫⲁⲛⲏ ϩⲏⲡⲡⲉ ⲓⲥ ⲛⲁ ⲛⲓ⳿ϩⲃⲱⲥ ⳿ⲛϫⲁⲛⲏ ⲥⲉⲭⲏ ϧⲉⲛ ⲛⲉⲛⲏⲟⲩ ⳿ⲛⲛⲓⲟⲩⲣⲱⲟⲩ.
9 Àní kí ní ẹ jáde láti lọ wò? Wòlíì? Bẹ́ẹ̀ ni, mo wí fún yín, ó sì ju wòlíì lọ.”
ⲑ̅ⲁⲗⲗⲁ ⳿ⲉⲧⲁⲣⲉⲧⲉⲛ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲉⲑⲃⲉ ⲟⲩ ⳿ⲉⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲟⲩ⳿ⲡⲣⲟⲫⲏⲧⲏⲥ ⳿ⲁϩⲁ ϯϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⲛⲱⲧⲉⲛ ϫⲉ ⲟⲩϩⲟⲩ⳿ⲟ ⳿ⲉⲟⲩ⳿ⲡⲣⲟⲫⲏⲧⲏⲥ.
10 Èyí ni ẹni tí a ti kọ̀wé rẹ̀ pé: “‘Èmi yóò rán ìránṣẹ́ mi síwájú rẹ, ẹni tí yóò tún ọ̀nà rẹ ṣe níwájú rẹ.’
ⲓ̅ⲫⲁⲓ ⲅⲁⲣ ⲫⲏⲉⲧ⳿ⲥϧⲏⲟⲩⲧ ⲉⲑⲃⲏⲧϥ ϫⲉ ϩⲏⲡⲡⲉ ϯⲛⲁⲟⲩⲱⲣⲡ ⳿ⲙⲡⲁⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ϧⲁϫⲱⲕ ⲟⲩⲟϩ ⲉϥ⳿ⲉⲥⲟⲃϯ ⳿ⲙⲡⲉⲕⲙⲱⲓⲧ ⳿ⲙⲡⲉⲕ⳿ⲙⲑⲟ.
11 Lóòótọ́ ni mó wí fún yín, nínú àwọn tí a bí nínú obìnrin, kò sí ẹni tí ó tí í dìde tí ó ga ju Johanu onítẹ̀bọmi lọ, síbẹ̀ ẹni tí ó kéré jù ní ìjọba ọ̀run ni ó pọ̀jù ú lọ.
ⲓ̅ⲁ̅⳿ⲁⲙⲏⲛ ϯϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⲛⲱⲧⲉⲛ ϫⲉ ⳿ⲙⲡⲉ ⲟⲩⲟⲛ ⲧⲱⲛϥ ϧⲉⲛ ⲛⲓⲙⲓⲥⲓ ⳿ⲛⲧⲉ ⲛⲓϩⲓ⳿ⲟⲙⲓ ⳿ⲉⲛⲁⲁϥ ⳿ⲉⲒⲱⲁⲛⲛⲏⲥ ⲡⲓⲣⲉϥϯⲱⲙⲥ ⲡⲓⲕⲟⲩϫⲓ ⲇⲉ ⳿ⲉⲣⲟϥ ϧⲉⲛ ϯⲙⲉⲧⲟⲩⲣⲟ ⳿ⲛⲧⲉ ⲛⲓⲫⲏⲟⲩ⳿ⲓ ⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⲡⲉ.
12 Láti ìgbà ọjọ́ Johanu onítẹ̀bọmi títí di àkókò yìí ni ìjọba ọ̀run ti di à fi agbára wọ̀, àwọn alágbára ló ń fi ipá gbà á.
ⲓ̅ⲃ̅ⲓⲥϫⲉⲛ ⲛⲓ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⲇⲉ ⳿ⲛⲧⲉ Ⲓⲱⲁⲛⲛⲏⲥ ⲡⲓⲣⲉϥϯⲱⲙⲥ ϣⲁ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉϯⲛⲟⲩ ϯⲙⲉⲧⲟⲩⲣⲟ ⳿ⲛⲧⲉ ⲛⲓⲫⲏⲟⲩ⳿ⲓ ⲥⲉϭⲓ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⳿ⲛϫⲟⲛⲥ ⲟⲩⲟϩ ϩⲁⲛⲣⲉϥϭⲓ ⳿ⲛϫⲟⲛⲥ ⲉⲧϩⲱⲗⲉⲙ ⳿ⲙⲙⲟⲥ.
13 Nítorí náà gbogbo òfin àti wòlíì ni ó sọtẹ́lẹ̀ kí Johanu kí ó tó dé.
ⲓ̅ⲅ̅ⲛⲓⲡⲣⲟⲫⲏⲧⲏⲥ ⲅⲁⲣ ⲧⲏⲣⲟⲩ ⲛⲉⲙ ⲡⲓⲛⲟⲙⲟⲥ ⲁⲩⲉⲣ⳿ⲡⲣⲟⲫⲏⲧⲉⲩⲓⲛ ϣⲁ Ⲓⲱⲁⲛⲛⲏⲥ.
14 Bí ẹ̀yin yóò bá gbà á, èyí ni Elijah tó ń bọ̀ wá.
ⲓ̅ⲇ̅ⲟⲩⲟϩ ⲓⲥϫⲉ ⲧⲉⲧⲉⲛⲟⲩⲱϣ ⳿ⲉϣⲟⲡϥ ⳿ⲛⲑⲟϥ ⲡⲉ Ⲏ̇ⲗⲓⲁⲥ ⲉⲑⲛⲏⲟⲩ.
15 Ẹni tí ó bá ní etí, kí ó gbọ́.
ⲓ̅ⲉ̅ⲫⲏ⳿ⲉⲧⲉ ⲟⲩⲟⲛ ⲙⲁϣϫ ⳿ⲙⲙⲟϥ ⳿ⲉⲥⲱⲧⲉⲙ ⲙⲁⲣⲉϥⲥⲱⲧⲉⲙ.
16 “Kí ni èmi ìbá fi ìran yìí wé? Ó dàbí àwọn ọmọ kékeré tí ń jókòó ní ọjà tí wọ́n sì ń ké pe àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn:
ⲓ̅ⲋ̅ⲁⲓⲛⲁⲧⲉⲛⲑⲱⲛ ⲧⲁⲓⲅ⳿ⲉⲛⲉ⳿ⲁ ⲇⲉ ⳿ⲉⲛⲓⲙ ⳿ⲥ⳿ⲟⲛⲓ ⳿ⲛϩⲁⲛ⳿ⲁⲗⲱⲟⲩ⳿ⲓ ⲉⲩϩⲉⲙⲥⲓ ϩⲓ ⲛⲓ⳿ⲁⲅⲟⲣⲁ ⲛⲁⲓ ⲉⲑⲙⲟⲩϯ ⲟⲩⲃⲉ ⲛⲟⲩ⳿ⲉⲣⲏⲟⲩ.
17 “‘Àwa ń fun fèrè fún yín, ẹ̀yin kò jó; àwa kọrin ọ̀fọ̀ ẹ̀yin kò káàánú.’
ⲓ̅ⲍ̅ⲉⲩϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ⲁⲛϫⲱ ⳿ⲉⲣⲱⲧⲉⲙ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲙⲡⲉⲧⲉⲛϭⲟⲥϫⲉⲥ ⲁⲛⲣⲓⲙⲓ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲙⲡⲉⲧⲉⲛⲛⲉϩⲡⲓ.
18 Nítorí Johanu wá kò bá a yín jẹ bẹ́ẹ̀ ni kò mu, ẹ̀yin sì wí pé, ‘Ó ní ẹ̀mí èṣù.’
ⲓ̅ⲏ̅ⲁϥ⳿ⲓ ⲅⲁⲣ ⳿ⲛϫⲉ Ⲓⲱⲁⲛⲛⲏⲥ ⳿ⲛ⳿ϥⲟⲩⲱⲙ ⲁⲛ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛ⳿ϥⲥⲱ ⲁⲛ ⲡⲉϫⲱⲟⲩ ϫⲉ ⲟⲩⲟⲛ ⲟⲩⲇⲉⲙⲱⲛ ⲛⲉⲙⲁϥ.
19 Ọmọ Ènìyàn wá bá a yín jẹun, ó sì bá yin mu, wọ́n wí pé, ‘Ọ̀jẹun àti ọ̀mùtí; ọ̀rẹ́ àwọn agbowó òde àti àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀.’ Ṣùgbọ́n a dá ọgbọ́n láre nípa ìṣe rẹ̀.”
ⲓ̅ⲑ̅ⲁϥ⳿ⲓ ⲇⲉ ⳿ⲛϫⲉ Ⲡ̇ϣⲏⲣⲓ ⳿ⲙⲪ̇ⲣⲱⲙⲓ ⲉϥⲟⲩⲱⲙ ⲟⲩⲟϩ ⲉϥⲥⲱ ⲡⲉϫⲱⲟⲩ ϫⲉ ⲓⲥ ⲟⲩⲣⲱⲙⲓ ⳿ⲛⲣⲉϥⲟⲩⲱⲙ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲥⲁⲩⲏⲣⲡ ⳿ⲡ⳿ϣⲫⲏⲣ ⲡⲉ ⳿ⲛⲧⲉ ⲛⲓⲧⲉⲗⲱⲛⲏⲥ ⲛⲉⲙ ⲛⲓⲣⲉϥⲉⲣⲛⲟⲃⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲥ⳿ⲑⲙⲁⲓ⳿ⲟ ⳿ⲛϫⲉ ϯⲥⲟⲫⲓ⳿ⲁ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲛⲉⲥ⳿ϩⲃⲏⲟⲩ⳿ⲓ.
20 Nígbà náà ni Jesu bẹ̀rẹ̀ sí í bá ìlú tí ó ti ṣe ọ̀pọ̀ iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ wí, nítorí wọn kò ronúpìwàdà.
ⲕ̅ⲧⲟⲧⲉ ⲁϥⲉⲣϩⲏⲧⲥ ⳿ⲛϩⲓⲭⲟϩ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉⲛⲓⲃⲁⲕⲓ ⲛⲏ⳿ⲉⲧⲁ ⳿ⲡϩⲟⲩ⳿ⲟ ⳿ⲛⲛⲉϥϫⲟⲙ ϣⲱⲡⲓ ⳿ⲛϧⲏⲧⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲙⲡⲟⲩⲉⲣⲙⲉⲧⲁⲛⲟⲓⲛ.
21 Ó wí pé, “Ègbé ni fún ìwọ Korasini, ègbé ni fún ìwọ Betisaida! Ìbá ṣe pé a ti ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu tí a ṣe nínú yín ní a ṣe ni Tire àti Sidoni, àwọn ènìyàn wọn ìbá ti ronúpìwàdà ti pẹ́ nínú aṣọ ọ̀fọ̀ àti eérú.
ⲕ̅ⲁ̅ⲟⲩⲟⲓ ⲛⲉ Ⲭⲟⲣⲁⲍⲓⲛ ⲟⲩⲟⲓ ⲛⲉ Ⲃⲏⲑⲥⲁ⳿ⲓⲇⲁ ϫⲉ ⳿⳿ⲉⲛⲉ ⳿ⲁ ⲛⲁⲓϫⲟⲙ ϣⲱⲡⲓ ϧⲉⲛ Ⲧⲩⲣⲟⲥ ⲛⲉⲙ ⳿ⲧⲤⲓⲇⲱⲛ ⳿ⲉⲧⲁⲩϣⲱⲡⲓ ϧⲉⲛ ⲑⲏⲛⲟⲩ ⲛⲉ ⲓⲥ⳿ⲑⲛⲉⲓ ⲡⲉ ⲁⲩⲉⲣⲙⲉⲧⲁⲛⲟⲓⲛ ϧⲉⲛ ⲟⲩⲥⲟⲕ ⲛⲉⲙ ⲟⲩⲕⲉⲣⲙⲓ.
22 Ṣùgbọ́n mo wí fún yín, yóò sàn fún Tire àti Sidoni ní ọjọ́ ìdájọ́ jù fún yín.
ⲕ̅ⲃ̅⳿ⲡⲗⲏⲛ ϯϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⲛⲱⲧⲉⲛ ϫⲉ Ⲧⲩⲣⲟⲥ ⲛⲉⲙ ⳿ⲧⲤⲓⲇⲱⲛ ⲉⲩ⳿ⲉϯ⳿ⲁⲥⲟ ⳿ⲉⲣⲱⲟⲩ ϧⲉⲛ ⳿ⲡ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⳿ⲛⲧⲉ ϯ⳿ⲕⲣⲓⲥⲓⲥ ⳿ⲉϩⲟⲧⲉⲣⲱⲧⲉⲛ.
23 Àti ìwọ Kapernaumu, a ó ha gbé ọ ga sókè ọ̀run? Rárá, a ó rẹ̀ ọ́ sílẹ̀ sí ipò òkú. Nítorí, ìbá ṣe pé a ti ṣe iṣẹ́ ìyanu tí a ṣe nínú rẹ ní Sodomu, òun ìbá wà títí di òní. (Hadēs )
ⲕ̅ⲅ̅ⲛⲉⲙ ⳿ⲛⲑⲟ ϩⲱⲓ Ⲕⲁⲫⲁⲣⲛⲁⲟⲩⲙ ⲙⲏ ⲧⲉⲣⲁϭⲓⲥⲓ ϣⲁ ⳿ⲉ⳿ϩⲣⲏⲓ ⳿ⲉ⳿ⲧⲫⲉ ⲉⲩ⳿ⲉⲑⲉⲃⲓ⳿ⲟ ϣⲁ ⳿ⲉ⳿ϧⲣⲏⲓ ⳿ⲉ⳿ⲁⲙⲉⲛϯ ϫⲉ ⳿⳿ⲉⲛⲉ ϧⲉⲛ Ⲥⲟⲇⲟⲙⲁ ⲁⲩϣⲱⲡⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲁⲓϫⲟⲙ ⳿ⲉⲧⲁⲩϣⲱⲡⲓ ⳿ⲛϧⲏϯ ⲛⲉ ⲓⲥϫⲉⲕ ⲥⲉϣⲟⲡ ϣⲁ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉⲫⲟⲟⲩ. (Hadēs )
24 Lóòótọ́ yóò sàn fún ilẹ̀ Sodomu ní ọjọ́ ìdájọ́ jù fún ìwọ lọ.”
ⲕ̅ⲇ̅⳿ⲡⲗⲏⲛ ϯϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⲛⲱⲧⲉⲛ ϫⲉ ⲡⲕⲁϩⲓ ⳿ⲛⲤⲟⲇⲟⲙⲁ ⲉⲩ⳿ⲉϯ⳿ⲁⲥⲟ ⳿ⲉⲣⲟϥ ϧⲉⲛ ⳿ⲡ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⳿ⲛⲧⲉ ϯ⳿ⲕⲣⲓⲥⲓⲥ ⳿ⲉϩⲟⲧⲉⲣⲟ.
25 Nígbà náà ni Jesu wí pé, “Mo yìn ọ Baba, Olúwa ọ̀run àti ayé, nítorí ìwọ ti fi òtítọ́ yìí pamọ́ fún àwọn tó jẹ́ ọlọ́gbọ́n àti amòye, Ìwọ sì ti fi wọ́n hàn fún àwọn ọmọ wẹ́wẹ́.
ⲕ̅ⲉ̅⳿ⲛ⳿ϩⲣⲏⲓ ⲇⲉ ϧⲉⲛ ⲡⲓⲥⲏⲟⲩ ⳿ⲉⲧⲉ⳿ⲙⲙⲁⲩ ⲁϥ⳿ⲉⲣⲟⲩ⳿ⲱ ⳿ⲛϫⲉ Ⲓⲏ̅ⲥ̅ ⲟⲩⲟϩ ⲡⲉϫⲁϥ ϫⲉ ϯⲟⲩⲱⲛϩ ⲛⲁⲕ ⳿ⲉⲃⲟⲗ Ⲫ̇ⲓⲱⲧ Ⲡ⳪ ⳿ⲛ⳿ⲧⲫⲉ ⲛⲉⲙ ⳿ⲡⲕⲁϩⲓ ϫⲉ ⲁⲕϩⲉⲡ ⲛⲁⲓ ⳿ⲉϩⲁⲛⲥⲁⲃⲉⲩ ⲛⲉⲙ ϩⲁⲛⲕⲁⲧϩⲏ ⲧ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲕϭⲟⲣⲡⲟⲩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲛϩⲁⲛⲕⲟⲩϫⲓ ⳿ⲛ⳿ⲁⲗⲱⲟⲩ⳿ⲓ.
26 Bẹ́ẹ̀ ni, Baba, nítorí ó wù ọ́ láti ṣe bẹ́ẹ̀.
ⲕ̅ⲋ̅⳿ⲁϩⲁ Ⲫ̇ⲓⲱⲧ ϫⲉ ⲫⲁⲓ ⲡⲉ ⲡⲓϯⲙⲁϯ ⳿ⲉⲧⲁϥϣⲱⲡⲓ ⳿ⲙⲡⲉⲕ⳿ⲙⲑⲟ.
27 “Ohun gbogbo ni Baba mi ti fi sí ìkáwọ́ mi. Kò sí ẹni tí ó mọ ọmọ bí kò ṣe Baba, bẹ́ẹ̀ ni kò sí ẹnikẹ́ni tí ó mọ Baba, bí kò ṣe ọmọ, àti àwọn tí ọmọ yan láti fi ara hàn fún.
ⲕ̅ⲍ̅ϩⲱⲃ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⳿ⲁ Ⲫ̇ⲓⲱⲧ ⲧⲏⲓⲧⲟⲩ ⳿ⲉⲧⲟⲧ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲙⲙⲟⲛ ⳿ϩⲗⲓ ⲥⲱⲟⲩⲛ ⳿ⲙⲠ̇ϣⲏⲣⲓ ⳿ⲉⲃⲏⲗ ⳿ⲉⲪ̇ⲓⲱⲧ ⲟⲩⲇⲉ ⳿ⲙⲙⲟⲛ ⳿ϩⲗⲓ ⲥⲱⲟⲩⲛ ⳿ⲙⲪ̇ⲓⲱⲧ ⳿ⲉⲃⲏⲗ ⳿ⲉⲠ̇ϣⲏⲣⲓ ⲛⲉⲙ ⲫⲏ⳿ⲉⲧⲉϩⲛⲉ Ⲡ̇ϣⲏⲣⲓ ⳿ⲉϭⲱⲣⲡ ⲛⲁϥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ.
28 “Ẹ wá sọ́dọ̀ mi gbogbo ẹ̀yin tí ń ṣiṣẹ́ tí a sì di ẹrù wíwúwo lé lórí, èmi yóò sì fún yín ní ìsinmi.
ⲕ̅ⲏ̅⳿ⲁⲙⲱⲓⲛⲓ ϩⲁⲣⲟⲓ ⲟⲩⲟⲛ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲉⲧϧⲟⲥⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲉⲧⲟⲡⲧ ϧⲁ ⲛⲟⲩⲉⲧⲫⲱⲟⲩ⳿ⲓ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲁⲛⲟⲕ ⲉⲑⲛⲁϯ⳿ⲙⲧⲟⲛ ⲛⲱⲧⲉⲛ.
29 Ẹ gbé àjàgà mi wọ̀. Ẹ kọ́ ẹ̀kọ́ lọ́dọ̀ mi nítorí onínútútù àti onírẹ̀lẹ̀ ọkàn ni èmi, ẹ̀yin yóò sì ri ìsinmi fún ọkàn yín.
ⲕ̅ⲑ̅⳿ⲁⲗⲓⲟⲩ⳿ⲓ ⳿ⲙⲡⲁⲛⲁϩⲃⲉϥ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⲑⲏⲛⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲁⲣⲓ⳿ⲉⲙⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲙⲙⲟⲓ ϫⲉ ⳿ⲁⲛⲟⲕ ⲟⲩⲣⲉⲙⲣⲁⲩϣ ⲟⲩⲟϩ ϯⲑⲉⲃⲓⲏⲟⲩⲧ ϧⲉⲛ ⲡⲁϩⲏⲧ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉⲣⲉⲧⲉⲛ⳿ⲉϫⲓⲙⲓ ⳿ⲛⲟⲩⲙⲁⲛⲉⲙⲧⲟⲛ ⳿ⲛⲛⲉⲧⲉⲛⲯⲩⲭⲏ.
30 Nítorí àjàgà mi rọrùn ẹrù mi sì fúyẹ́.”
ⲗ̅ⲡⲁⲛⲁϩⲃⲉϥ ⲅⲁⲣ ⳿ϥϩⲟⲗϫ ⲟⲩⲟϩ ⲧⲁⲉⲧⲫⲱ ⳿ⲁⲥⲓ⳿ⲱⲟⲩ