< Mark 7 >
1 Àwọn Farisi sì péjọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, àti àwọn kan nínú àwọn akọ̀wé, tí ó wá láti Jerusalẹmu,
Bu qaƣda, Pǝrisiylǝr wǝ Tǝwrat ustazliridin bǝziliri Yerusalemdin kelip uning aldiƣa yiƣildi;
2 wọ́n sì ṣe àkíyèsí wí pé díẹ̀ nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Jesu ń fi ọwọ́ àìmọ́ jẹun, èyí yìí ni wẹ ọwọ́.
xu Pǝrisiylǝr wǝ Tǝwrat ustazliri uning muhlisliridin bǝzilirining tamaⱪni ⱪolini yumay, yǝni «napak» ⱨalda yǝwatⱪanliⱪini kɵrüp, uningdin: — Muhlisliring nemixⱪa ata-bowilirimizning ǝn’ǝnilirigǝ riayǝ ⱪilmay, bǝlki yuyulmiƣan ⱪolliri bilǝn tamaⱪ yǝydu? — dǝp soraxti (qünki Pǝrisiylǝr wǝ pütün Yǝⱨudiylar ata-bowiliri tǝripidin ⱪaldurulƣan ǝn’ǝnini qing tutⱪaqⱪa, awwal ⱪollirini ǝstayidilliⱪ bilǝn yumisa, tamaⱪ yemǝydu. Xuningdǝk bazardin ⱪaytip kǝlgǝndimu, ular ⱪol yumay birnǝrsǝ yemǝydu. Uningdin baxⱪa, piyalǝ-ⱪǝdǝⱨ, das-qɵgün wǝ mis ⱪaqilar wǝ diwanlarni yuyux toƣrisida tapxurulƣan nurƣunliƣan ǝn’ǝnilǝrdimu qing turidu).
3 (Àwọn Farisi, àti gbogbo àwọn Júù, bí wọ́n kò bá wẹ ọwọ́ wọn gidigidi, wọn kì í jẹun nítorí wọ́n ti pa òfin àtọwọ́dọ́wọ́ àwọn àgbà mọ́.
4 Nígbà tí wọ́n bá sì ti ọjà dé sílé, wọn kò gbọdọ̀ fi ọwọ́ kan oúnjẹ àfi tí wọ́n bá bu omi wẹ ara wọn. Èyí sì jẹ́ ọ̀kan nínú ogunlọ́gọ̀ àpẹẹrẹ òfin àti ìlànà tí wọ́n ti dì mú fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún sẹ́yìn, bí i fífọ kọ́ọ̀bù, àwọn ìkòkò, àti kẹ́tù.)
5 Nítorí èyí àwọn Farisi àti àwọn olùkọ́ òfin béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Èéṣe tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ kò tẹ̀lé àwọn òfin àtọwọ́dọ́wọ́ àwọn àgbà nítorí wọ́n fi ọwọ́ àìmọ́ jẹun?”
6 Jesu dá wọn lóhùn wí pé, “Ẹyin àgàbàgebè yìí, òtítọ́ ni wòlíì Isaiah ń sọtẹ́lẹ̀ nípa tí ẹ̀yin àgàbàgebè, bí a ti kọ ọ́ pé: “‘Àwọn ènìyàn wọ̀nyí fi ẹnu wọn bu ọlá fún mi ṣùgbọ́n ọkàn wọn jìnà sí mi.
U ularƣa jawab berip mundaⱪ dedi: — Yǝxaya pǝyƣǝmbǝr silǝr sahtipǝzlǝr toƣranglarda aldin’ala toptoƣra bexarǝt bǝrgǝn! [uning] yazmisida pütülgǝndǝk: — «Muxu hǝlⱪ aƣzida Meni ⱨɵrmǝtligini bilǝn, Biraⱪ ⱪǝlbi Mǝndin yiraⱪ;
7 Ìsìn wọn jẹ́ lásán, ìkọ́ni wọ́n jẹ́ kìkìdá òfin tí àwọn ènìyàn fi ń kọ́ni.’
Ular Manga biⱨudǝ ibadǝt ⱪilidu. Ularning ɵgǝtkǝn tǝlimliri pǝⱪǝt insanlardin qiⱪⱪan pǝtiwalarla, halas».
8 Nítorí tí ẹ̀yin fi òfin Ọlọ́run sí apá kan, ẹ̀yin ń tẹ̀lé àṣà àwọn ènìyàn.”
Qünki silǝr Hudaning ǝmrini taxlap ⱪoyup, insanlarning ǝn’ǝnisini qing tutiwalidikǝnsilǝr — das-qɵgün, piyalǝ-ⱪǝdǝⱨlǝrni yuyux wǝ xuningƣa ohxap ketidiƣan nurƣan baxⱪa ixlarni ǝn’ǝnǝ ⱪilip yürisilǝr.
9 Ó si wí fún wọn: “Ẹ̀yin sá à mọ̀ bí ẹ ti ń gbé òfin Ọlọ́run jù sẹ́yìn kí ẹ lè mú òfin tiyín ṣẹ.
U ularƣa yǝnǝ mundaⱪ dedi: — Silǝr ɵzliringlarning ǝn’ǝnisini qing tutimiz dǝp Hudaning ǝmrini ǝpqillik bilǝn bir qǝtkǝ ⱪayrip ⱪoydunglar!
10 Mose fún un yín ní òfin yìí láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run pé, ‘Bọ̀wọ̀ fún baba òun ìyá rẹ.’ Ó tún sọ pé, ‘Ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ̀rọ̀ aburú sí baba tàbí ìyá rẹ̀ ní láti kú ni.’
Qünki Musa [pǝyƣǝmbǝr]: «Ata-anangni ⱨɵrmǝt ⱪil» wǝ «Atisi yaki anisini ⱨaⱪarǝtligǝnlǝr ɵlümgǝ mǝⱨkum ⱪilinsun» dǝp ǝmr ⱪilƣan.
11 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin wá sọ pé ó dára bákan náà fún ọkùnrin kan bí kò bá tilẹ̀ pèsè fún àìní àwọn òbí rẹ̀, ṣùgbọ́n kí o sọ fún wọn pé, ‘Ẹ má ṣe bínú baba tàbí ìyá mi, n kò lè ràn yín lọ́wọ́ nísinsin yìí,’ nítorí tí mo ti fi ẹ̀bùn tí ǹ bá fi fún un yín fún Ọlọ́run.
Lekin silǝr: — Birsi «Atisi yaki anisiƣa: — Mǝn silǝrgǝ yardǝm bǝrgüdǝk nǝrsilǝrni alliⱪaqan «ⱪurban ⱪilip» Hudaƣa atiwǝttim — desila,
12 Bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin kò si jẹ́ kí ó ṣe ohunkóhun fún baba tàbí ìyá rẹ̀ mọ́.
xu kixining ata-anisining ⱨalidin hǝwǝr elixƣa bolmaydu, dǝp ɵgitisilǝr.
13 Ẹ̀yin ń fi òfin àtọwọ́dọ́wọ́ tiyín tí ẹ fi lélẹ̀, sọ ọ̀rọ̀ Ọlọ́run di asán àti ọ̀pọ̀ irú nǹkan bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin ń ṣe.”
Xundaⱪ ⱪilip, silǝr [ǝwladliringlarƣa] tapxurƣan ǝn’ǝnǝnglǝrni dǝp Hudaning ǝmrini yoⱪⱪa qiⱪiriwǝttinglar, wǝ xuningƣa ohxax kɵp ixlarni ⱪilisilǝr.
14 Lẹ́yìn náà, Jesu pe ọ̀pọ̀ ènìyàn láti wá gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀. Ó sì wí fún wọn pé, “Gbogbo yín ẹ tẹ́tí sílẹ̀ kí ẹ sì jẹ́ kí èyí ó yé e yín.
Andin halayiⱪni yǝnǝ yeniƣa qaⱪirip, ularƣa: — Ⱨǝmminglar manga ⱪulaⱪ selinglar wǝ xuni qüxininglarki,
15 Kò sí ohunkóhun láti òde ènìyàn, tí ó wọ inú rẹ̀ lọ, tí ó lè sọ ọ́ di aláìmọ́, ṣùgbọ́n àwọn nǹkan tí ó ti inú rẹ jáde, àwọn wọ̀nyí ní ń sọ ènìyàn di aláìmọ́.”
insanning sirtidin iqigǝ kiridiƣan nǝrsilǝrning ⱨeqⱪandiⱪi uni napak ⱪilmaydu, bǝlki ɵz iqidin qiⱪidiƣan nǝrsilǝr bolsa, ular insanni napak ⱪilidu.
Angliƣudǝk ⱪuliⱪi barlar buni anglisun! — dedi.
17 Nígbà tí Jesu sì wọ inú ilé kan lọ, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn tẹ̀lé é, wọ́n sì béèrè ìtumọ̀ àwọn òwe tí ó pa.
U halayiⱪtin ayrilip ɵygǝ kirgǝndǝ, muhlisliri uningdin bu tǝmsil ⱨǝⱪⱪidǝ soridi.
18 Jesu béèrè wí pé, “Àbí kò sí èyí tí ó yé yín nínú ọ̀rọ̀ náà? Ẹ̀yin kò rí i wí pé ohunkóhun tí ó wọ inú ènìyàn láti òde kò lè sọ ènìyàn di aláìmọ́?
U ularƣa: — Silǝrmu tehiqǝ qüxǝnmǝy yürüwatamsilǝr?! Sirttin insanning iqigǝ kiridiƣan ⱨǝrⱪandaⱪ nǝrsining uni napak ⱪilalmaydiƣanliⱪini tonup yǝtmǝywatmamsilǝr?
19 Nítorí tí kò lọ sínú ọkàn rẹ̀, ṣùgbọ́n sínú ara, a sì yà á jáde, a sì gbá gbogbo oúnjẹ dànù.” (Nípa sísọ èyí, Jesu fihàn pé gbogbo oúnjẹ jẹ́ “mímọ́.”)
[Sirttin kirgǝn nǝrsǝ] insanning ⱪǝlbigǝ ǝmǝs, axⱪaziniƣa kiridu, andin u yǝrdin tǝrǝt bolup taxlinidu, — dedi (u bu gǝpni deyix bilǝn, ⱨǝmmǝ yemǝkliklǝrni ⱨalal ⱪiliwǝtti).
20 Nígbà náà, ó fi kún un pé, “Èyí ti ó ti ọkàn ènìyàn jáde ni ń sọ ni di aláìmọ́.
U yǝnǝ sɵz ⱪilip mundaⱪ dedi: — Insanning iqidin qiⱪidiƣinila, insanni napak ⱪilidu.
21 Nítorí pé láti inú ọkàn ènìyàn ni àwọn èrò búburú wọ̀nyí ti ń jáde wá: àgbèrè, olè, ìpànìyàn, panṣágà,
Qünki xular — yaman niyǝtlǝr, zinahorluⱪ, jinsiy buzuⱪluⱪlar, ⱪatilliⱪ, oƣriliⱪ, aqkɵzlük, rǝzilliklǝr, aldamqiliⱪ, xǝⱨwaniyliⱪ, ⱨǝsǝthorluⱪ, til-aⱨanǝt, tǝkǝbburluⱪ wǝ ⱨamaⱪǝtliklǝr insanning iqidin, yǝni uning ⱪǝlbidin qiⱪidu
22 ọ̀kánjúwà, odì yíyàn, ìtànjẹ, ìmọ-tara-ẹni, ìlara, ọ̀rọ̀ ẹ̀yìn, ìgbéraga, òmùgọ̀.
23 Gbogbo àwọn nǹkan búburú wọ̀nyí ń tí inú wá, àwọn ló sì ń sọ yín di aláìmọ́.”
— bu rǝzil ixlarning ⱨǝmmisi insanning iqidin qiⱪip, ɵzini napak ⱪilidu.
24 Nígbà náà ni Jesu kúrò ní Galili, ó sí lọ sí agbègbè Tire àti Sidoni, ó sì gbìyànjú láti nìkan wà pẹ̀lú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ fún àkókò díẹ̀, ṣùgbọ́n eléyìí kò ṣe é ṣe, nítorí pé kò pẹ́ púpọ̀ tí ó wọ ìlú nígbà tí ìròyìn dídé rẹ̀ tàn káàkiri.
U ornidin turup u yǝrdin ayrilip, Tur wǝ Zidon ǝtrapidiki rayonlarƣa bardi wǝ bir ɵygǝ kirdi. Gǝrqǝ u buni ⱨeqkim bilmisun degǝn bolsimu, lekin yoxurup ⱪalalmidi.
25 Láìpẹ́, obìnrin kan tí ọmọbìnrin rẹ̀ ní ẹ̀mí àìmọ́ tọ̀ ọ́ wá, ó ti gbọ́ nípa Jesu, ó wá, ó sì wólẹ̀ lẹ́sẹ̀ Jesu.
Dǝrwǝⱪǝ, napak roⱨ qaplaxⱪan kiqik bir ⱪizning anisi uning toƣrisidiki hǝwǝrni angliƣan ⱨaman yetip kelip, uning ayiƣiƣa yiⱪildi
26 Giriki ní obìnrin náà, Siro-Fonisia ní orílẹ̀-èdè rẹ̀. Ó bẹ Jesu kí ó bá òun lé ẹ̀mí èṣù náà jáde lára ọmọbìnrin òun.
(ayal Yunanliⱪ bolup, Suriyǝ ɵlkisidiki Fǝnikiy millitidin idi). U uningdin ⱪizidin jinni ⱨǝydiwetixni ɵtündi.
27 Jesu sọ fún obìnrin yìí pé, “Ní àkọ́kọ́, ó yẹ kí a fi oúnjẹ tẹ́ àwọn ọmọ lọ́rùn ná. Nítorí kò tọ́ kí a mú oúnjẹ àwọn ọmọ fún àwọn ajá.”
Lekin Əysa uningƣa: — Aldi bilǝn balilar ⱪorsiⱪini toyƣuzsun; qünki balilarning nenini kiqik itlarƣa taxlap berix toƣra ǝmǝs, — dedi.
28 Obìnrin náà dáhùn wí pé, “Òótọ́ ni ọ̀rọ̀ yín Olúwa, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ ajá pàápàá a máa ní àǹfààní láti jẹ èérún oúnjẹ tí ó bá bọ́ sílẹ̀ láti orí tábìlì.”
Lekin u buningƣa jawabǝn: — Durus, i Rǝb, biraⱪ ⱨǝtta itlarmu üstǝl astida turup balilardin qüxkǝn nan uwaⱪlirini yǝydiƣu, — dedi.
29 “Ó sì wí fún un pé, nítorí ọ̀rọ̀ yìí, máa lọ, ẹ̀mí àìmọ́ náà ti jáde kúrò lára ọmọbìnrin rẹ.”
Əysa uningƣa: — Sening muxu sɵzüng tüpǝylidin yolungƣa ⱪayt, jin ⱪizingdin qiⱪip kǝtti, — dedi.
30 Nígbà tí ó padà dé ilé, ó bá ọmọbìnrin rẹ̀ ní ìdùbúlẹ̀ jẹ́jẹ́ lórí ibùsùn, ẹ̀mí àìmọ́ náà ti fi í sílẹ̀.
Ayal ɵyigǝ ⱪaytip kǝlgǝndǝ, mana ⱪiz kariwatta yatatti, jin uningdin qiⱪip kǝtkǝnidi.
31 Nígbà náà ni Jesu fi agbègbè Tire àti Sidoni sílẹ̀, ó wá si Òkun Galili láàrín agbègbè Dekapoli.
Əysa yǝnǝ Tur wǝ Zidon xǝⱨirining ǝtrapidiki rayonlardin qiⱪip, «On xǝⱨǝr» rayoni otturisidin ɵtüp, yǝnǝ Galiliyǝ dengiziƣa kǝldi.
32 Níbẹ̀ ọkùnrin kan tí kò lè sọ̀rọ̀ wá sí ọ̀dọ̀ Jesu, àwọn ènìyàn sì bẹ Jesu pé kí ó gbé ọwọ́ rẹ̀ lé e.
Halayiⱪ uning aldiƣa tili eƣir, gas bir adǝmni elip kelip, uning uqisiƣa ⱪolungni tǝgküzüp ⱪoysang, dǝp ɵtünüxti.
33 Jesu sì mú ọkùnrin náà kúrò láàrín ọ̀pọ̀ ènìyàn. Ó sì fi àwọn ìka rẹ̀ sí etí ọkùnrin náà, ó tu itọ́ ṣọ́wọ́. Ó sì fi kan ahọ́n rẹ̀.
U u adǝmni halayiⱪtin ayrip bir qǝtkǝ tartip, barmaⱪlirini uning ⱪulaⱪliriƣa tiⱪti, tükürüp, [barmiⱪini] uning tiliƣa tǝgküzdi.
34 Nígbà náà ni Jesu wòkè ọ̀run, ó sì mí kanlẹ̀, ó sì pàṣẹ wí pé, “Efata!” (èyí ni, “Ìwọ ṣí!”).
Andin u asmanƣa ⱪarap uⱨ tartip horsinƣandin keyin, u adǝmgǝ: «Əffata» (mǝnisi «eqil») dedi.
35 Lójúkan náà, etí rẹ̀ sì ṣí, okùn ahọ́n rẹ̀ sì tú, ó sì ń sọ̀rọ̀ ketekete.
U adǝmning ⱪulaⱪliri dǝrⱨal eqilip, tilimu eqilip rawan gǝp ⱪilixⱪa baxlidi.
36 Jesu pàṣẹ fún ọ̀pọ̀ ènìyàn tó wà níbẹ̀ pé kí wọn má ṣe tan ìròyìn náà ká. Ṣùgbọ́n bí ó ti ń pa wọ́n lẹ́nu mọ́ tó, náà ni wọ́n ń tan ìròyìn náà káàkiri tó.
Əysa ularƣa buni ⱨeqkimgǝ eytmasliⱪni tapilidi. Lekin ularƣa ⱨǝrⱪanqǝ tapiliƣan bolsimu, bu hǝwǝrni yǝnila xunqǝ kǝng tarⱪitiwǝtti.
37 Àwọn ènìyàn sì kún fún ìyanu, wọ́n wí pé, “Ó ṣe ohun gbogbo dáradára, Ó mú kí adití gbọ́rọ̀, odi sì sọ̀rọ̀.”
Halayiⱪ [bu ixⱪa] mutlǝⱪ ⱨǝyran ⱪelixip: — U ⱨǝmmǝ ixlarni ⱪaltis ⱪilidikǝn! Ⱨǝtta gaslarni anglaydiƣan, gaqilarni sɵzlǝydiƣan ⱪilidikǝn, — deyixti.