< Malachi 2 >

1 “Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ẹ̀yin àlùfáà, òfin yìí ní fún yín.
Xəəne G'oşunbışde Rəbbee eyhe vod: – Kaahinar, ina əmr həşde vuşdemee vob: Yizde cuvabıl k'ırı ilydiyxheene, Yizın do yik'eençe axtı qıde'eene, şolqa bed-düə gyooğav'u, vuşun xayir-düəbı bed-düəlqa sak'al ha'as. Şu Yizın do yik'eençe axtı qıdi'ıva, şu Yizda bed-düə alyapt'ınacab.
2 Bí ẹ̀yin kò bá ni gbọ́, bí ẹ̀yin kò bá ní fi í sí àyà láti fi ọ̀wọ̀ fún orúkọ mi,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí; èmi yóò sì ran ègún sí orí yín, èmi yóò sì fi ìbùkún yín ré. Nítòótọ́ mó ti fi ré ná, nítorí pé, ẹ̀yin kò fi sí ọkàn yín láti bu ọlá fún mi.
3 “Nítorí tiyín èmí yóò ba àwọn ọmọ yín wí, èmi ó sì fi ìgbẹ́ rẹ́ yín lójú, àní àwọn ìgbẹ́ ọrẹ ọwọ́ yín wọ̀nyí, a ó sì kó yín lọ pẹ̀lú rẹ̀.
Zı şol-alla şoke g'abıynbışikınıd ha'asın. Bayrambışil şu q'urbanna alli'iyne həyvanaaşin xhidbı Zı vuşde aq'vabışile k'ena ı'xəs, mançika sacigee şu dağaa'as.
4 Ẹ̀yin ó sì mọ̀ pé, èmi ni ó ti rán òfin yìí sí yín, kí májẹ̀mú mi pẹ̀lú Lefi lè tẹ̀síwájú,” ní Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Manke şok'le ats'axhxhes, Zı mana əmr şoka, Leviyne nasılıka, hav'una mugaavile aaxvecenva g'axuvu. Məxüd Xəəne G'oşunbışde Rəbbee eyhe!
5 “Májẹ̀mú mi wà pẹ̀lú rẹ̀, májẹ̀mú ti ìyè àti àlàáfíà wà pẹ̀lú rẹ̀; mo sì fi wọn fún un, nítorí bíbẹ̀rù tí ó bẹ̀rù mi, tí ẹ̀rù orúkọ mi sì bà á.
Zı Leviyne nasılıka barakatnana ı'mı'r hoolena mugaavileniy hav'u. Zas hı'rmat gyuvxhuva, Zı manbışis man gırgın huvuyn. Manbıb Zale qəpq'ı'ninbı, Yizde doyusub hı'rmat gyuvxhuna.
6 Òfin òtítọ́ wà ni ẹnu rẹ̀, a kò sì rí irọ́ ni ètè rẹ̀: ó ba mi rìn ní àlàáfíà àti ni ìdúró ṣinṣin, ó sì yí ọ̀pọ̀lọpọ̀ kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀.
Manbışde mizel qopkuna Q'aanun vuxha, ghaleençed horbı qığeeç'enbı deşdiy. Manbışe Yizde ögil yugnayiy qopkuna ı'mı'r hav'u. Geebınbı manbışe yəqqı'lqa sav'u.
7 “Nítorí ètè àlùfáà ní òye láti máa pa ìmọ̀ mọ́, kí àwọn ènìyàn lè máa wá ìtọ́ni ni ẹnu rẹ̀: nítorí òun ni ìránṣẹ́ Olúwa àwọn ọmọ-ogun.
Kaahinaaşine ghalen ats'al havaces ıkkan, insanaaşisse manbışde mizele Q'aanun t'abal haa'as vəəxecenva. Kaahinar Xəəne G'oşunbışde Rəbbee g'axuvuynbı vob.
8 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ti yapa kúrò ní ọ̀nà náà; ẹ̀yin sì ti fi ìkọ́ni yín mú ọ̀pọ̀lọpọ̀ kọsẹ̀; ẹ̀yin ti ba májẹ̀mú tí mo da pẹ̀lú Lefi jẹ́,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Şumee, kaahinar, yəqqı'le qığeepç'ıynbı, şu helene ats'aalybışika mansanbıb şoqab qihna habğı. Zı Leviyne nasılıka hav'una mugaavile şu havakkal hav'una. Məxüd Xəəne G'oşunbışde Rəbbee eyhe!
9 “Nítorí náà ni èmi pẹ̀lú ṣe sọ yín di ẹ̀gàn, àti ẹni àìkàsí níwájú gbogbo ènìyàn, nítorí ẹ̀yin kò tẹ̀lé ọ̀nà mi, ṣùgbọ́n ẹ̀yin ń ṣe ojúsàájú nínú òfin.”
Şu Yizde yəqqı'n apk'ın deş, Q'aanunuka g'acesde işbışee, şu gırgıng'uqa sa uleka ılyaakı deş. Mançil-allab Zı şu milletnecab g'eliqqa hevles, k'ap'ik'ıle avqa qaa'as.
10 Baba kan náà kí gbogbo wa ha ní? Ọlọ́run kan náà kọ́ ni ó dá wa bí? Nítorí kín ni àwa ha ṣe sọ májẹ̀mú àwọn baba wa di aláìmọ nípa híhu ìwà àrékérekè olúkúlùkù sí arákùnrin rẹ̀?
Yişda gırgıng'una Dek sa dişde vor? Şi sa Allahee dişde ipxhın? Nya'a manke şi dekkaaşika hav'una mugaavileyna muq'addasiyvalla avaakan haa'a, sana-sang'us horbı ha'a?
11 Juda ti ń hùwà àrékérekè, a sì ti hùwà ìríra ní Israẹli àti ni Jerusalẹmu: nítorí Juda tí sọ ìwà mímọ́ Olúwa di aláìmọ́, èyí tí ó fẹ́, nípa gbígbé ọmọbìnrin ọlọ́run àjèjì ni ìyàwó.
Yahudayne milletın Allahıs xayaanat hı'ı. İzraileeyiy İyerusalimee həlyvəəq'ənasın işbı hı'ı: Yahudabışee menne allahbışis ı'bəədat ha'an yedar hav'u, Rəbbis ıkkananne, muq'addasne cigayna muq'addasiyvalla avaakan hav'u.
12 Ní ti ẹni tí ó ṣe èyí, ẹni tí ó wù kí ó jẹ, kí Olúwa kí ó gé e kúrò nínú àgọ́ Jakọbu, bí ó tilẹ̀ mú ẹbọ ọrẹ wá fún Olúwa àwọn ọmọ-ogun.
Man hı'ına insan vuşu ıxhay ixhecen, Xəəne G'oşunbışde Rəbbis q'urban ablyaa'ana çikana ixheeyir, Rəbbee mana Yaaq'ubne çadırbışisse g'e'eşşecen.
13 Èyí ni ohun mìíràn tí ẹ̀yin sì túnṣe. Ẹ̀yin fi omijé bo pẹpẹ Olúwa mọ́lẹ̀. Ẹ̀yin sọkún, ẹ̀yin sì ba ara jẹ́ nítorí tì Òun kò ka ọrẹ yín sí mọ́, tàbí kí ó fi inú dídùn gba nǹkan yìí lọ́wọ́ yín.
Şu in karıd ha'an: gyaaşu-gyaaxu, Rəbbin q'urbanbı allya'an cigad ulene nağıka gyats'a'an. Məxüd, şu adıyne q'urbanıqa Rəbb sak'ı ilydakkava, manbı şoke ilydyaat'ava ha'a.
14 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin wí pé, “Nítorí kín ní?” Nítorí Olúwa ti ṣe ẹlẹ́rìí láàrín ìwọ àti láàrín aya èwe rẹ, ẹni tí ìwọ ti ń hùwà ẹ̀tàn sí i: bẹ́ẹ̀ ni ẹnìkejì rẹ ni òun jẹ́, àti aya májẹ̀mú rẹ.
Şosse «Nişil allavane?» qidghın ha'as əxə. Ğu mek'vranang'a hey'iyne zəiyfayneyiy yiğne yı'q'nee Şahad Rəbb vorna. Ğu, mana yiğna nikahıkana xhunaşşe yixhayka ilydyakkı, məng'ı's xayaanat hı'ı.
15 Ọlọ́run kò ha ti ṣe wọ́n ní ọ̀kan? Ni ara àti ni ẹ̀mí tirẹ̀ ni. Èéṣe tí Ọlọ́run da yín lọ́kàn? Kí òun bá à lè wá irú-ọmọ bí ti Ọlọ́run. Nítorí náà, ẹ tọ́jú ẹ̀mí yín, ẹ má sì ṣe hùwà ẹ̀tàn sí aya èwe yín.
Allahee şu sa tan, sa rı'h xhinne dişde ipxhın? Nya'asdiyxan Mang'us şu sa vuxha vukkan? Mang'us Cunemee nasılniy vukkan. Mançil-allab şucab şu havaace. Hasre şavaacad mek'vranang'a hey'iyne xhunaşşeys xayaanat hıma'acen.
16 “Ọkùnrin tí ó bá kórìíra, tí ó sì kọ ìyàwó rẹ̀,” se ìwà ipá sí ẹni tí ó yẹ kí ó dá ààbò bò, ni Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí, Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun. Nítorí náà, ẹ ṣọ́ ẹ̀mí yín, kí ẹ má ṣe hùwà ẹ̀tàn.
İzrailyne Allahee, Rəbbee eyhen: – Xhunaşşeyka yugra dexhena, mana qıxeelena Zak'le g'ımece vor. Mançil-allad şucab şu havaace, xayaanat hıma'a! Məxüd Xəəne G'oşunbışde Rəbbee eyhe!
17 Ẹ̀yin ti fi ọ̀rọ̀ yín dá Olúwa ní agara. Ṣùgbọ́n ẹ̀yin béèrè pé, “Nínú kín ni àwa fi dá a ní agara?” Nígbà tí ẹ̀yìn wí pé, “Gbogbo ẹni tí ó ṣe ibi, rere ni níwájú Olúwa, inú rẹ̀ sì dùn sí wọn,” tàbí “Níbo ni Ọlọ́run ìdájọ́ gbé wà?”
Vuşde yuşan hav'uyn Rəbb ozar ha'a. «Nəxürne şi Mana ozar ha'ava?» şosse qiyghanasıd əxə. Şu eyhen: – Qəlasın ha'anbı Rəbbine ulesqa yugba qöö, Rəbbis manbı vukkananbı. Şucadıd meed eyhen: – Qopkuvalin məhkama alğayhena Allah nyaane? Mançikar şu Mana ozar ha'a.

< Malachi 2 >