< Malachi 2 >

1 “Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ẹ̀yin àlùfáà, òfin yìí ní fún yín.
“To koro, yaye jodolo, siemni en maru.
2 Bí ẹ̀yin kò bá ni gbọ́, bí ẹ̀yin kò bá ní fi í sí àyà láti fi ọ̀wọ̀ fún orúkọ mi,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí; èmi yóò sì ran ègún sí orí yín, èmi yóò sì fi ìbùkún yín ré. Nítòótọ́ mó ti fi ré ná, nítorí pé, ẹ̀yin kò fi sí ọkàn yín láti bu ọlá fún mi.
Ka ok uchiko itu malongʼo, kendo ka ok uketo chunyu mar miyo nyinga luor, to abiro oro kwongʼ kuomu kendo abiro kwongʼo gweth mau. Ee, asekwongʼo-gi nimar ok useketo chunyu mondo omiya duongʼ,” Jehova Nyasaye Maratego owacho.
3 “Nítorí tiyín èmí yóò ba àwọn ọmọ yín wí, èmi ó sì fi ìgbẹ́ rẹ́ yín lójú, àní àwọn ìgbẹ́ ọrẹ ọwọ́ yín wọ̀nyí, a ó sì kó yín lọ pẹ̀lú rẹ̀.
“Abiro tieko kothu, nikech un; abiro mieno wen mag chiayo mutimonago misengni e nyasi mau e pat wengeu kendo anariembu kubakoru gi wen kamano.
4 Ẹ̀yin ó sì mọ̀ pé, èmi ni ó ti rán òfin yìí sí yín, kí májẹ̀mú mi pẹ̀lú Lefi lè tẹ̀síwájú,” ní Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Eka unungʼe ni An ema aseoronu siemni mondo singruokna kod jo-Lawi odhi nyime,” Jehova Nyasaye Maratego owacho.
5 “Májẹ̀mú mi wà pẹ̀lú rẹ̀, májẹ̀mú ti ìyè àti àlàáfíà wà pẹ̀lú rẹ̀; mo sì fi wọn fún un, nítorí bíbẹ̀rù tí ó bẹ̀rù mi, tí ẹ̀rù orúkọ mi sì bà á.
“Namiye singruokna ma en singruok mar ngima kod kwe. Singruokni ne dwaro ni mondo omiya luor, kendo notimo kamano; nochungʼ e nyima koluoro nyinga.
6 Òfin òtítọ́ wà ni ẹnu rẹ̀, a kò sì rí irọ́ ni ètè rẹ̀: ó ba mi rìn ní àlàáfíà àti ni ìdúró ṣinṣin, ó sì yí ọ̀pọ̀lọpọ̀ kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀.
Puonj madier ema ne ni e dhoge kendo miriambo kata achiel ne ok oyud e dhoge. Nowuotho koda gi kwe kod ratiro, kendo noloko ji mangʼeny oa e richo.
7 “Nítorí ètè àlùfáà ní òye láti máa pa ìmọ̀ mọ́, kí àwọn ènìyàn lè máa wá ìtọ́ni ni ẹnu rẹ̀: nítorí òun ni ìránṣẹ́ Olúwa àwọn ọmọ-ogun.
“Lew jadolo nyaka puonj rieko kendo ji onego dhi puonjre Chike Nyasaye kuome nikech en jaote mar Jehova Nyasaye Maratego.
8 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ti yapa kúrò ní ọ̀nà náà; ẹ̀yin sì ti fi ìkọ́ni yín mú ọ̀pọ̀lọpọ̀ kọsẹ̀; ẹ̀yin ti ba májẹ̀mú tí mo da pẹ̀lú Lefi jẹ́,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Kata kamano isebaro iweyo yo kendo puonjgi osemiyo ji mangʼeny ochwanyore; iseketho singruok mar jo-Lawi,” Jehova Nyasaye Maratego owacho.
9 “Nítorí náà ni èmi pẹ̀lú ṣe sọ yín di ẹ̀gàn, àti ẹni àìkàsí níwájú gbogbo ènìyàn, nítorí ẹ̀yin kò tẹ̀lé ọ̀nà mi, ṣùgbọ́n ẹ̀yin ń ṣe ojúsàájú nínú òfin.”
“Kuom mano asemiyo ojari kendo okuod wiyi e nyim ji duto, nikech ok iseluwo yorega to isedewo wangʼ ji e yore mag chik.”
10 Baba kan náà kí gbogbo wa ha ní? Ọlọ́run kan náà kọ́ ni ó dá wa bí? Nítorí kín ni àwa ha ṣe sọ májẹ̀mú àwọn baba wa di aláìmọ nípa híhu ìwà àrékérekè olúkúlùkù sí arákùnrin rẹ̀?
To donge wan duto wan gi Wuoro achiel? Donge Nyasaye achiel ema nochweyowa? Kare en angʼo momiyo waketho singruok mar wuonewa, ka waonge gi winjruok e kindwa ngʼato gi ngʼato?
11 Juda ti ń hùwà àrékérekè, a sì ti hùwà ìríra ní Israẹli àti ni Jerusalẹmu: nítorí Juda tí sọ ìwà mímọ́ Olúwa di aláìmọ́, èyí tí ó fẹ́, nípa gbígbé ọmọbìnrin ọlọ́run àjèjì ni ìyàwó.
Juda oseketho winjruok osetimo gima mono e Israel kendo e Jerusalem: Osechido kama ler mar lemo ma Jehova Nyasaye ohero kuom kendo nyar joma lamo nyiseche mamoko.
12 Ní ti ẹni tí ó ṣe èyí, ẹni tí ó wù kí ó jẹ, kí Olúwa kí ó gé e kúrò nínú àgọ́ Jakọbu, bí ó tilẹ̀ mú ẹbọ ọrẹ wá fún Olúwa àwọn ọmọ-ogun.
To kuom ngʼat matimo ma, kata bed ni en ngʼama nade, Jehova Nyasaye mad ngʼad kare oko e hembe mag Jakobo, kata bed ni okelo misengini ni Jehova Nyasaye Maratego.
13 Èyí ni ohun mìíràn tí ẹ̀yin sì túnṣe. Ẹ̀yin fi omijé bo pẹpẹ Olúwa mọ́lẹ̀. Ẹ̀yin sọkún, ẹ̀yin sì ba ara jẹ́ nítorí tì Òun kò ka ọrẹ yín sí mọ́, tàbí kí ó fi inú dídùn gba nǹkan yìí lọ́wọ́ yín.
Gimachielo mutimo ema: Upongʼo kendo mar misango mar Jehova Nyasaye gi pi wangʼu. Uywak kendo udengo nikech Jehova Nyasaye ok dew misengni ma umiye, kata bedo mamor gi gik moa lwetu.
14 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin wí pé, “Nítorí kín ní?” Nítorí Olúwa ti ṣe ẹlẹ́rìí láàrín ìwọ àti láàrín aya èwe rẹ, ẹni tí ìwọ ti ń hùwà ẹ̀tàn sí i: bẹ́ẹ̀ ni ẹnìkejì rẹ ni òun jẹ́, àti aya májẹ̀mú rẹ.
To upenjo niya, “Nangʼo?” En kamano nikech Jehova Nyasaye obedo kaka janeno e kindi kod chiegi mane ikendo ka in wuowi, nikech useketho singruok mane ni e kindu koda. Kata obedo ni en chiegi mane itimogo singruok mar kend.
15 Ọlọ́run kò ha ti ṣe wọ́n ní ọ̀kan? Ni ara àti ni ẹ̀mí tirẹ̀ ni. Èéṣe tí Ọlọ́run da yín lọ́kàn? Kí òun bá à lè wá irú-ọmọ bí ti Ọlọ́run. Nítorí náà, ẹ tọ́jú ẹ̀mí yín, ẹ má sì ṣe hùwà ẹ̀tàn sí aya èwe yín.
Donge Jehova Nyasaye oseketogi gibedo gimoro achiel? E ringruok kendo e chuny gin mage. To angʼo momiyo achiel? Nikech ne odwaro kodhi moluoro Nyasaye. Omiyo ritreuru e chunyu kendo kik ngʼato keth singruokne gi chiege mane oangorego.
16 “Ọkùnrin tí ó bá kórìíra, tí ó sì kọ ìyàwó rẹ̀,” se ìwà ipá sí ẹni tí ó yẹ kí ó dá ààbò bò, ni Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí, Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun. Nítorí náà, ẹ ṣọ́ ẹ̀mí yín, kí ẹ má ṣe hùwà ẹ̀tàn.
Jehova Nyasaye, ma Nyasach Israel wacho niya, “Amon gi weruok mantiere e kind dichwo gi chiege kendo amon gi dichwo matimo gima chalo kamano ni chiege,” Jehova Nyasaye Maratego ema owacho. Kuom mano, ritreuru e chunyu kendo kik uketh singruok.
17 Ẹ̀yin ti fi ọ̀rọ̀ yín dá Olúwa ní agara. Ṣùgbọ́n ẹ̀yin béèrè pé, “Nínú kín ni àwa fi dá a ní agara?” Nígbà tí ẹ̀yìn wí pé, “Gbogbo ẹni tí ó ṣe ibi, rere ni níwájú Olúwa, inú rẹ̀ sì dùn sí wọn,” tàbí “Níbo ni Ọlọ́run ìdájọ́ gbé wà?”
Uolo Jehova Nyasaye gi wecheu. To upenjo niya, “Ere kaka wechewa oole?” Uole kuom wacho niya, “Joma timo marach gin joma beyo e nyim wangʼ Jehova Nyasaye, kendo omor kodgi,” kata uwacho niya, “Ere Nyasaye mangʼado bura makare?”

< Malachi 2 >