< Malachi 4 >

1 “Dájúdájú, ọjọ́ náà ń bọ̀; tí yóò máa jó bi iná ìléru. Gbogbo àwọn agbéraga, àti gbogbo àwọn olùṣe búburú yóò dàbí àgékù koríko: ọjọ́ náà tí ń bọ̀ yóò si jó wọn run,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, “Ti ki yóò fi kù gbòǹgbò kan tàbí ẹ̀ka kan fún wọn.
Inao, ho tondroke ty andro hirehetse hoe toñake; ie ho ahe-maike iaby o mpirengevokeo naho o mpanao haloloañeo; hampirebareba iareo amy andro ho aviy, hoe t’Iehovà’ i Màroy, vaho tsy hapo’e ndra vahatse ndra singa.
2 Ṣùgbọ́n fún ẹ̀yin tí ó bẹ̀rù orúkọ mi, oòrùn òdodo yóò yọ, pẹ̀lú ìmúláradá ni ìyẹ́ apá rẹ̀. Ẹ̀yin yóò sì jáde lọ, ẹ̀yin yóò sì máa fò fún ayọ̀ bi àwọn ẹgbọrọ màlúù tí a tú sílẹ̀ lórí ìso.
Fe ama’ areo mpañeveñe ami’ty añarako, ro hanjiriha’ ty andron-kavañonañe, reketse fijangañañe an-dengon-tsaro’e eo; hionjom-beo nahareo manahake ty fivoamboañan-tsarake boak’an-kijoly ao.
3 Ẹ̀yin yóò sì tẹ àwọn ènìyàn búburú mọ́lẹ̀: nítorí wọn yóò di eérú lábẹ́ àtẹ́lẹsẹ̀ yín, ní ọjọ́ náà tí èmi yóò ṣe nǹkan wọ̀nyí,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Le ho lialià’ areo o lo-tserekeo; ie ho lavenok’ ambane’ lelam-pandia’ areo ao amy andro anoeko izay, hoe t’Iehovà’ i Màroy.
4 “Ẹ rántí òfin Mose ìránṣẹ́ mi, àwọn ìlànà àti òfin èyí tí mo fún un ní Horebu fún gbogbo Israẹli.”
Tiahio i Ha’ i Mosè mpitorokoy, i nafantoko aze e Korebe añey: o fañè naho fepetse ho a Israele iabio.
5 “Wò ó, èmi yóò rán wòlíì Elijah sí i yín, ki ọjọ́ ńlá, ọjọ́ ẹ̀rù Olúwa to dé.
Inao te hiraheko ama’ areo t’i Elià mpitoky aolo’ i andro Iehovà jabajaba naho maharevendreveñey.
6 Òun yóò sì pa ọkàn àwọn baba dà sí ti àwọn ọmọ, àti ọkàn àwọn ọmọ sì ti àwọn baba wọn, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, èmi yóò wá, èmi yóò sì fi ilẹ̀ náà gégùn.”
Ie ty hampimpoly ty arofon-droae amo ana’eo, naho o tron’anakeo aman-droae’iareoo; tsy mone homb’eo iraho handafa i taney am-pandrotsahañe do’e.

< Malachi 4 >