< Malachi 4 >

1 “Dájúdájú, ọjọ́ náà ń bọ̀; tí yóò máa jó bi iná ìléru. Gbogbo àwọn agbéraga, àti gbogbo àwọn olùṣe búburú yóò dàbí àgékù koríko: ọjọ́ náà tí ń bọ̀ yóò si jó wọn run,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, “Ti ki yóò fi kù gbòǹgbò kan tàbí ẹ̀ka kan fún wọn.
Xəəne G'oşunbışde Rəbbee eyhen: – Peşt xhinne gyotxhanan yiğ k'ane qexhe vod. Gırgın cocab co axtıba vukkekanbıyiy pisvalla haa'anbı, mane yiğıl balybiy xhinne gyooxhanas. Mane k'ane qexhene yiğın manbı gyooxhan haa'asınbı. Manbışike kokbıd, bıtağbıd axvas deş.
2 Ṣùgbọ́n fún ẹ̀yin tí ó bẹ̀rù orúkọ mi, oòrùn òdodo yóò yọ, pẹ̀lú ìmúláradá ni ìyẹ́ apá rẹ̀. Ẹ̀yin yóò sì jáde lọ, ẹ̀yin yóò sì máa fò fún ayọ̀ bi àwọn ẹgbọrọ màlúù tí a tú sílẹ̀ lórí ìso.
Zale qəvəyq'ənanbışdemeeme, Qopkuvalina verığ ılqevç'es. Mançine şü'ülee yug qav'iy ixhes. Ağıleençe g'aykkiyn q'ıkar xhinne şu huvaagas.
3 Ẹ̀yin yóò sì tẹ àwọn ènìyàn búburú mọ́lẹ̀: nítorí wọn yóò di eérú lábẹ́ àtẹ́lẹsẹ̀ yín, ní ọjọ́ náà tí èmi yóò ṣe nǹkan wọ̀nyí,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Pisınbı şu kööq'əsınbı. Zı man ha'asde yiğıl, manbı vuşde g'elybışik avub yı'q xhinne vuxhes. Məxüd Xəəne G'oşunbışde Rəbbee eyhe!
4 “Ẹ rántí òfin Mose ìránṣẹ́ mi, àwọn ìlànà àti òfin èyí tí mo fún un ní Horebu fún gbogbo Israẹli.”
Yizda nukar Mısa Xorevne suvalynang'a, Zı mang'us İzrailyne milletnemeecab huvuna Q'aanun, Yizın g'aydabıyiy əmrbı şu yik'el aqqe.
5 “Wò ó, èmi yóò rán wòlíì Elijah sí i yín, ki ọjọ́ ńlá, ọjọ́ ẹ̀rù Olúwa to dé.
İlyaake, Rəbbin xədın, dağamın yiğ qalesse, Zı şosqa İlyas peyğambar g'axıles.
6 Òun yóò sì pa ọkàn àwọn baba dà sí ti àwọn ọmọ, àti ọkàn àwọn ọmọ sì ti àwọn baba wọn, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, èmi yóò wá, èmi yóò sì fi ilẹ̀ náà gégùn.”
Zı qarı in cigabı kunfa-yakun hıma'acenva, Mang'vee dekkaaşin yik'bı dixbışilqa, dixbışinbıd dekkaaşilqa sak'al ha'as.

< Malachi 4 >