< Malachi 4 >
1 “Dájúdájú, ọjọ́ náà ń bọ̀; tí yóò máa jó bi iná ìléru. Gbogbo àwọn agbéraga, àti gbogbo àwọn olùṣe búburú yóò dàbí àgékù koríko: ọjọ́ náà tí ń bọ̀ yóò si jó wọn run,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, “Ti ki yóò fi kù gbòǹgbò kan tàbí ẹ̀ka kan fún wọn.
Hina Gode Bagadedafa da amane sia: sa, “Eso da mana, amoga wadela: i hamosu dunu amola hidale gasa fi dunu huluane da gilisili gisi agoane laluga nenanebe ba: mu. Amo esoga ili da laluga nene dagole, susei hamedafa ba: mu.
2 Ṣùgbọ́n fún ẹ̀yin tí ó bẹ̀rù orúkọ mi, oòrùn òdodo yóò yọ, pẹ̀lú ìmúláradá ni ìyẹ́ apá rẹ̀. Ẹ̀yin yóò sì jáde lọ, ẹ̀yin yóò sì máa fò fún ayọ̀ bi àwọn ẹgbọrọ màlúù tí a tú sílẹ̀ lórí ìso.
Be dilia, Nama nabasu dunu, dilia da Na gaga: su gasa bagade hou dili gaga: ma: ne, eso ea heda: su hou defele dilima heda: lebe ba: mu. Amola eso ea digagala: su defele, dilia uhinisisu houdafa ba: mu. Bulamagau mano da ea gagoi logo doasi dagoi ba: sea, hahawane gadili lala, amo defele dilia da hahawane halegale lalumu.
3 Ẹ̀yin yóò sì tẹ àwọn ènìyàn búburú mọ́lẹ̀: nítorí wọn yóò di eérú lábẹ́ àtẹ́lẹsẹ̀ yín, ní ọjọ́ náà tí èmi yóò ṣe nǹkan wọ̀nyí,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Amo eso bagadega Na da gasa bagade hamosea, dilia da wadela: i hamosu dunu ilima osa: le heda: le, ilia da dilia emo hagudu osobo gulu agoane ba: mu.
4 “Ẹ rántí òfin Mose ìránṣẹ́ mi, àwọn ìlànà àti òfin èyí tí mo fún un ní Horebu fún gbogbo Israẹli.”
Dilia da olelesu, amo Na da Na hawa: hamosu dunu Mousesema olelei, amo bu dawa: ma. Amo sema amola hamoma: ne sia: i Na da Sainai Goumia, Isala: ili dunu huluane ilima nabawane fa: no bobogema: ne, Mousesema i.
5 “Wò ó, èmi yóò rán wòlíì Elijah sí i yín, ki ọjọ́ ńlá, ọjọ́ ẹ̀rù Olúwa to dé.
Amo eso bagadedafa Na da hamosea, osobo bagade fifi asi gala dunu huluane da bagadewane beda: mu. Be hidadea, Na da balofede dunu Ilaidia amo dilima asunasimu.
6 Òun yóò sì pa ọkàn àwọn baba dà sí ti àwọn ọmọ, àti ọkàn àwọn ọmọ sì ti àwọn baba wọn, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, èmi yóò wá, èmi yóò sì fi ilẹ̀ náà gégùn.”
E da eda amola mano huluane gilisilisimu. Be agoane hame ilegei ganiaba, Na da dilia soge wadela: lesila: loba.” Sia: ama dagoi