< Mark 10 >

1 Nígbà náà, Jesu kúrò níbẹ̀, ó sì wá sí ẹkùn Judea níhà òkè odò Jordani. Àwọn ènìyàn sì tún tọ̀ ọ́ wá, bí i ìṣe rẹ̀, ó sì kọ́ wọn.
KAHCHU iiti otsi niiya, kahchu yuhchiklodesha Judea ti otaihchi Jordan natyechi: kahchu tane yinkhatyesha; kahchu tane ootanaun akehe kooh otye keeoach ahli taneghaotatyechoo.
2 Àwọn Farisi kan tọ̀ ọ́ wá, láti dán an wò. Wọ́n béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Ǹjẹ́ ó ha tọ̀nà fún ènìyàn láti kọ ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀?”
Kahchu Phariseene yechitestyetl kahchu taoontya yehti, Oochu la teze tatsiyue yechanaolohu aotezi? kikaotyehunooh.
3 Jesu béèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Kí ni Mose pàṣẹ fún un yín?”
Kahchu ateyatetlalon toowehchu yehtilon Tyeha kehe anaghehtya Moses?
4 Wọ́n dáhùn pé, “Mose yọ̀ǹda fún wa láti kọ ìwé ìkọ̀sílẹ̀ fún un, kí a sì fi sílẹ̀.”
Kahchu toowe ghati, Moses hatyeh kha syeklah takehnichatinklessi o-ochatihtyehi adusklesse, kahchu oonchatoohtyellu.
5 Ṣùgbọ́n Jesu dá wọn lóhùn, ó sì wí pé, “Nítorí líle àyà yín ni Mose fi kọ òfin yìí fun un yín.
Kahchu Jesus ateyatetlakahchu toowe yehti, Naghadzye natsut akehe ayi ihe naghatsi achateskleslon tidi sa.
6 Ṣùgbọ́n láti ìgbà tí ayé ti ṣẹ̀, Ọlọ́run dá wọn ní akọ àti abo.
Ahwole hatseto otsi tike ooli toh Nagha Tgha teze oola tsege chu.
7 Nítorí ìdí èyí, ọkùnrin yóò fi baba àti ìyá rẹ̀ sílẹ̀ yóò sì fi ara mọ́ aya rẹ̀.
Ayi otsi teze tatgha echeli to chu kahchu tatsiyue kah awoti;
8 Òun àti ìyàwó rẹ̀ yóò di ara kan náà. Nítorí náà, wọn kì í túnṣe méjì mọ́ bí kò ṣe ẹyọ ọ̀kan ṣoṣo.
Kahchu kooh chu onkeghatatye kootsun ehlatootyesi: atu otaihchi onkyeghatutyesi ahwole kootsun ehlatootyesi.
9 Nítorí náà ohun ti Ọlọ́run bá sọ dọ̀kan, ki ẹnikẹ́ni máa ṣe yà wọ́n.”
Oo ayi Nagha Tgha tsayaghehtichii, atuline inchake niyulel.
10 Lẹ́yìn náà, nígbà tí Jesu nìkan wà nínú ilé pẹ̀lú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, wọ́n tún béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ nípa ohun kan náà.
Kahchu nito kwa oota yaotatichne taoontya yehti kwaka inhligi tsi.
11 Jesu túbọ̀ ṣe àlàyé fún wọn pé, “Ẹnikẹ́ni tí ó bá kọ aya rẹ̀ sílẹ̀ tí ó bá sì fẹ́ ẹlòmíràn, irú ọkùnrin bẹ́ẹ̀ ṣe panṣágà sí obìnrin tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé níyàwó.
Kahchu toowe yehti, Ooline assine tatsiyue odehtyetine achune chu makahtueh akoochaile ate, soocha keoach.
12 Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́, bí obìnrin kan bá kọ ọkọ rẹ̀ sílẹ̀ tí ó sì fẹ́ ọkùnrin mìíràn, irú obìnrin bẹ́ẹ̀ ṣe panṣágà.”
Tsege chu tatsiyue odehtye, kahchu makahtueh achilai ate, soocha keoach.
13 Lẹ́yìn èyí, àwọn ènìyàn bẹ̀rẹ̀ sí í gbé àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ tọ Jesu wá kí ó lè súre fún wọn. Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ kígbe mọ́ àwọn tí ń gbé àwọn ọmọdé wọ̀nyí bọ̀ pé wọn kò gbọdọ̀ yọ Jesu lẹ́nu rárá.
Kahchu kiyananihtyi tsito yechihai, yekatootihi; yaotatichne yachuootatyech ayi naghanihtyisi ihe.
14 Ṣùgbọ́n nígbà tí Jesu rí ohun tí ó ń ṣẹlẹ̀, inú rẹ̀ kò dùn sí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀. Nítorí náà, ó sọ fún wọn pé, “Ẹ jẹ́ kí àwọn ọmọdé kékeré wá sọ́dọ̀ mi. Ẹ má ṣe dá wọn lẹ́kun nítorí pé irú wọn ni ìjọba Ọlọ́run.
Ahwole Jesus wa-ichi, ohtye atu minihtike ooghilelon, kahchu toowe yehti, Ghateh kooyasahlah tsito yechihai sachaghatutyeli, kahchu atu nanahahun: ayi ihe nao-oaizi Nagha Tgha kyeyih tsi.
15 Lóòótọ́ ni mo wí fún yín, ẹnikẹ́ni tí kò bá gba ìjọba Ọlọ́run bí ọmọ kékeré, kì yóò le è wọ inú rẹ̀.”
Kwa hli anaghaisii. Ooline atu niyatiooti Nagha Tgha kyeyih yechinekehchi atu Nagha Tgha kahchi koowoyezi.
16 Nígbà náà, Jesu gbé àwọn ọmọ náà lé ọwọ́ rẹ̀, ó gbé ọwọ́ lé orí wọn. Ó sì súre fún wọn.
Kahchu yakoone ihe niyatintyih, kahchu yakatihtich, kahchu oochu yachi indityesa.
17 Bí Jesu ti bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò rẹ, ọkùnrin kan sáré wá sọ́dọ̀ rẹ̀. Ó sì kúnlẹ̀, ó béèrè pé, “Olùkọ́ rere, kí ni èmi yóò ṣe láti jogún ìyè àìnípẹ̀kun?” (aiōnios g166)
Kahchu yitai tyesha atghunni kehchi, ehlaityi yuhchidesha ghatlelhu, kahchu yachinachustatalih, kahchu taoontya yehti toowe, Oochu Tanechiotyihi, tawoshlaitea ahtaze wostazonha? (aiōnios g166)
18 Jesu béèrè pé, arákùnrin, “Èéṣe tí o fi ń pè mí ní ẹni rere? Ẹni rere kan kò sí Ọlọ́run nìkan ni ẹni rere.
Kahchu Jesus toowe yehti, Yehoo gha oochu indityesa sindilon ha? atuline oochu oontye ehlaiti zon, ayi Tikeaootli.
19 Ìwọ mọ àwọn òfin bí: ‘Ìwọ kò gbọdọ̀ pànìyàn, ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe panṣágà, ìwọ kò gbọdọ̀ jalè, ìwọ kò gbọdọ̀ purọ́, ìwọ kò gbọdọ̀ rẹ́ ọmọnìkejì jẹ, bọ̀wọ̀ fún baba àti ìyá rẹ.’”
Sa tsiwohzon atanati, Atu soocha aoonta, Atu chu tane zaoohel, Atu chu anaooih, Atu chu ketselihoo tsiwotahoontich neotinoo, Atu chu tane nawoah, Ohtye taghooncha natgna chu noo chu.
20 Ọkùnrin náà dáhùn pé, “Olùkọ́, gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni èmi ń ṣe láti ìgbà èwe mi wá.”
Kahchu ateyatetlalon toowehchu yehti, Taneghaotatich, atghe tidi kama indityeaiih yeshihto otsi.
21 Jesu wò ó tìfẹ́tìfẹ́. Ó wí fún un pé, “Bí ó bá rí bẹ́ẹ̀, ohun kan ló kù fún ọ láti ṣe, lọ nísinsin yìí, ta gbogbo nǹkan tí o ní, kí o sì pín owó náà fún àwọn aláìní ìwọ yóò sì ní ìṣúra ní ọ̀run, sì wá, kí ó sì máa tọ̀ mí lẹ́yìn.”
Kahchu Jesus yakaihtgha, yuntyeh, kahchu toowe yehti, Ehlaiti ooli nainchi tehtsut: ootinta, anehisi anetye mataghaneli, tyetaisanaine chu ghatanale, kooh ohtye natatootlosi ya tehchi: kahchu yuhchidiya, kahchu ninaootiah ayi sookatiya-i, kahchu sakehtiya.
22 Nígbà tí ọkùnrin yìí gbọ́ èyí, ojú rẹ̀ korò, ó sì lọ pẹ̀lú ìbànújẹ́, nítorí pé ó ní ọrọ̀ púpọ̀.
Kahchu atu oochu indityesalon ayi sa tachi, kahchu yitaityeshalon atu keneli ihe: atane ohtye ooli natlon ayehilon.
23 Jesu wò ó bí ọkùnrin náà ti ń lọ. Ó yípadà, ó sì sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Àní, ohun ìṣòro ni fún ọlọ́rọ̀ láti wọ ìjọba Ọlọ́run!”
Kahchu Jesus klokanatgha, toowehchu yehti yaotatichne, Tewotye atatlate ayine matatintlone kwewootyelassi Nagha Tgha nataghe tsi!
24 Ọ̀rọ̀ yìí ya àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ lẹ́nu. Jesu tún sọ fún wọn pé, “Ẹyin ọmọ yóò tí ṣòro tó fún àwọn tí ó ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú ọrọ̀ láti wọ ìjọba Ọlọ́run.
Kahchu yaotatichne yazake kaooghulli. Ahwole Jesus ateyatetla kahchu toowehchu yehti, Tsitohkaine, tahtye indatlaooh ayi kiyasooli mehmehetatintlon kwewootyelu Nagha Tgha mataghe tsi!
25 Ó rọrùn fún ìbákasẹ láti gba ojú abẹ́rẹ́ wọlé jù fún ọlọ́rọ̀ kan láti wọ ìjọba ọ̀run.”
Ayi kyeotunni ghatai kwewotyizoo apetsiche kaookoodi, o-ochi matatintlon ehlaiti teze kwewoya Nagha Tgha nataghe tsi.
26 Ẹnu túbọ̀ ya àwọn ọmọ-ẹ̀yìn sí i. Wọ́n béèrè wí pé, “Tí ó bá rí bẹ́ẹ̀, ta ni nínú ayé ni ó lè ní ìgbàlà?”
Kahchu o-ochi ghaooghali, toowe hlaghatati ihe, Mea mechua aghatoota?
27 Jesu wò wọ́n, ó sì wí fún wọn pé, “Ènìyàn ní èyí kò ṣe é ṣe fún ṣùgbọ́n kì í ṣe fún Ọlọ́run, nítorí ohun gbogbo ni ṣíṣe fún Ọlọ́run.”
Kahchu Jesus yakaitgha toowe yehti, Tane la atu kookechi nioontsit, Nagha Tgha la atu kooh hoontye: aha atane Nagha Tgha atghezi ooli mahechi nioontsut.
28 Nígbà náà ni Peteru kọjú sí Jesu, ó wí pé, “Àwa ti fi ohun gbogbo sílẹ̀, a sì ń tọ̀ ọ́ lẹ́yìn.”
Kahchu Peter toowe tyi ehti, Nea anetye kyecho tasityetl, kahchu naghakyehtasityetliih.
29 Jesu dáhùn pé, “Lóòótọ́ ni mo wí fún un yín pé, kò sí ẹnikẹ́ni tí ó fi ohunkóhun sílẹ̀ bí: ilé, tàbí àwọn arákùnrin, tàbí àwọn arábìnrin, tàbí ìyá, tàbí baba, tàbí àwọn ọmọ tàbí ohun ìní nítorí mi àti nítorí ìyìnrere,
Kahchu Jesus ateyatetla toowehchu yehti, Kwa hli anaghaisii, atuline ooli kyeghachelihine nito kwa, mekye koole, mehtghizze koole, matgha koole, ma koole, matsiyue koole, maskyege koole, matsatle koole, suni ihe, kahchu otich oochu ihe,
30 tí a kì yóò fún padà ní ọgọọgọ́rùn-ún àwọn ilé, tàbí arákùnrin, tàbí arábìnrin, tàbí ìyá, tàbí ọmọ, tàbí ilẹ̀, àti inúnibíni pẹ̀lú. Gbogbo nǹkan wọ̀nyí yóò jẹ́ tirẹ̀ ní ayé yìí àti pé ní ayé tó ń bọ̀ yóò ní ìyè àìnípẹ̀kun. (aiōn g165, aiōnios g166)
Ahwole otsinitooalassi keonetyi ketyi otehche enetyi too, nito kwane, mekye chu, mehtghizze chu, matgha chu, ma chu, maskyege chu, makyeyih chu, kahchu tsookatayaghi chu; kahchu achu tike tsi ghonioonizut ate kwihzon ehchaghatai. (aiōn g165, aiōnios g166)
31 Ṣùgbọ́n ọ̀pọ̀ àwọn tí ó síwájú ni yóò di ẹni ìkẹyìn, àwọn tí ó sì kẹ́yìn yóò síwájú.”
Ahwole natlone haladi atine haistlachi awotyeissi; kahchu haistlachi atine haladi awotyeissi.
32 Nísinsin yìí, wọ́n wà lójú ọ̀nà sí Jerusalẹmu. Jesu sì ń lọ níwájú wọn, bí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn ti ń tẹ̀lé e, ìbẹ̀rù kún ọkàn wọn. Ó sì tún mú àwọn méjìlá sí apá kan, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí ṣàlàyé ohun gbogbo tí a ó ṣe sí i fún wọn.
Kahchu atghunni aghatii Jerusalem otsi ghatestyetlu; kahchu Jesus yaghatyesha: kahchu kawoghuli; kahchu kiyahsellu oonighanityetlon. Kahchu niyatila keneti onketi matgha kahchu yatatati yesoo yuhniyi ihe,
33 Ó sọ fún wọn pé, “Àwa ń gòkè lọ Jerusalẹmu, a ó sì fi Ọmọ Ènìyàn lé àwọn olórí àlùfáà àti àwọn olùkọ́ òfin lọ́wọ́. Wọn ni yóò dá lẹ́bi ikú. Wọn yóò sì fà á lé ọwọ́ àwọn aláìkọlà.
Toowe ehti ihe, Nea Jerusalem otsitatyetl; kahchu tane Chue niyatoohtyelassi taneghaotatich tyiyine, adesklesne chu; inkai mazetse ooli kiyehtlon, kahchu kiyaniyutyelessi achunene;
34 Wọn yóò fi ṣe ẹlẹ́yà, wọn yóò tutọ́ sí ní ara, wọn yóò nà pẹ̀lú pàṣán wọn. Wọn yóò sì pa, ṣùgbọ́n lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta yóò tún jíǹde.”
Kahchu kiyachaochesi, kahchu kikatootoozassi, kahchu kikyehoozekassi, kahchu kizoohelassi: taiti dzinee awooche ate tsitike nawootyeissi.
35 Lẹ́yìn èyí, Jakọbu àti Johanu, àwọn ọmọ Sebede wá sọ́dọ̀ Jesu. Wọ́n sì bá a sọ̀rọ̀ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́, wọ́n wí pé, “Olùkọ́, inú wa yóò dùn bí ìwọ bá lè ṣe ohunkóhun tí a bá béèrè fún wa.”
Kahchu James chu John chu, Zebidee chue, yachidesha toowe yehtie, Taneghaotatyechi, kooh koosti aghaawoti akootiti sikooh.
36 Jesu béèrè pé, “Kí ni Ẹ̀yin ń fẹ́ kí èmi ó ṣe fún un yín?”
Kahchu toowe yehti, Yea sachi nioonunassit naghachanasti?
37 Wọ́n bẹ̀bẹ̀ pé, “Jẹ́ kí ọ̀kan nínú wa jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ àti ẹnìkejì ní ọwọ́ òsì nínú ògo rẹ!”
Kahchu toowe kiyehti, Aghaniah sookah ookyetih, ehlaiti mehoonati, hligi oosklaghazihtye, nachatinchai kehe.
38 Ṣùgbọ́n Jesu dá wọn lóhùn pé, “Ẹ kò mọ ohun tí ẹ̀ ń béèrè! Ṣe ẹ lè mu nínú ago kíkorò tí èmi ó mú tàbí a lè bamitiisi yín pẹ̀lú irú ì bamitiisi ìjìyà tí a ó fi bamitiisi mi?”
Ahwole Jesus toowe yehtii, Atu atawahti ooli ootahkyeti: atu mihe tuwahto la ayi tsa mehtughastoii? kahchu tunaghakechuhkliti ayi mehtanekhaitsikliti ayi ihe nehsakaichihkliti?
39 Àwọn méjèèjì dáhùn pé, “Àwa pẹ̀lú lè ṣe bẹ́ẹ̀.” Jesu wí fún wọn pé, “Lóòótọ́ ni ẹ̀yin ó mu ago ti èmi yóò mu, àti bamitiisi tí a sí bamitiisi mi ni a ó fi bamitiisi yín,
Toowe kiyehti, Atu ahandatla. Kahchu Jesus toowe yehti, Kwa hli tuwahtoissi tsaeh ieti otsi tughastode; kahchu ayi mehtukhaitsihkliti mihe tusakechihklitii ihe ayi ihe mihe naghakyechuhklitassi:
40 ṣùgbọ́n láti jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún mi àti ní ọwọ́ òsì mi kì ì ṣe ti èmi láti fi fún ni: bí kò ṣe fún àwọn ẹni tí a ti pèsè rẹ̀ sílẹ̀ fún.”
Ahwole wostyi chisinchi chu tayaghetichu oosklaghazintye atu si senatunne eli kaooali; ahwole kooyachulelassi ayine kooya so-ochesunne,
41 Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mẹ́wàá ìyókù gbọ́ ohun tí Jakọbu àti Johanu béèrè, wọ́n bínú.
Kahchu kenetyine aghatitsuk chi ohtye atu yatsi kyehanelilon James chu John chu.
42 Nítorí ìdí èyí, Jesu pè wọ́n sọ́dọ̀, ó sì wí fún wọn pé, “Gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yin ti mọ̀ pé, àwọn ọba àti àwọn kèfèrí ń lo agbára lórí àwọn ènìyàn.
Ahwole Jesus tyechi yehtilon toowehchu yehti, Atawahti ayi kechanehtya kehe kikaootsutti ayi achune kooyakeolech; kahchu kootaityiye kooyaghatah.
43 Ṣùgbọ́n láàrín yín ko gbọdọ̀ ri bẹ. Ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ di olórí nínú yín gbọdọ̀ ṣe ìránṣẹ́.
Ahwole naghai atu kooh akehe naghahtyeissi: Ahwole ayi koonoochu sachatoohcha kooti, naghani ayi nagha keo-otichassi:
44 Ẹnikẹ́ni tí ó fẹ́ di aṣáájú nínú yín gbọdọ̀ ṣe ìránṣẹ́ gbogbo yín.
Kahchu ooline assine naghani ihe haladi miindichatoesi o-ochi chatoohchai gha, tane glia keo-otichassi achanetye gha.
45 Nítorí, Èmi, Ọmọ Ènìyàn kò wá sí ayé kí ẹ lè ṣe ìránṣẹ́ fún mi, ṣùgbọ́n láti lè ṣe ìránṣẹ́ fun àwọn ẹlòmíràn, àti láti fi ẹ̀mí rẹ̀ ṣe ìràpadà ọ̀pọ̀ ènìyàn.”
Ayi aghoo teze Chue atu makeochatichi ihe yuhchideya, ahwole tane gha keo-otichassi, kahchu khaooallu yeghataisi natlone yatachi ootane.
46 Wọ́n dé Jeriko, bí Jesu àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ àti ọ̀pọ̀ ènìyàn ti fẹ́ kúrò ní ìlú Jeriko, ọkùnrin afọ́jú kan, Bartimeu, ọmọ Timeu jókòó lẹ́gbẹ̀ẹ́ ọ̀nà ó ń ṣagbe.
Kahchu nighanintyetl Jericho: kahchu Jericho otsi hatayaooh yaotatichne chu tane natlone chu, mataituehi Bartimaeus, chue Timaeus, tinkuzze satah tyechihi ihe.
47 Nígbà tí Bartimeu gbọ́ pé Jesu ti Nasareti wà nítòsí, o bẹ̀rẹ̀ sí kígbe lóhùn rara pé, “Jesu ọmọ Dafidi, ṣàánú fún mi.”
Atitsuk chi ayi Jesus Nazareth chihtatyezutti, ohtye tyi otyesta, kahchu toowe yehti, Jesus nai chue David, soonchoonaya.
48 Àwọn tó wà níbẹ̀ kígbe mọ́ ọn pé, “Pa ẹnu rẹ mọ́.” Ṣùgbọ́n dípò kí ó pa ẹnu mọ́, ṣe ló ń kígbe lóhùn rara pé, “Jesu ọmọ Dafidi ṣàánú fún mi.”
Kahchu natlone yatati atu awotihi gha: hoontye ooli otaihchi ohtye otyesta, David chue, soonchoonaya.
49 Nígbà tí Jesu gbọ́ igbe rẹ̀, ó dẹ́sẹ̀ dúró lójú ọ̀nà, ó sì wí pé, “Ẹ pè é kí ó wá sọ́dọ̀ mi.” Nítorí náà wọ́n pe ọkùnrin afọ́jú náà, wọ́n wí pé, “Tújúká! Dìde lórí ẹsẹ̀ rẹ! Ó ń pè ọ́.”
Kahchu Jesus hlininiya, kahchu kwehakehe ehti. Kahchu tyechi kiyehti ayi teze mataituehi, toowe kiyehti ihe, Kyeneneli, niiya; tyechi nehti.
50 Lẹ́sẹ̀kan náà, Bartimeu bọ́ agbádá rẹ̀ sọnù, ó fò sókè, ó sì wá sọ́dọ̀ Jesu.
Kahchu ooyadehchus yiatehtakadi, niiya, kahchu Jesus tsidyesha.
51 Jesu béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Kí ni ìwọ fẹ́ kí èmi kí ó ṣe fún ọ?” Afọ́jú náà dáhùn pé, “Rabbi, jẹ́ kí èmi kí ó ríran.”
Kahchu Jesus otyesta toowehchu yehti, Ye sachinioonunisita anusleha? Ayi mataituehi teze toowe ehti, Aghaghintai, setai saanaoontlihi.
52 Jesu wí fún un pé, “Máa lọ, ìgbàgbọ́ rẹ ti mú ọ láradá.” Lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀, ọkùnrin afọ́jú náà ríran ó sì ń tẹ̀lé Jesu lọ ní ọ̀nà.
Jesus toowe yehti, Taihchi ootinta; na-ihe naghinta. Iitetyeh matai naootli, kahchu Jesus kyehtesha atghunni.

< Mark 10 >