< Malachi 3 >

1 “Wò ó, Èmi yóò ran ìránṣẹ́ mi, yóò tún ọ̀nà ṣe ṣáájú mi. Nígbà náà ni Olúwa, tí ẹ̀yin ń wa, yóò dé ni òjijì sí tẹmpili rẹ̀; àní oníṣẹ́ májẹ̀mú náà, tí inú yín dùn sí, yóò dé,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
LEUM GOD Kulana El topuk ac fahk, “Nga fah supwaot mwet utuk kas luk in akoela inkanek luk. Na Leum su kowos suk ac fah sa na in tuku nu ke Tempul lal. Mwet utuk pweng se su kowos kena liye inge ac fah tuku ac sulkakin wuleang luk.”
2 Ṣùgbọ́n ta ni o lè fi ara da ọjọ́ dídé rẹ̀? Ta ni yóò sì dúró nígbà tí ó bá fi ara hàn? Nítorí òun yóò dàbí iná ẹni tí ń da fàdákà àti bi ọṣẹ alágbàfọ̀.
Tusruktu su ac fah ku in muteng len sac ke El tuku? Su ac fah ku in painmoulla ke El ac sikme? El ac fah oana sie e arulana ku ma aknasnasye osra, ac oana soap kulana.
3 Òun yóò sì jókòó bí ẹni tí n yọ́, tí ó sì ń da fàdákà; yóò wẹ àwọn ọmọ Lefi mọ́, yóò sì tún wọn dàbí wúrà àti fàdákà, kí wọn bá a lè mú ọrẹ òdodo wá fún Olúwa,
El ac fah tuku in orek nununku oana sie mwet orekma ke osra su munanak silver ac gold in aknasnasyela. Ouinge mwet utuk kas lun LEUM GOD fah aknasnasye mwet tol uh, na elos fah use mwe sang wo ma fal nu sin LEUM GOD.
4 nígbà náà ni ọrẹ Juda àti ti Jerusalẹmu yóò jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà fún Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ti ọjọ́ àtijọ́, àti gẹ́gẹ́ bí ọdún ìgbàanì.
Na mwe sang su mwet Judah ac mwet Jerusalem us nu sin LEUM GOD fah mwe insewowo nu sel, oana in pacl meet ah.
5 “Èmi ó sì súnmọ́ yin fún ìdájọ́. Èmi yóò sì yára ṣe ẹlẹ́rìí sí àwọn oṣó, sí àwọn panṣágà, sí àwọn abúra èké, àti àwọn tí ó fi ọ̀yà alágbàṣe pọn wọn lójú, àti àwọn tí ó ni àwọn opó àti àwọn aláìní baba lára, àti sí ẹni tí kò jẹ́ kí àjèjì rí ìdájọ́ òdodo gbà, tí wọn kò sì bẹ̀rù mi,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
LEUM GOD Kulana El fahk, “Nga ac fah tuku nu yuruwos in nununkekowos, ac nga fah sa in orek loh lainulos su inutnut, oayapa mwet kosro, ac elos su orek loh kikiap, ac elos su kutasrik ke molin mwet orekma lalos, ac elos su oru koluk nu sin katinmas, tulik mukaimtal, ac mwetsac — aok, lainulos nukewa su tia sunakinyu.
6 “Èmi Olúwa kò yípadà. Nítorí náà ni a kò ṣe run ẹ̀yin ọmọ Jakọbu.
“Nga pa LEUM GOD, ac nga tia ekyek. Ouinge kowos, fwilin tulik natul Jacob, kowos soenna tuhlac na pwaye.
7 Láti ọjọ́ àwọn baba ńlá yín wá ni ẹ̀yin tilẹ̀ ti kọ ẹ̀yìn sí ìlànà mi, tí ẹ kò sì pa wọ́n mọ́. Ẹ padà wá sí ọ̀dọ̀ mi, Èmi yóò sì padà sí ọ̀dọ̀ yín,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí. “Ṣùgbọ́n ẹ̀yin béèrè pé, ‘Báwo ni àwa yóò ṣe padà?’
Kowos oapana mwet matu lowos meet liki kowos, su forla liki ma sap luk ac tia liyaung. Foloko nu yuruk, ac nga fah folokot nu yuruwos. Na kowos siyuk, ‘Mea kut ac enenu in oru tuh kut in folokot nu yurum?’
8 “Ènìyàn yóò ha ja Ọlọ́run ni olè bí? Síbẹ̀ ẹ̀yin ti jà mí ní olè. “Ṣùgbọ́n ẹ̀yin béèrè pé, ‘Báwo ni àwa ṣe jà ọ́ ní olè?’ “Nípa ìdámẹ́wàá àti ọrẹ.
Nga siyuk suwos, ya fal sie mwet in kutasrik nu sin God? Kalem lah tiana fal, a kowos orek kutasrik nu sik. Na kowos siyuk, ‘Kut kutasriki kom fuka?’ Ke mwe sang ac sie tafu singoul lowos.
9 Ríré ni a ó fi yín ré: gbogbo orílẹ̀-èdè yìí, nítorí ẹ̀yin ti jà mi lólè.
Sie selnga oan fowos nukewa, mweyen mutunfacl se inge nufon kutasrik nu sik.
10 Ẹ mú gbogbo ìdámẹ́wàá wá sí ilé ìṣúra, kí oúnjẹ bá à lè wà ní ilé mi, ẹ fi èyí dán mi wò,” ní Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, “kí ẹ sì wò bí èmi kò bá ní sí àwọn fèrèsé ọ̀run fún yin, kí èmi sì tú ìbùkún àkúnwọ́sílẹ̀ jáde fún yín, tó bẹ́ẹ̀ tí kì yóò sì ààyè láti gbà á.
Use nufon lupan sie tafu singoul lowos nu ke nien filma in Tempul, tuh in pus mwe mongo we. Srikeyu ac kowos fah liye ke nga ac ikasla winto inkusrao ac ukuiya nu fowos kain in ma wo nukewa, in arulana yolyak nu suwos.
11 Èmi yóò sì bá kòkòrò ajẹnirun wí nítorí yín, òun kò sì ni run èso ilẹ̀ yín, bẹ́ẹ̀ ni àjàrà inú oko yín kò ní rẹ̀ dànù,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Nga fah tia lela wet srisrik in kunausla sacn sunowos, ac ima in grape lowos uh ac fah rukruk ke fahko.
12 “Nígbà náà ni gbogbo orílẹ̀-èdè yóò sì pè yín ni alábùkún fún, nítorí tiyín yóò jẹ́ ilẹ̀ tí ó wu ni,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Na mutunfacl nukewa fah pangon kowos mwet insewowo, mweyen facl suwos uh ac fah sie acn wowo in muta we.”
13 “Ẹ̀yin ti sọ ọ̀rọ̀ líle sí mi,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí. “Síbẹ̀ ẹ̀yin béèrè pé, ‘Ọ̀rọ̀ kín ni àwa sọ sí ọ?’
LEUM GOD El fahk, “Kowos fahk kas in akkolukyeyu. A kowos siyuk, ‘Mea kut fahk keim?’
14 “Ẹ̀yin ti wí pé, ‘Asán ni láti sin Ọlọ́run. Kí ni àwa jẹ ní èrè, nígbà tí àwa ti pa ìlànà rẹ mọ́, tí àwa sì ń rìn kiri bí ẹni tí ń ṣọ̀fọ̀ ní iwájú Olúwa àwọn ọmọ-ogun?
Kowos fahk mu, ‘Wangin sripa kut in orekma nu sin God. Mwe mea kut in oru ma El fahk uh, ku in akkalemye nu sin LEUM GOD Kulana lah kut asor ke ma kut oru uh?
15 Ṣùgbọ́n ní ìsinsin yìí àwa pé agbéraga ni alábùkún fún. Ní òtítọ́ ni àwọn ti ń ṣe búburú ń gbèrú sí i, kódà àwọn ti ó dán Ọlọ́run wò ni a dá sí.’”
Ke liye lasr uh, mwet filang uh pa insewowo. Mwet koluk uh elos kapkapak, ac ke elos srike muteng lun God ke orekma koluk lalos, wanginna ma sikyak nu selos.’”
16 Nígbà náà ni àwọn tí ó bẹ̀rù Olúwa ń ba ara wọn sọ̀rọ̀, Olúwa sì tẹ́tí sí i, ó sì gbọ́. A sì kọ ìwé ìrántí kan níwájú rẹ̀, fún àwọn tí o bẹ̀rù Olúwa, tiwọn sì bọ̀wọ̀ fún orúkọ rẹ̀.
Na mwet su akfulatye LEUM GOD elos asramsrami, ac LEUM GOD El lipsre ac lohng ma elos fahk uh. Na simisyukla inen mwet nukewa su sangeng sin LEUM GOD ac akfulatyal, ke sie book in esmakin ye mutal.
17 “Wọn yóò sì jẹ́ tèmi,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, “ni ọjọ́ náà, tí èmi ó dá; èmi yóò sì da wọ́n sí gẹ́gẹ́ bí ènìyàn tí máa ń dá ọmọ rẹ̀ tí yóò sìn ín sí.
LEUM GOD Kulana El fahk, “Elos inge ac fah mwet luk. In len se ke nga ac oru nununku luk, elos ac fah ma luk sifacna. Nga ac fah pakomutalos oana ke sie papa el pakomuta sie wen su aksol.
18 Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò rí ìyàtọ̀, ìyàtọ̀ láàrín olódodo àti ẹni búburú, láàrín ẹni tí ń sìn Ọlọ́run, àti ẹni tí kò sìn ín.
Na mwet luk elos ac fah sifilpa liye lah oasr ekla inmasrlon ma ac sikyak nu sin mwet suwoswos ac mwet koluk, ac nu selos su kulansupweyu ac elos su tia.”

< Malachi 3 >