< Mark 9 >
1 Ó sì wí fún wọn pé, “Lóòótọ́ ni mo wí fún un yín àwọn mìíràn wa nínú àwọn tó dúró níhìn-ín yìí, tí kì yóò tọ́ ikú wò, títí yóò fi rí ìjọba Ọlọ́run tí yóò fi dé pẹ̀lú agbára.”
ⲁ̅ⲟⲩⲟϩ ⲛⲁϥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⲛⲱⲟⲩ ϫⲉ ⳿ⲁⲙⲏⲛ ϯϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⲛⲱⲧⲉⲛ ϫⲉ ⲟⲩⲟⲛ ϩⲁⲛⲟⲩⲟⲛ ϧⲉⲛ ⲛⲏⲉⲧ⳿ⲟϩⲓ ⳿ⲉⲣⲁⲧⲟⲩ ⳿ⲙⲡⲁⲓⲙⲁ ⳿ⲛⲥⲉⲛⲁϫⲉⲙϯⲡⲓ ⳿ⲙ⳿ⲫⲙⲟⲩ ⲁⲛ ϣⲁⲧⲟⲩⲛⲁⲩ ⳿ⲉϯⲙⲉⲧⲟⲩⲣⲟ ⳿ⲛⲧⲉ Ⲫϯ ⳿ⲉⲁⲥ⳿ⲓ ϧⲉⲛ ⲟⲩϫⲟⲙ.
2 Lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́fà tí Jesu sọ̀rọ̀ yìí, Jesu mú Peteru, Jakọbu àti Johanu lọ sí orí òkè gíga ní apá kan. Kò sí ẹlòmíràn pẹ̀lú wọn, ara rẹ̀ sì yípadà níwájú wọn.
ⲃ̅ⲟⲩⲟϩ ⲙⲉⲛⲉⲛⲥⲁ ⲋ̅ ⳿ⲛ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⲁϥϭⲓ ⳿ⲛϫⲉ Ⲓⲏ̅ⲥ̅ ⳿ⲙⲠⲉⲧⲣⲟⲥ ⲛⲉⲙ Ⲓⲁⲕⲱⲃⲟⲥ ⲛⲉⲙ Ⲓⲱⲁⲛⲛⲏⲥ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥ⳿ⲟⲗⲟⲩ ⳿ⲉ⳿ϩⲣⲏⲓ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⲟⲩⲧⲱⲟⲩ ⲉϥϭⲟⲥⲓ ⲥⲁ⳿ⲡⲥⲁ ⳿ⲙⲙⲁⲩⲁⲧⲟⲩ ⲁϥϣⲟⲃⲧϥ ⳿ⲙⲡⲟⲩ⳿ⲙⲑⲟ.
3 Aṣọ rẹ̀ sì di dídán, ó sì funfun gbòò, tí alágbàfọ̀ kan ní ayé kò lè sọ di funfun bẹ́ẹ̀.
ⲅ̅ⲟⲩⲟϩ ⲛⲉϥ⳿ϩⲃⲱⲥ ⲁⲩϣⲱⲡⲓ ⲉⲩⲫⲟⲣⲓ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲛⲟⲩⲭⲓⲱⲛ ⲉⲩⲟⲩⲟⲃϣ ⳿ⲉⲙⲁϣⲱ ⲛⲏ⳿ⲉⲧⲉ ⳿ⲙⲙⲟⲛ⳿ϣϫⲟⲙ ⳿ⲛⲧⲉ ⲣⲁϧⲧ ⲉⲧϩⲓϫⲉⲛ ⲡⲓⲕⲁϩⲓ ⲉⲑⲣⲉ ⲟⲩⲟⲛ ⲟⲩⲃⲁϣ ⳿ⲙⲡⲁⲓⲣⲏϯ.
4 Nígbà náà ni Elijah àti Mose farahàn fún wọn, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀ pẹ̀lú Jesu.
ⲇ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩⲟⲩⲟⲛϩⲟⲩ ⳿ⲉⲣⲱⲟⲩ ⳿ⲛϫⲉ Ⲏ̇ⲗⲓⲁⲥ ⲛⲉⲙ Ⲙⲱ⳿ⲩⲥⲏⲥ ⲟⲩⲟϩ ⲛⲁⲩⲥⲁϫⲓ ⲛⲉⲙ Ⲓⲏ̅ⲥ̅.
5 Peteru sì wí fún Jesu pé, “Rabbi, ó dára fún wa láti máa gbé níhìn-ín, si jẹ́ kí a pa àgọ́ mẹ́ta, ọ̀kan fun ọ, ọ̀kan fún Mose, àti ọ̀kan fún Elijah.”
ⲉ̅ⲟⲩⲟϩ ⲧⲟⲧⲉ ⳿ⲉⲧⲁϥ⳿ⲉⲣⲟⲩ⳿ⲱ ⳿ⲛϫⲉ Ⲡⲉⲧⲣⲟⲥ ⲡⲉϫⲁϥ ⳿ⲛⲒⲏ̅ⲥ̅ ϫⲉ ⲣⲁⲃⲃⲓ ⲛⲁⲛⲉⲥ ⲛⲁⲛ ⳿ⲛⲧⲉⲛϣⲱⲡⲓ ⳿ⲙⲡⲁⲓⲙⲁ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲧⲉⲛⲑⲁⲙⲓ⳿ⲟ ⳿ⲛⲅ̅ ⳿ⲛ⳿ⲥⲕⲩⲛⲏ ⲟⲩ⳿ⲓ ⲛⲁⲕ ⲟⲩ⳿ⲓ ⳿ⲙⲘⲱ⳿ⲩⲥⲏⲥ ⲟⲩⲟϩ ⲟⲩ⳿ⲓ ⳿ⲛⲎ̇ⲗⲓⲁⲥ.
6 Nítorí òun kò mọ ohun tí òun ìbá sọ, nítorí ẹ̀rù bà wọ́n gidigidi.
ⲋ̅ⲛⲁϥ⳿ⲉⲙⲓ ⲅⲁⲣ ⲁⲛ ϫⲉ ⲟⲩ ⲡⲉⲧⲉϥⲛⲁ⳿ⲉⲣⲟⲩ⳿ⲱ ⳿ⲙⲙⲟϥ ⲁⲩϣⲱⲡⲓ ⲅⲁⲣ ⲉⲩⲙⲉϩ ⳿ⲛϩⲟϯ.
7 Ìkùùkuu kan sì bò wọ́n, ohùn kan sì ti inú ìkùùkuu náà wá wí pé, “Èyí ni àyànfẹ́ ọmọ mi. Ẹ máa gbọ́ ti rẹ̀!”
ⲍ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲥϣⲱⲡⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲟⲩϭⲏⲡⲓ ⲉⲥⲉⲣϧⲏⲓⲃⲓ ⳿ⲉⲣⲱⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲥϣⲱⲡⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲟⲩ⳿ⲥⲙⲏ ⳿ⲉⲃⲟⲗϧⲉⲛ ϯϭⲏⲡⲓ ϫⲉ ⲫⲁⲓ ⲡⲉ ⲡⲁϣⲏⲣⲓ ⲡⲁⲙⲉⲛⲣⲓⲧ ⲥⲱⲧⲉⲙ ⳿ⲛⲥⲱϥ.
8 Lójijì, wọ́n wo àyíká wọn, wọn kò sì rí ẹnìkankan mọ́, bí kò ṣe Jesu nìkan ṣoṣo ni ó sì wà pẹ̀lú wọn.
ⲏ̅ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉⲧⲁⲩϫⲟⲩϣⲧ ⳿ⲉⲝⲁⲡⲓⲛⲁ ⳿ⲙⲡⲟⲩⲛⲁⲩ ⳿ⲉ⳿ϩⲗⲓ ⳿ⲉⲃⲏⲗ ⳿ⲉⲒⲏ̅ⲥ̅ ⳿ⲙⲙⲁⲩⲁⲧϥ ⲛⲉⲙⲱⲟⲩ.
9 Bí wọ́n ti ń sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè, Jesu kìlọ̀ fún wọn kí wọ́n má ṣe sọ ohun tí wọ́n ti rí fún ẹnikẹ́ni títí Ọmọ Ènìyàn yóò fi jíǹde kúrò nínú òkú.
ⲑ̅ⲟⲩⲟϩ ⲉⲩⲛⲏⲟⲩ ⳿ⲉ⳿ϧⲣⲏⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗϩⲓ ⲡⲓⲧⲱⲟⲩ ⲁϥϩⲟⲛϩⲉⲛ ⳿ⲉⲧⲟⲧⲟⲩ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲧⲟⲩ⳿ϣⲧⲉⲙⲥⲁϫⲓ ϧⲁⲧⲉⲛ ⳿ϩⲗⲓ ⳿ⲙⲡⲉⲧⲁⲩⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⳿ⲉⲃⲏⲗ ⳿ⲛⲧⲉ Ⲡ̇ϣⲏⲣⲓ ⳿ⲙⲪ̇ⲣⲱⲙⲓ ⲧⲱⲛϥ ⳿ⲉⲃⲟⲗϧⲉⲛ ⲛⲏⲉⲑⲙⲱⲟⲩⲧ.
10 Nítorí náà, wọ́n pa nǹkan náà mọ́ ní ọkàn wọn. Ṣùgbọ́n wọ́n ń béèrè lọ́wọ́ ara wọn ohun tí àjíǹde kúrò nínú òkú túmọ̀ sí.
ⲓ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩ⳿ⲁⲙⲟⲛⲓ ⳿ⲙⲡⲓⲥⲁϫⲓ ⳿ⲛϧⲏⲧⲟⲩ ⲉⲩⲕⲱϯ ⲛⲉⲙ ⳿ⲛⲛⲟⲩ⳿ⲉⲣⲏⲟⲩ ϫⲉ ⲟⲩ ⲡⲉ ⲡⲓⲧⲱⲛϥ ⳿ⲉⲃⲟⲗϧⲉⲛ ⲛⲏⲉⲑⲙⲱⲟⲩⲧ.
11 Nísinsin yìí, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí í béèrè lọ́wọ́ rẹ̀, èéṣe tí àwọn olùkọ́ òfin ń sọ wí pé, “Elijah ní yóò kọ́kọ́ dé.”
ⲓ̅ⲁ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩϣⲉⲛϥ ⲉⲩϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ⲉⲑⲃⲉⲟⲩ ⲛⲓⲥⲁϧ ⲥⲉϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ϩⲱϯ ⲡⲉ ⳿ⲛⲧⲉ Ⲏ̇ⲗⲓⲁⲥ ⳿ⲓ ⳿ⲛϣⲟⲣⲡ.
12 Ó sì dáhùn ó sì wí fún wọn pé, “Lóòótọ́ ni Elijah yóò kọ́kọ́ dé yóò sì mú nǹkan gbogbo padà bọ̀ sípò. Àní gẹ́gẹ́ bí a ti kọ̀wé rẹ nípa ti Ọmọ Ènìyàn pé kò le ṣàìmá jìyà ohun púpọ̀ àti pé a ó sì kọ̀ ọ́ sílẹ̀.
ⲓ̅ⲃ̅⳿ⲛⲑⲟϥ ⲇⲉ ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲱⲟⲩ ϫⲉ Ⲏ̇ⲗⲓⲁⲥ ⲙⲉⲛ ⳿ϥⲛⲁ⳿ⲓ ⳿ⲛϣⲟⲣⲡ ⲟⲩⲟϩ ⳿ϥⲛⲁⲧⲁⲫⲉ ϩⲱⲃ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲟⲩⲟϩ ⲡⲱⲥ ⳿ⲥ⳿ⲥϧⲏⲟⲩⲧ ⳿ⲉϫⲉⲛ Ⲡ̇ϣⲏⲣⲓ ⳿ⲙⲪ̇ⲣⲱⲙⲓ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲧⲉϥϭⲓ ⲟⲩⲙⲏϣ ⳿ⲛϧⲓⲥⲓ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲧⲟⲩϣⲟϣϥ.
13 Ṣùgbọ́n mo wí fún yín pé, Elijah ti wa ná, wọ́n sì ti ṣe ohunkóhun tí ó wù wọ́n sí i, gẹ́gẹ́ bí a ti kọ̀wé nípa rẹ̀.”
ⲓ̅ⲅ̅ⲁⲗⲗⲁ ϯϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⲛⲱⲧⲉⲛ ϫⲉ Ⲏ̇ⲗⲓⲁⲥ ⲁϥ⳿ⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩ⳿⳿ⲓⲣⲓ ⲛⲁϥ ⳿ⲙⲡⲉⲧⲟⲩⲟⲩⲁϣϥ ⲕⲁⲧⲁ⳿ⲫⲣⲏϯ ⲉⲧ⳿ⲥϧⲏⲟⲩⲧ ⳿ⲉϫⲱϥ.
14 Nígbà tí wọ́n sọ̀kalẹ̀ pátápátá sí ẹsẹ̀ òkè náà, wọ́n bá ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn tí wọ́n yí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mẹ́sàn-án ìyókù ká. Àwọn olùkọ́ òfin díẹ̀ sì ń bá wọn jiyàn.
ⲓ̅ⲇ̅ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉⲧⲁϥ⳿ⲓ ϩⲁ ⲛⲓⲙⲁⲑⲏⲧⲏⲥ ⲁϥⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲟⲩⲙⲏϣ ⲉϥⲟϣ ⳿ⲙⲡⲟⲩⲕⲱϯ ⲟⲩⲟϩ ϩⲁⲛⲥⲁϧ ⲉⲩⲕⲱϯ ⲛⲉⲙⲱⲟⲩ.
15 Bí Jesu ti ń súnmọ́ ọ̀pọ̀ ènìyàn wọ̀nyí ni wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ sí í wò ó pẹ̀lú ìbẹ̀rù, nígbà náà ni wọ́n sáré lọ kí i.
ⲓ̅ⲉ̅ⲟⲩⲟϩ ⲥⲁⲧⲟⲧϥ ⲡⲓⲙⲏϣ ⲧⲏⲣϥ ⳿ⲉⲧⲁⲩⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⲁⲩⲉⲣϩⲟϯ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉⲧⲁⲩϭⲟϫⲓ ⲛⲁⲩⲉⲣⲁⲥⲡⲁⲍⲉⲥⲑⲉ ⳿ⲙⲙⲟϥ.
16 Jesu béèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Kí ló fa àríyànjiyàn?”
ⲓ̅ⲋ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁϥϣⲉⲛⲟⲩ ϫⲉ ⳿ⲁⲣⲉⲧⲉⲛⲕⲱϯ ⳿ⲛⲥⲁ ⲟⲩ ⳿ⲛⲧⲟⲧⲟⲩ.
17 Ọkùnrin kan láàrín ọ̀pọ̀ ènìyàn dáhùn pé, “Olùkọ́, èmi ni mo mú ọmọ yìí wá fún ọ láti wò ó sàn. Kò lè sọ̀rọ̀ rárá, nítorí tí ó ní ẹ̀mí àìmọ́.
ⲓ̅ⲍ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁϥ⳿ⲉⲣⲟⲩ⳿ⲱ ⲛⲁϥ ⳿ⲛϫⲉ ⲟⲩⲁⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗϧⲉⲛ ⲡⲓⲙⲏϣ ϫⲉ ⳿ⲫⲣⲉϥϯ⳿ⲥⲃⲱ ⲁⲓⲉⲛ ⲡⲁϣⲏⲣⲓ ϩⲁⲣⲟⲕ ⳿ⲉⲟⲩⲟⲛ ⲟⲩⲡ͞ⲛⲁ̅ ⳿ⲛⲁⲧⲥⲁϫⲓ ⲛⲉⲙⲁϥ.
18 Àti pé, nígbàkígbà tí ó bá mú un, á gbé e ṣánlẹ̀, a sì máa hó itọ́ lẹ́nu, a sì máa lọ́ eyín rẹ̀. Òun pàápàá a wá le gbagidi. Mo sì bẹ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ kí wọn lé ẹ̀mí àìmọ́ náà jáde, ṣùgbọ́n wọ́n kò lè ṣe é.”
ⲓ̅ⲏ̅ⲟⲩⲟϩ ⲡⲓⲙⲁ ⳿ⲉⲧⲉϥⲛⲁⲧⲁϩⲟϥ ⳿ⲙⲙⲁⲩ ϣⲁϥⲉⲛϥ ⳿ⲉⲡⲉⲥⲏⲧ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲧⲉ ⲣⲱϥ ϫⲉϣ⳿ⲥⲫⲏⲓϯ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲉϥ⳿ϧⲣⲁϫⲣⲉϫ ⳿ⲛⲛⲉϥⲛⲁϫϩⲓ ⲟⲩⲟϩ ϣⲁϥϣⲱⲟⲩ⳿ⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲓϫⲟⲥ ⳿ⲛⲛⲉⲕⲙⲁⲑⲏⲧⲏⲥ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲧⲟⲩϩⲓⲧϥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲙⲡⲟⲩ⳿ϣϫⲉⲙϫⲟⲩ.
19 Ó sì dá wọn lóhùn, ó wí pé, “Ẹ̀yin ìran aláìgbàgbọ́ yìí, èmi yóò ti bá a yín gbé pẹ́ tó? Èmi yóò sì ti mú sùúrù fún un yín pẹ́ tó? Ẹ mú ọmọ náà wá sọ́dọ̀ mi.”
ⲓ̅ⲑ̅ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲑⲟϥ ⳿ⲉⲧⲁϥ⳿ⲉⲣⲟⲩ⳿ⲱ ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲱⲟⲩ ϫⲉ ⳿ⲱ ⲡⲓϫⲱⲟⲩ ⳿ⲛⲁⲑⲛⲁϩϯ ϣⲁ ⳿ⲑⲛⲁⲩ ϯⲛⲁϣⲱⲡⲓ ⲛⲉⲙⲱⲧⲉⲛ ϣⲁ ⳿ⲑⲛⲁⲩ ϯⲛⲉⲁⲣ⳿ⲁⲛⲁⲭⲉⲥⲑⲉ ⳿ⲙⲙⲱⲧⲉⲛ ⳿ⲁⲛⲓⲧϥ ϩⲁⲣⲟⲓ.
20 Wọ́n sì mú un wá sọ́dọ̀ rẹ̀: nígbà tí ó sì rí i, lójúkan náà ẹ̀mí náà nà án tàntàn ó sì ṣubú lu ilẹ̀, ó sì ń fi ara yílẹ̀, ó sì ń yọ ìfófó lẹ́nu.
ⲕ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩⲉⲛϥ ϩⲁⲣⲟϥ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉⲧⲁϥⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⳿ⲛϫⲉ ⲡⲓⲡ͞ⲛⲁ̅ ⲥⲁⲧⲟⲧϥ ⲁϥ⳿ϣⲧⲉⲣⲑⲱⲣϥ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉⲧⲁϥϩⲉⲓ ϩⲓϫⲉⲛ ⲡⲓⲕⲁϩⲓ ⲛⲁϥ⳿ⲥⲑⲉⲣⲧⲉⲣ ⲡⲉ ⳿ⲉⲣⲉ ⲣⲱϥ ϫⲉϣ⳿ⲥⲫⲏⲓϯ ⳿ⲉⲃⲟⲗ.
21 Jesu béèrè lọ́wọ́ baba ọmọ náà pé, “Ó tó ìgbà wo tí ọmọ rẹ̀ ti wà nínú irú ipò báyìí?” Baba ọmọ náà dáhùn pé, “Láti kékeré ni.”
ⲕ̅ⲁ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁϥϣⲉⲛ ⲡⲉϥⲓⲱⲧ ϫⲉ ⲓⲥ ⲟⲩⲏⲣ ⳿ⲛ⳿ⲭⲣⲟⲛⲟⲥ ⲓⲥϫⲉⲛ ⳿ⲉⲧⲁ ⲫⲁⲓ ϣⲱⲡⲓ ⳿ⲙⲙⲟϥ ⳿ⲛⲑⲟϥ ⲇⲉ ⲡⲉϫⲁϥ ϫⲉ ⲓⲥϫⲉⲛ ⲧⲉϥⲙⲉⲧ⳿ⲁⲗⲟⲩ.
22 Nígbàkígbà ni ó sì máa ń gbé e sínú iná àti sínú omi, láti pa á run, ṣùgbọ́n bí ìwọ bá lè ṣe ohunkóhun, ṣàánú fún wa, kí o sì ràn wá lọ́wọ́.
ⲕ̅ⲃ̅ⲟⲩⲟϩ ⲟⲩⲙⲏϣ ⳿ⲛⲥⲟⲡ ϣⲁϥϩⲓⲧϥ ⳿ⲉⲡⲓ⳿ⲭⲣⲱⲙ ⲛⲉⲙ ⲡⲓⲙⲱⲟⲩ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲧⲉϥⲧⲁⲕⲟϥ ⲁⲗⲗⲁ ⲡⲉⲧⲉ ⲟⲩⲟⲛ⳿ϣϫⲟⲙ ⳿ⲙⲙⲟⲕ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⳿ⲁⲣⲓⲃⲟ⳿ⲏⲑⲓⲛ ⳿ⲉⲣⲟⲛ ⳿ⲉⲁⲕϣⲉⲛϩⲏⲧ ⳿ⲉϫⲱⲛ.
23 “Jesu sì wí fún un pé, ‘Bí ìwọ bá le gbàgbọ́: ohun gbogbo ni ó ṣe é ṣe fún ẹni tí ó bá gbàgbọ́.’”
ⲕ̅ⲅ̅Ⲓⲏ̅ⲥ̅ ⲇⲉ ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲁϥ ϫⲉ ⲟⲩ ⲡⲉ ϫⲉ ⲫⲏ⳿ⲉⲧⲉ ⲟⲩⲟⲛ⳿ϣϫⲟⲙ ⳿ⲙⲙⲟⲕ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⲟⲩⲟⲛ⳿ϣϫⲟⲙ ⳿ⲛϩⲱⲃ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⳿ⲙⲫⲏⲉⲑⲛⲁϩϯ.
24 Lójúkan náà baba ọmọ náà kígbe ní ohùn rara, ó sì wí pé, “Olúwa, mo gbàgbọ́, ran àìgbàgbọ́ mi lọ́wọ́.”
ⲕ̅ⲇ̅ⲥⲁⲧⲟⲧϥ ⲁϥⲱϣ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲛϫⲉ Ⲫ̇ⲓⲱⲧ ⳿ⲙⲡⲓ⳿ⲁⲗⲟⲩ ϧⲉⲛ ϩⲁⲛⲉⲣⲙⲱⲟⲩ⳿ⲓ ⲉϥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ϯⲛⲁϩϯ Ⲡ⳪ ⳿ⲁⲣⲓⲃⲟ⳿ⲏⲑⲓⲛ ⳿ⲉⲧⲁⲙⲉⲧⲁⲑⲛⲁϩϯ.
25 Nígbà tí Jesu rí i pé ọ̀pọ̀ ènìyàn ń péjọ sọ́dọ̀ wọn, ó bá ẹ̀mí àìmọ́ náà wí pé, “Ìwọ ẹ̀mí àìmọ́, adití àti odi, mo pàṣẹ fún ọ, kí ó jáde kúrò lára ọmọ yìí, kí ó má ṣe padà sí ibẹ̀ mọ́.”
ⲕ̅ⲉ̅⳿ⲉⲧⲁϥⲛⲁⲩ ⲇⲉ ⳿ⲛϫⲉ Ⲓⲏ̅ⲥ̅ ϫⲉ ⲡⲓⲙⲏϣ ϭⲟϫⲓ ⲁϥⲉⲣ⳿ⲉⲡⲓⲧⲓⲙⲁⲛ ⳿ⲙⲡⲓⲡ͞ⲛⲁ̅ ⳿ⲛ⳿ⲁⲕⲁⲑⲁⲣⲧⲟⲛ ⲉϥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⲛⲁϥ ϫⲉ ⲡⲓⲁⲧⲥⲁϫⲓ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲕⲟⲩⲣ ⳿ⲙⲡ͞ⲛⲁ̅ ⳿ⲁⲛⲟⲕ ⲡⲉ ϯⲟⲩⲁϩⲥⲁϩⲛⲓ ⳿ⲙⲙⲟⲕ ⳿ⲁⲙⲟⲩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲛϧⲏⲧϥ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲙⲡⲉⲣϣⲉ ϫⲉ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉⲣⲟϥ.
26 Òun sì kígbe ńlá, ó sì nà án tàntàn, ó sì jáde kúrò lára rẹ̀, ọmọ náà sì dàbí ẹni tí ó kú tó bẹ́ẹ̀ tí ọ̀pọ̀ ènìyàn ké wí pé, “Hé è, ọmọ náà ti kú.”
ⲕ̅ⲋ̅ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉⲧⲁϥⲱϣ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉⲧⲁϥ⳿ϣⲧⲉⲣⲑⲱⲣϥ ⳿ⲛⲟⲩⲙⲏϣ ⲁϥ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥⲉⲣ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲛⲟⲩⲣⲉϥⲙⲱⲟⲩⲧ ϩⲱⲥⲧⲉ ⳿ⲛⲧⲉ ⲟⲩⲙⲏϣ ϫⲟⲥ ϫⲉ ⲁϥⲙⲟⲩ.
27 Ṣùgbọ́n Jesu fà á lọ́wọ́, ó sì ràn án lọ́wọ́ láti dúró lórí ẹsẹ̀ rẹ̀. Ó dìde dúró.
ⲕ̅ⲍ̅Ⲓⲏ̅ⲥ̅ ⲇⲉ ⲁϥ⳿ⲁⲙⲟⲛⲓ ⳿ⲛⲧⲉϥϫⲓϫ ⲁϥⲧⲟⲩⲛⲟⲥϥ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥⲧⲱⲛϥ.
28 Nígbà tí ó sì wọ ilé, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bi í léèrè níkọ̀kọ̀ wí pé, “Èéṣe tí àwa kò fi lè lé e jáde?”
ⲕ̅ⲏ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁϥϣⲉⲛⲁϥ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉⲡⲉϥⲏⲓ ⳿ⲁ ⲛⲉϥⲙⲁⲑⲏⲧⲏⲥ ⲇⲉ ϣⲉⲛϥ ⲥⲁ⳿ⲡⲥⲁ ϫⲉ ⲉⲑⲃⲉⲟⲩ ⳿ⲁⲛⲟⲛ ⳿ⲙⲡⲉⲛ⳿ϣϫⲉⲙϫⲟⲙ ⳿ⲛϩⲓⲧϥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ.
29 Ó sì wí fún wọn pé, “Irú èyí kò le ti ipa ohun kan jáde, bí kò ṣe nípa àdúrà.”
ⲕ̅ⲑ̅ⲟⲩⲟϩ ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲱⲟⲩ ϫⲉ ⲡⲁⲓⲅⲉⲛⲟⲥ ⳿ⲙⲙⲟⲛ⳿ϣϫⲟⲙ ⳿ⲛⲧⲉϥ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⳿ϩⲗⲓ ⳿ⲉⲃⲏⲗ ϧⲉⲛ ⲟⲩⲡⲣⲟⲥⲉⲩⲭⲏ ⲛⲉⲙ ⲟⲩⲛⲏⲥⲧⲓ⳿ⲁ.
30 Wọ́n sì kúrò níbẹ̀, wọ́n gba Galili kọjá. Níbẹ̀ ni Jesu ti gbìyànjú láti yẹra kí ó bá à lè wà pẹ̀lú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, kí ó lè ráàyè kọ́ wọn lẹ́kọ̀ọ́ sí i.
ⲗ̅ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉⲧⲁϥ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲙⲙⲁⲩ ⲛⲁϥⲥⲓⲛⲓ⳿ⲱⲟⲩ ⲡⲉ ⳿ⲉⲃⲟⲗϩⲓⲧⲉⲛ ϯⲄⲁⲗⲓⲗⲉ⳿ⲁ ⲟⲩⲟϩ ⲛⲁϥⲟⲩⲱϣ ⲁⲛ ⲡⲉ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲧⲉ ⳿ϩⲗⲓ ⳿ⲉⲙⲓ.
31 Nítorí ó kọ́ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó sì wí fun wọn pe, “A ó fi Ọmọ Ènìyàn lé àwọn ènìyàn lọ́wọ́, wọn ó sì pa á, lẹ́yìn ìgbà tí a bá sì pa á tan yóò jíǹde ní ọjọ́ kẹta.”
ⲗ̅ⲁ̅ⲛⲁϥϯ⳿ⲥⲃⲱ ⲅⲁⲣ ⲡⲉ ⳿ⲛⲛⲉϥⲙⲁⲑⲏⲧⲏⲥ ⲟⲩⲟϩ ⲛⲁϥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⲛⲱⲟⲩ ϫⲉ Ⲡ̇ϣⲏⲣⲓ ⳿ⲙⲪ̇ⲣⲱⲙⲓ ⲥⲉⲛⲁⲧⲏⲓϥ ⳿ⲉ⳿ϧⲣⲏⲓ ⳿⳿ⲉⲛⲉⲛϫⲓϫ ⳿ⲛⲛⲓⲣⲱⲙⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲥⲉⲛⲁϧⲟⲑⲃⲉϥ ⲙⲉⲛⲉⲛⲥⲁ ⲅ̅ ⳿ⲛ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⳿ϥⲛⲁⲧⲱⲛϥ.
32 Ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ náà kò yé wọn, ẹ̀rù sì bà wọ́n láti béèrè lọ́wọ́ rẹ̀, ìtumọ̀ ohun tí ó sọ náà.
ⲗ̅ⲃ̅⳿ⲛⲑⲱⲟⲩ ⲇⲉ ⲛⲁⲩⲟⲓ ⳿ⲛⲁⲧⲉⲙⲓ ⳿ⲉⲡⲓⲥⲁϫⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲛⲁⲩⲉⲣϩⲟϯ ⳿ⲉϣⲉⲛϥ ⲡⲉ.
33 Wọ́n dé sí Kapernaumu. Lẹ́yìn tí wọ́n sinmi tán nínú ilé tí wọ́n wọ̀, Jesu béèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Kí ni ohun tí ẹ́ ń bá ara yín jiyàn lé lórí?”
ⲗ̅ⲅ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁϥ⳿ⲓ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉⲔⲁⲫⲁⲣⲛⲁⲟⲩⲙ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉⲧⲁϥ⳿ⲓ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉⲡⲓⲏⲓ ⲛⲁϥϣⲓⲛⲓ ⳿ⲙⲙⲱⲟⲩ ϫⲉ ⲟⲩ ⳿ⲉⲛⲁⲣⲉⲧⲉⲛⲙⲟⲕⲙⲉⲕ ⳿ⲉⲣⲟϥ ϩⲓ ⳿ⲫⲙⲱⲓⲧ.
34 Ṣùgbọ́n wọ́n dákẹ́; nítorí wọn ti ń bá ara wọn jiyàn pé, ta ni ẹni tí ó pọ̀jù?
ⲗ̅ⲇ̅⳿ⲛⲑⲱⲟⲩ ⲇⲉ ⲛⲁⲩⲭⲱ ⳿ⲛⲣⲱⲟⲩ ⲛⲁⲩⲥⲁϫⲓ ⲅⲁⲣ ⲡⲉ ⲛⲉⲙ ⳿ⲛⲛⲟⲩ⳿ⲉⲣⲏⲟⲩ ϩⲓ ⳿ⲫⲙⲱⲓⲧ ϫⲉ ⲛⲓⲙ ⳿ⲙⲙⲱⲟⲩ ⲡⲉ ⲡⲓⲛⲓϣϯ.
35 Ó jókòó, ó sì pè àwọn méjìlá náà, ó sọ fún wọn pé, “Bí ẹnikẹ́ni bá fẹ́ ṣe ẹni ìṣáájú, òun ni yóò ṣe ẹni ìkẹyìn gbogbo wọn. Ó ní láti jẹ́ ìránṣẹ́ gbogbo ènìyàn.”
ⲗ̅ⲉ̅ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉⲧⲁϥϩⲉⲙⲥⲓ ⲁϥⲙⲟⲩϯ ⳿ⲉⲡⲓ ⲓ̅ⲃ̅ ⲟⲩⲟϩ ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲱⲟⲩ ϫⲉ ⲫⲏⲉⲑⲟⲩⲱϣ ⳿ⲉⲉⲣϩⲟⲩⲓⲧ ⲉϥ⳿ⲉⲉⲣϧⲁ⳿ⲉ ⳿ⲛⲟⲩⲟⲛ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲛⲉⲙ ⲇⲓ⳿ⲁⲕⲱⲛ ⳿ⲛⲟⲩⲟⲛ ⲛⲓⲃⲉⲛ.
36 Ó sì mú ọmọ kékeré kan, ó fi sáàárín wọn, nígbà tí ó sì gbé e sí apá rẹ̀, ó wí fún wọn pé,
ⲗ̅ⲋ̅ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉⲧⲁϥϭⲓ ⳿ⲛⲟⲩ⳿ⲁⲗⲟⲩ ⲁϥⲧⲁϩⲟϥ ⳿ⲉⲣⲁⲧϥ ϧⲉⲛ ⲧⲟⲩⲙⲏϯ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉⲧⲁϥ⳿ⲁⲙⲟⲛⲓ ⳿ⲙⲙⲟϥ ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲱⲟⲩ.
37 “Ẹnikẹ́ni tí ó bá tẹ́wọ́gbà ọmọ kékeré bí èyí ní orúkọ mi, òun gbà mí. Ẹnikẹ́ni tí ó bá sì gbà mi, ó gba Baba mi, tí ó rán mi.”
ⲗ̅ⲍ̅ϫⲉ ⲫⲏⲉⲑⲛⲁϣⲉⲡ ⲟⲩⲁⲓ ⳿ⲛⲛⲁⲓ⳿ⲁⲗⲱⲟⲩ⳿ⲓ ⳿ⲙⲡⲁⲓⲣⲏϯ ⳿ⲉⲡⲁⲣⲁⲛ ⳿ⲁⲛⲟⲕ ⲡⲉⲧⲉϥϣⲱⲡ ⳿ⲙⲙⲟⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲫⲏⲉⲧϣⲱⲡ ⳿ⲙⲙⲟⲓ ⳿ⲁⲛⲟⲕ ⲁⲛ ⲡⲉⲧⲉϥϣⲱⲡ ⳿ⲙⲙⲟⲓ ⲁⲗⲗⲁ ⲁϥϣⲱⲡ ⳿ⲙⲫⲏ⳿ⲉⲧⲁϥⲧⲁⲟⲩⲟⲓ.
38 Ọ̀kan nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, Johanu sọ fún un ní ọjọ́ kan pé, “Olùkọ́, àwa rí ọkùnrin kan, tí ń fi orúkọ rẹ̀ lé àwọn ẹ̀mí àìmọ́ jáde, ṣùgbọ́n a sọ fún un pé kò gbọdọ̀ ṣe bẹ́ẹ̀ mọ́, nítorí kì í ṣe ọ̀kan nínú wa.”
ⲗ̅ⲏ̅ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲁϥ ⳿ⲛϫⲉ Ⲓⲱⲁⲛⲛⲏⲥ ϫⲉ ⳿ⲫⲣⲉϥϯ⳿ⲥⲃⲱ ⲁⲛⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲟⲩⲁⲓ ⲉϥϩⲓ ⲇⲉⲙⲱⲛ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲡⲉⲕⲣⲁⲛ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲛⲧⲁϩⲛⲟ ⳿ⲙⲙⲟϥ ϫⲉ ⳿ⲛ⳿ϥⲟⲩⲉϩ ⳿ⲛⲥⲱⲛ ⲁⲛ.
39 Jesu sì sọ fún un pé, “Má ṣe dá irú ènìyàn bẹ́ẹ̀ dúró, nítorí kò sí ẹnìkan ti ó fi orúkọ mi ṣe iṣẹ́ ìyanu tí yóò tún lè máa sọ ohun búburú nípa mi.
ⲗ̅ⲑ̅Ⲓⲏ̅ⲥ̅ ⲇⲉ ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲁϥ ϫⲉ ⳿ⲙⲡⲉⲣⲧⲁϩⲛⲟ ⳿ⲙⲙⲟϥ ⳿ⲙⲙⲟⲛ ⳿ϩⲗⲓ ⲅⲁⲣ ⲫⲏⲉⲑⲛⲁ⳿⳿ⲓⲣⲓ ⳿ⲛⲟⲩϫⲟⲙ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⲡⲁⲣⲁⲛ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲧⲉϥϫⲉⲙϫⲟⲙ ⳿ⲛⲭⲱⲗⲉⲙ ⳿ⲉⲥⲁϫⲓ ⲉϥϩⲱⲟⲩ ϧⲁⲣⲟⲓ.
40 Nítorí ẹni tí kò bá kọ ojú ìjà sí wa, ó wà ní ìhà tiwa.
ⲙ̅ⲫⲏ ⲅⲁⲣ ⳿ⲉⲧⲉ ⳿ⲛ⳿ϥϯⲟⲩⲃⲏⲛ ⲁⲛ ⲁϥϯ ⳿ⲉϫⲱⲛ.
41 Lóòótọ́ ni mo sọ fún ún yín bí ẹnikẹ́ni bá fún un yín ní ife omi kan nítorí pé ẹ jẹ́ ti Kristi, dájúdájú ẹni náà kì yóò sọ èrè rẹ̀ nù bí ó ti wù kí ó rí.
ⲙ̅ⲁ̅ⲫⲏ ⲅⲁⲣ ⲉⲑⲛⲁ⳿ⲧⲥⲉ ⲑⲏⲛⲟⲩ ⳿ⲛⲟⲩ⳿ⲁⲫⲟⲧ ⳿ⲙⲙⲱⲟⲩ ϧⲉⲛ ⲡⲁⲣⲁⲛ ϫⲉ ⳿ⲛⲑⲱⲧⲉⲛ ⲛⲁ Ⲡⲭ̅ⲥ̅ ⳿ⲁⲙⲏⲛ ϯϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⲛⲱⲧⲉⲛ ϫⲉ ⳿ⲛⲛⲉϥⲧⲁⲕⲟ ⳿ⲛϫⲉ ⲡⲉϥⲃⲉⲭⲉ.
42 “Ṣùgbọ́n ti ẹnikẹ́ni bá mú ọ̀kan nínú àwọn ọmọ kékeré wọ̀nyí tí ó gbà mí gbọ́ ṣìnà nínú ìgbàgbọ́ rẹ́, ó sàn fún un kí a so òkúta ńlá mọ́ ọn ni ọ̀run, kí a sì sọ ọ́ sínú òkun.
ⲙ̅ⲃ̅ⲟⲩⲟϩ ⲫⲏⲉⲑⲛⲁⲉⲣ⳿ⲥⲕⲁⲛⲇⲁⲗⲓⲍⲉⲥⲑⲉ ⳿ⲛⲟⲩⲁⲓ ⳿ⲛⲛⲁⲓⲕⲟⲩϫⲓ ⲉⲑⲛⲁϩϯ ⳿ⲉⲣⲟⲓ ⲛⲁⲛⲉⲥ ⲛⲁϥ ⲙⲁⲗⲗⲟⲛ ⳿ⲉⲉϣ ⲟⲩ⳿ⲱⲛⲓ ⳿ⲙⲙⲟⲩⲗⲟⲛ ⳿ⲉϧⲏⲧϥ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲧⲟⲩϩⲓⲧϥ ⳿ⲉ⳿ⲫⲓⲟⲙ.
43 Bí ọwọ́ rẹ bá sì mú ọ kọsẹ̀, gé e sọnù, ó sàn fún ọ kí o ṣe akéwọ́ lọ sí ibi ìyè, ju kí o ní ọwọ́ méjèèjì, kí o lọ sí ọ̀run àpáàdì, sínú iná àjóòkú. (Geenna )
ⲙ̅ⲅ̅ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉϣⲱⲡ ⳿ⲛⲧⲉ ⲧⲉⲕϫⲓϫ ⲉⲣ⳿ⲥⲕⲁⲛⲇⲁⲗⲓⲍⲉⲥⲑⲉ ⳿ⲙⲙⲟⲕ ϫⲟϫⲥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲛⲁⲛⲉⲥ ⲅⲁⲣ ⲛⲁⲕ ⳿ⲛⲧⲉⲕ⳿ⲓ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉⲡⲓⲱⲛϧ ⲉⲕⲟⲓ ⳿ⲛϫⲁϭⲏ ⲓⲉ ⳿ⲉⲣⲉ ϫⲓϫ ⲃ̅ϯ ⳿ⲉⲣⲟⲕ ⳿ⲛⲧⲉⲕϣⲉ ⳿ⲉϯⲅⲉⲉⲛⲛⲁ ⳿ⲉⲡⲓ⳿ⲭⲣⲱⲙ ⳿ⲛⲁⲧϭⲉⲛⲟ. (Geenna )
ⲙ̅ⲇ̅ⲡⲓⲙⲁ ⳿ⲉⲧⲉ ⳿ⲙⲡⲁⲣⲉ ⲡⲟⲩϥⲉⲛⲧ ⲙⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲡⲟⲩ⳿ⲭⲣⲱⲙ ⳿ⲙⲡⲁϥϭⲉⲛⲟ.
45 Bí ẹsẹ̀ rẹ bá sì mú ọ kọsẹ̀, gé é sọnù, ó sàn kí ó di akesẹ̀, kí o sì gbé títí ayé àìnípẹ̀kun ju kí o ní ẹsẹ̀ méjì tí ó gbé ọ lọ sí ọ̀run àpáàdì. (Geenna )
ⲙ̅ⲉ̅ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉϣⲱⲡ ⳿ⲛⲧⲉ ⲧⲉⲕϭⲁⲗⲟϫ ⲉⲣ⳿ⲥⲕⲁⲛⲇⲁⲗⲓⲍⲉⲥⲑⲉ ⳿ⲙⲙⲟⲕ ϫⲟϫⲥ ϩⲓⲧⲥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲛⲁⲛⲉⲥ ⲛⲁⲕ ⳿ⲛⲧⲉⲕ⳿ⲓ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉⲡⲓⲱⲛϧ ⲉⲕⲟⲓ ⳿ⲛϭⲁⲗⲉ ⳿⳿ⲉϩⲟⲧⲉ ⳿ⲉⲣⲉ ⲟⲩⲟⲛ ϭⲁⲗⲟϫ ⳿ⲥⲛⲟⲩϯ ⳿ⲉⲣⲟⲕ ⳿ⲛⲥⲉϩⲓⲧⲕ ⳿ⲉϯⲅⲉⲉⲛⲛⲁ. (Geenna )
ⲙ̅ⲋ̅ⲡⲓⲙⲁ ⳿ⲉⲧⲉ ⳿ⲙⲡⲁⲣⲉ ⲡⲟⲩϥⲉⲛⲧ ⲙⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲡⲟⲩ⳿ⲭⲣⲱⲙ ⳿ⲙⲡⲁϥϭⲉⲛⲟ.
47 Bí ojú rẹ bá sì mú ọ kọsẹ̀, yọ ọ́ sọnù, ó sàn kí o wọ ìjọba Ọlọ́run pẹ̀lú ojú kan ju kí ó ní ojú méjì kí ó sì lọ sínú iná ọ̀run àpáàdì. (Geenna )
ⲙ̅ⲍ̅ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉϣⲱⲡ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲉⲕⲃⲁⲗ ⲉⲣ⳿ⲥⲕⲁⲛⲇⲁⲗⲓⲍⲉⲥⲑⲉ ⳿ⲙⲙⲟⲕ ⲫⲟⲣⲕϥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲛⲁⲛⲉⲥ ⲛⲁⲕ ⳿ⲛⲧⲉⲕ⳿ⲓ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉϯⲙⲉⲧⲟⲩⲣⲟ ⳿ⲛⲧⲉ Ⲫϯ ⳿ⲉⲟⲩⲃⲁⲗ ⳿ⲙⲙⲁⲩⲁⲧϥ ⳿ⲉⲧⲉⲣⲟⲕ ⳿⳿ⲉϩⲟⲧⲉ ⳿ⲉⲟⲩⲟⲛ ⲃⲁⲗ ⲃ̅ ⳿ⲙⲙⲟⲕ ⳿ⲛⲥⲉϩⲓⲧⲕ ⳿ⲉϯⲅⲉⲉⲛⲛⲁ. (Geenna )
48 Níbi ti “‘kòkòrò wọn kì í kú, tí iná kì í sì í kú.’
ⲙ̅ⲏ̅ⲡⲓⲙⲁ ⳿ⲉⲧⲉ ⳿ⲙⲡⲁⲣⲉ ⲡⲟⲩϥⲉⲛⲧ ⲙⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲡⲟⲩ⳿ⲭⲣⲱⲙ ⳿ⲙⲡⲁϥϭⲉⲛⲟ.
49 Níbẹ̀ ni a ó ti fi iná dán ẹnìkọ̀ọ̀kan wò.
ⲙ̅ⲑ̅ⲟⲩⲟⲛ ⲅⲁⲣ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⳿ⲉϣⲁⲩⲙⲟⲗϩϥ ⳿ⲙⲡⲓ⳿ⲭⲣⲱⲙ ⲟⲩⲟϩ ϣⲱⲧ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⳿ⲉϣⲁⲩⲙⲟⲩⲗϩϥ ϧⲉⲛ ⲡⲓ⳿ϩⲙⲟⲩ.
50 “Iyọ̀ dára, ṣùgbọ́n tí ó bá sọ adùn rẹ̀ nù, báwo ni ẹ ṣè lè padà mú un dùn? Ẹ ni iyọ̀ nínú ara yín, ki ẹ sì máa gbé ní àlàáfíà pẹ̀lú ara yín.”
ⲛ̅ⲛⲁⲛⲉ ⲡⲓ⳿ϩⲙⲟⲩ ⳿ⲉϣⲱⲡ ⲇⲉ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲓ⳿ϩⲙⲟⲩ ⲉⲣⲁⲧ⳿ϩⲙⲟⲩ ⳿ⲉϣⲁⲩⲙⲟⲗϩϥ ϧⲉⲛ ⲟⲩ ⲙⲁⲣⲉ ⳿ϩⲙⲟⲩ ϣⲱⲡⲓ ϧⲉⲛ ⲑⲏⲛⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲁⲣⲓϩⲓⲣⲏⲛⲏ ϧⲉⲛ ⲛⲉⲧⲉⲛ⳿ⲉⲣⲏⲟⲩ.