< Mark 13 >
1 Bí Jesu ti ń jáde láti inú tẹmpili ní ọjọ́ náà, ọ̀kan nínú ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sọ fún un pé, “Olùkọ́, wo ilé ńlá tí ó dára wọ̀nyí. Sì wo òkúta tí a ṣe lọ́ṣọ̀ọ́ lára àwọn ògiri ilé náà.”
Jisu Rangteenok nawa dokkhoom adi heliphante wasiit ih liita, “Nyootte, Sok uh! Arah nok loong nyia jong ah, tumthan milung miwaang ah!”
2 Jesu dáhùn pé, “Ìwọ rí ilé ńlá wọ̀nyí? Kì yóò sí òkúta kan tí a ó fi sílẹ̀ lórí èkejì tí a kì yóò wó lulẹ̀.”
Jisu ih ngaakbaatta, “An ih arah nok loong ah elong longwah tam et tup hu?” Arah nok abah saasiit erukdat eah, arah nok adoh jongteh tesiit taan uh tah dak tongka ang ah; loongtang rukdat ih ah.”
3 Bí Jesu si ti jókòó lórí òkè olifi tí ó kọjú sí tẹmpili, Peteru, Jakọbu, Johanu àti Anderu wà pẹ̀lú rẹ̀ níbẹ̀, wọ́n bi í léèrè ni ìkọ̀kọ̀ pé,
Rangteenok ka ni Jisu Olib kong ni tong adi, Pitar, Jeems, Joon nyia Endriu loong ah huchomui wang rumtaha.
4 “Sọ fún wa, nígbà wo ni nǹkan wọ̀nyí yóò ṣẹlẹ̀ sí tẹmpili náà? Kí ni yóò sì jẹ́ àmì nígbà tí gbogbo nǹkan wọ̀nyí yóò ṣẹ?”
“Erah loong ah maatok doh angte angla, seng suh baat kohe,” neng ih cheng rumta, “Erah loong ah saapoot ah echang ela ih jat suh tumjih ih jatthuk he, erah nep baat kohe.”
5 Jesu kìlọ̀ fún wọn pé, “Ẹ má ṣe jẹ́ kí ẹnikẹ́ni tàn yín.
Jisu ih baat rumta, “Naririh ih ban tong an, mih ih naktoom mokwaan han.
6 Nítorí pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ yóò wá ní orúkọ mi, wọn yóò wí pé, ‘Èmi ni Kristi,’ wọn yóò tan ọ̀pọ̀ ènìyàn jẹ.
Nga tiitbaatte mih hantek ih dong ah, ‘Jisu ah ngah’ ih chaangte nep dong ha! Eno neng ih hantek moong mokwaan ah.
7 Nígbà tí ẹ̀yin bá ń gbọ́ ìró ogun àti ìdágìrì ogun, kí ẹ̀yin má ṣe jáyà, nítorí irú nǹkan wọ̀nyí kò le ṣe kí ó má ṣẹlẹ̀, ṣùgbọ́n òpin náà kì í ṣe ìgbà yìí.
Sen ih haniik haloot nawa raamui tiit ephoop chochaat an, ang abah uh sen lasootsaam theng. Erah loong ah elang jaatjaat eah, enoothong erah suh rangkuh thoonla ih liijih tah angka.
8 Orílẹ̀-èdè yóò dìde sí orílẹ̀-èdè, àti ìjọba sí ìjọba ilẹ̀ yóò máa jì ní ibi púpọ̀. Ìyàn yóò sì wà níbi gbogbo. Gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni ìbẹ̀rẹ̀ ìpọ́njú tí ń bọ̀ níwájú.
Hasong rookwih nah neng neng rookmui arah je ah, deek akaan ah deek akaan loong damdoh rookmui ah. Rongrep nah hasatek nyi ramtek khamle totoh ang ah. Erah loong ah, noonuh nootup suh kaphang sat arah likhiik ih ang ah.
9 “Ṣùgbọ́n nígbà tí àwọn nǹkan wọ̀nyí bá bẹ̀rẹ̀ sí i ṣẹlẹ̀, ẹ kíyèsára! Nítorí ẹ̀yin yóò wà nínú ewu. Wọn yóò fà yín lọ ilé ẹjọ́ gbogbo. Wọn yóò fi ìyà jẹ yín nínú Sinagọgu wọn. Àwọn ènìyàn yóò fẹ̀sùn kàn yín níwájú àwọn baálẹ̀ àti níwájú àwọn ọba nítorí orúkọ mi, fún ẹ̀rí fún wọn.
“Sen teeteewah sensen ih naririh ih ban sok an. Sen loong ah khak hanno mat hoon nok nah siitwan han. Sen loong ah Jehudi rangsoomnok loong nah buh kaat han; nga thoidoh sen loong ah mih luungwang loong ngathong nah chap anno ruurang ese tiit ah baat an.
10 Nítorí pé ẹ gbọdọ̀ kọ́kọ́ wàásù ìyìnrere náà fún gbogbo orílẹ̀-èdè kí òpin tó dé.
Enoothong rangkuh thoon jaakhoh nah mongrep dowa mirep miraang suh Rangte tiitkhaap ah baat jaatjaat etheng.
11 Ṣùgbọ́n nígbà tí wọ́n bá ń fà yín lọ, tí wọ́n bá sì ń fi yín lé wọn lọ́wọ́, ẹ má ṣe ṣàníyàn ṣáájú ohun tí ẹ ó sọ. Ṣùgbọ́n ohun tí bá fi fún yín ní wákàtí náà, òun ni kí ẹ̀yin kí ó wí. Nítorí kì í ṣe ẹ̀yin ni ó ń wí, bí kò ṣe Ẹ̀mí Mímọ́.
Eno sen loong ah, maatok doh khak hanno mat hoon nok nah siitwan han doh tumjih jeng ang ih lasootsaam theng; saapoot thok ha doh an tumjih jeng thuk ho, erah jeng uh. Jengkhaap marah jeng uh erah an jeng tah angka ang ah; erah Esa Chiiala nawa jeng raaha.
12 “Arákùnrin yóò máa fi ẹ̀sùn kan arákùnrin rẹ̀, tí yóò sì yọrí sí ikú. Baba yóò máa ṣe ikú pa ọmọ rẹ̀. Àwọn ọmọ yóò máa dìtẹ̀ sí òbí wọn. Àní, àwọn ọmọ pẹ̀lú yóò máa ṣe ikú pa òbí wọn.
Mina loong ah soophoh ah soophoh ih jootkot mui rum ano tek haatmui ah eno hewah loong ah ih emamah heh sah loong tek haat ah. Heh sah loong ah ih henuh hewah damdoh miksuk mui rum ano tek haatmui rum ah.
13 Àwọn ènìyàn yóò kórìíra yín nítorí tí ẹ jẹ́ tèmi. Ṣùgbọ́n ẹni tó bá fi ara da ìyà títí dé òpin tí kò sì kọ̀ mí sílẹ̀ òun ni yóò rí ìgbàlà.
Nga tungthoidoh warep ih miksuk han. Enoothong o hethoon tuk ih ramram ih joh ah erah ba pui ah.
14 “Ṣùgbọ́n nígbà tí ẹ̀yin bá rí ìríra ìsọdahoro, tí ó dúró níbí tí kò yẹ (ẹnikẹ́ni tí ó bá kà á kí ó yé e), nígbà náà ni kí àwọn tí ń bẹ ni Judea sálọ sí orí òkè.
“Sen ih ‘Rapne Echoojih’ jaatrep jen thet haatte ah japtup et an, marah doh lah angtheng angta erah doh ang ah.” (Arah wette suh: esamjat etheng tumjih men et ha rah ah!) “Eno Judia nawa miloong ah kong akaan ko ih toonsoonjih jaatjaat ang ah.
15 Kí ẹni ti ń bẹ lórí ilé má ṣe sọ̀kalẹ̀ lọ sínú ilé, bẹ́ẹ̀ ni kí ó má sì ṣe wọ inú rẹ̀, láti mú ohunkóhun jáde nínú ilé rẹ̀.
O bah uh nok khoni angte rah ih nokmong nawa hukkhaak toon suh lajaatjaat saathaam kaat jih ang ah.
16 Kí ẹni tí ó wà lóko má ṣe padà sẹ́yìn láti wá mú aṣọ rẹ̀.
O mina phek nah ang ah, heh nok nawa nyuh akhat toon suh lajaatjaat ngaak wangjih.
17 Ègbé ní fún àwọn tí ó lóyún, àti fún obìnrin tí ń fún ọ́mọ lọ́mú ní ọjọ́ wọ̀nyí.
Erah tokdoh tumthan ethih ang ah sah wokte nyi khobaang nuh loong ah raang ih ah!
18 Kí ẹ sì máa gbàdúrà pé èyí ṣẹlẹ̀ ní àkókò òtútù.
Rangte rangsoom an erah rangwuung ah hahook doh nak toom ang ah!
19 Nítorí ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì yóò jẹ́ àkókò ìpọ́njú, irú èyí tí kò ì ṣẹlẹ̀ láti ìbẹ̀rẹ̀ ẹ̀dá Ọlọ́run. Irú rẹ̀ kò sì ni ṣẹlẹ̀ mọ́.
Tumeah erah tokdoh chamchojih rah, Rangte ih hasong phangdong siitta dowa ih amatuk ih o uh lathaak chamka rah cham ah. Adoleh erah likhiikkhiik tumsa doh uh takah we angka.
20 “Àfi tí Olúwa bá gé àkókò ìjìyà náà kúrú, ẹyọ ẹ̀mí kan ní ayé kì yóò là. Ṣùgbọ́n nítorí àwọn tí Ọlọ́run yàn, ni yóò ṣe dín àwọn ọjọ́ náà kù.
Enoothong Teesu ih erah saakaan rookweh ah ethoosiit thong et koha, lah angta bah, o uh ething tatong thengta. Heh ih danjeeta mina loong suh raamwe ih erah saakaan ah thoosiitta.
21 Nígbà náà, bí ẹnikẹ́ni bá sọ fún un yín pé, ‘Ẹ wò ó, Kristi wa níbi yìí!’ tàbí, sọ fún un yín pé, ‘Ẹ wò ó, ó wà lọ́hùn ún nì!’ Ẹ má ṣe gbà wọ́n gbọ́.
“Eno, o ih bah uh amah mok ih baat han, ‘Sok an, Kristo aani,’ adoleh mararah ih baat han ‘Kristo bah therah ni thong!—erah sen ih lahanpi theng.
22 Nítorí àwọn èké Kristi àti àwọn wòlíì èké ni yóò wá, wọn yóò sì fi iṣẹ́ ìyanu tí yóò tan ènìyàn jẹ hàn. Bí ó bá ṣe é ṣe, wọn yóò tan àwọn àyànfẹ́ pàápàá jẹ.
Tumeah emoong Kristo nyia emoong khowah loong ephoop dong ha. Neng ih epaatjaajih nyia mih lungwaang theng ephoop noisok rum ah, jen lang abah Rangte ih danjeeta mina loong ah nep mokwaan suh ah.
23 Nítorí náà, ẹ ṣọ́ra. Mo ti kìlọ̀ fún un yín ṣáájú tó!
Sen teeteewah naririh ih ban sok an! Ngah ih jaatrep tiit ah rangwuung saakaan maang thok ra ngakhoni banbaat rumhala!
24 “Ṣùgbọ́n ni ọjọ́ wọ̀nyí lẹ́yìn ìpọ́njú tí mo sọ yìí, “‘oòrùn yóò ṣókùnkùn, òṣùpá kò ní tan ìmọ́lẹ̀ rẹ̀.
“Erah chamnaang loong saakaan lidoh rangsa ah emoon eah, laaphiing ah takah kaang phaakka ang ah,
25 Àwọn ìràwọ̀ pẹ̀lú yóò já lulẹ̀ láti ojú ọ̀run, àti agbára tí ń bẹ ní ọ̀run ni a ó sì mì tìtì.’
rang nawa riksih loong ah datti ih raaha, rangkho nawa rangsa laaphiing loong ah dumdan eah.
26 “Nígbà náà ni gbogbo ayé yóò sì rí i tí èmi Ọmọ Ènìyàn yóò máa bọ̀ wá láti inú àwọsánmọ̀ pẹ̀lú agbára àti ògo ńlá.
Erah lidoh, Mina Sah ah jiingmuung khuinah, chaan aphaan pan ih phaakjaaja ih dong raaha.
27 Nígbà náà ni yóò sì rán àwọn angẹli rẹ̀ láti kó àwọn àyànfẹ́ ní gbogbo ayé jọ láti orígun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin ayé láti ìkangun ayé títí dé ìkangun ọ̀run.
Eno rangsah loong ah hatoh rongbaji adoh daapkaat ah, heh ih danjeeta mina loong ah mongrep noongrepwih dowa lom khoonsiit rum ah.
28 “Nísinsin yìí, ẹ kọ́ òwe lára igi ọ̀pọ̀tọ́, nígbà tí ẹ̀ka rẹ bá ń yọ tuntun, tí ó bá sì ń rú ewé, èyí fihàn pé àkókò ẹ̀rùn ti dé.
“Puksak bang ih sen suh toom nyoot han. Heh demdem suh hephaak ah jang ano dongkom raaha eno helak ah pa, erah di sen ih jat han rangsoh thok hala eah.
29 Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́, nígbà tí ẹ ba ri àwọn ohun wọ̀nyí ti n ṣẹlẹ̀, kí ẹ mọ̀ pé ó súnmọ́ etílé tán, bi ìgbà tí ó wà lẹ́yìn ìlẹ̀kùn.
Erah likhiik ih, sen ih sen mik ih erah loong chikrok ah tup anno ba, hethoon saapoot ah haniik ih thok hala ih samthun an.
30 Lóòótọ́ ni mo wí fún un yín, ìran yìí kì yóò rékọjá títí a ó fi mú gbogbo nǹkan wọ̀nyí ṣẹ.
Banthun et an erah loong ah amah dowa mina thoontang maang matti rumka ngakhoh nah ang raaha.
31 Ọ̀run àti ayé yóò kọjá lọ, ṣùgbọ́n àwọn ọ̀rọ̀ mi dúró dájú títí ayé àìnípẹ̀kun.
Rang nyia hah bah ethoon eah, nga jengkhaap loong abah babah uh tathoonka.
32 “Ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí ó mọ ọjọ́ tàbí wákàtí tí nǹkan wọ̀nyí yóò ṣẹlẹ̀. Àwọn angẹli ọ̀run pàápàá kò mọ̀. Àní, èmi pẹ̀lú kò mọ̀ ọ́n, bí kò ṣe baba nìkan.
“O mina reh uh rangwuung saakaan ah tajatka, tum sa doh, maatok doh raaha eah—rangmong nawa Rangsah reh uh tajatka; heh Sah reh uh tajatka, heh Wah luulu ih ba jat ah.
33 Ẹ máa ṣọ́ra, ẹ dúró wámú, kí ẹ sì máa gbàdúrà, nítorí ẹ̀yin kò mọ ìgbà tí àkókò ná yóò dé.
Erah raang ih ban sok et an, nyia banban ih tong an, tumeah sen ih rangwuung saakaan ah tajatkan.
34 Ó dà bí ọkùnrin kan tí ó lọ sí ìrìnàjò tí ó jìnnà rere, ẹni tí ó fi ilé rẹ̀ sílẹ̀, tí ó sì fi àṣẹ fún àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀, àti iṣẹ́ tí ẹnìkọ̀ọ̀kan yóò ṣe, ó sì fi àṣẹ fún ẹni tó dúró lẹ́nu-ọ̀nà láti máa ṣọ́nà.
Erah langla changte wah ih heh laksuh loong wasiit wasiit suh heh nok nawa reeraang loong ah baat koh thiin rum ano heh ah haloot nah moongkhoom kah arah likhiik ang ah. Eno heh maang ngaakwang wang et ban sok thuk arah likhiik.
35 “Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́, ẹ̀yin pẹ̀lú ní láti máa fi ìrètí ṣọ́nà, nítorí pé ẹ kò mọ àkókò tí baálé ilé yóò dé. Bóyá ní ìrọ̀lẹ́ ni o, tàbí ní ọ̀gànjọ́ òru, tàbí nígbà tí àkùkọ máa ń kọ, tàbí ní òwúrọ̀.
Erah raang ih naririh ih ban sok an! Tumeah sen ih tajatkan nok changte wah ah maatok doh ngaakwang koja, rangja ko doh tam pheethungkham doh, tama rangkhano doh, adoleh rangsa dong doh wang koja.
36 Àti wí pé nígbà tí ó bá dé lójijì, kó má ṣe bá yín lójú oorun.
Heh baphuk ih raaha doh, sen emokjup ean rah nak toom kapjoh raahan.
37 Ohun tí mo wí fún un yín, mo wí fun gbogbo ènìyàn: ‘Ẹ máa ṣọ́nà!’”
Ngah ih sen loong suh baat rumhala rah, mirep suh baat hang: Banban ih tong an!”