< Luke 9 >

1 Ó sì pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ méjìlá jọ, ó sì fún wọn ní agbára àti àṣẹ lórí àwọn ẹ̀mí èṣù gbogbo, àti láti wo ààrùn sàn.
Avilangile vala khnche na vavili pupaminye, avapile uluhala nu vulweli uwa masetano nu kuponyiy avatamu.
2 Ó sì rán wọn lọ wàásù ìjọba Ọlọ́run, àti láti mú àwọn ọlọkùnrùn láradá.
Akhavasuha ukhuluta kuluvubilila uvutwa wa Nguluve nu khuponiya avatamu.
3 Ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ má ṣe mú nǹkan lọ́wọ́ fún àjò yín, ọ̀pá, tàbí àpò tàbí àkàrà, tàbí owó, bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ̀yin má sì ṣe ní ẹ̀wù méjì.
Akhavavula, “Mlatolaga ikhya venjaga khu njila yinyo luve lubikhi, na gupakho, nu khata na nchi ndalam naliligwanda.
4 Ní ilékílé tí ẹ̀yin bá sì wọ̀, níbẹ̀ ni kí ẹ̀yin gbé, láti ibẹ̀ ni kí ẹ̀yin sì ti jáde.
Inyumba nchoni inchiyakhiva mukhwingiela mtamage umwya isiku nchoni, mupakha upayikhiva mwichega aponu apo.
5 Iye àwọn tí kò bá si gbà yín, nígbà tí ẹ̀yin bá jáde kúrò ní ìlú náà, ẹ gbọn eruku ẹsẹ̀ yín fún ẹ̀rí sí wọn.”
Khu vala avikhuvabela ukhu vapokhela, mungehegage apo, isanyanage lndukhulu lwoni mumalunde genyo nu khunjova khuvene.”
6 Wọ́n sì lọ, wọ́n ń la ìletò kọjá wọ́n sì ń wàásù ìyìnrere, wọ́n sì ń mú ènìyàn láradá níbi gbogbo.
Vakhahega nu khuluta ikhu gendela mukhaya vuvunchova ilimenyu nu khuponiya avanu na nduvungilo.
7 Herodu tetrarki gbọ́ nǹkan gbogbo èyí tí a ṣe láti ọ̀dọ̀ rẹ̀ wá: ó sì dààmú, nítorí tí àwọn ẹlòmíràn ń wí pé, Johanu ni ó jíǹde kúrò nínú òkú,
Lino uvakhilunga u Herode, uvilolelaikhilunga, akhapulika agavonikhe, agatanchiwe lweli ulwakhuwa lyanehowiwe na vange ukhuta Yohani ikhwoncha anchukhile ukhuhuma khuguli,
8 Àwọn ẹlòmíràn sì wí pé Elijah ni ó farahàn; àwọn ẹlòmíràn sì wí pé, ọ̀kan nínú àwọn wòlíì àtijọ́ ni ó jíǹde.
Na vange, u Elia amalile ukhuhumila na vange panineye na vanyamalago avakhalale au chukhile khuvuguli.
9 Herodu sì wí pé, “Johanu ni mo ti bẹ́ lórí, ṣùgbọ́n ta ni èyí tí èmi ń gbọ́ irú nǹkan wọ̀nyí sí?” Ó sì ń fẹ́ láti rí i.
U Herode akhata, “Nakhegite khura Yohani, lino uyu viweni uviyakhiva nikhupulikha uvunchofi? Nu Herode akha landa inchila iya khuvulona U Yisu.
10 Nígbà tí àwọn aposteli sì padà dé, wọ́n ròyìn ohun gbogbo fún un tí wọ́n ti ṣe. Ó sì mú wọn, lọ sí apá kan níbi tí a ń pè ní Betisaida.
Unsikhi ugwa vuvakhiliwekhe vala avava sukhile, vakhambula khila khinu ikhivavombile. Akhavatola pipamuye, akhaluta mwene khu Bethsadia.
11 Nígbà tí ọ̀pọ̀ ènìyàn sì mọ̀, wọ́n tẹ̀lé e: ó sì gbà wọ́n, ó sì sọ̀rọ̀ ìjọba Ọlọ́run fún wọn; àwọn tí ó fẹ́ ìmúláradá, ni ó sì mú láradá.
Ulwakhuva ululundano valupulikhe vakhakhonga, nu khuvahegencha nu khunjova navo ukhuta uludeva ulwa Nguluve, nukhu vasaye avavidikhe ukhupokhiwa.
12 Nígbà tí ọjọ́ bẹ̀rẹ̀ sí rọlẹ̀, àwọn méjìlá wá, wọ́n sì wí fún un pé, “Tú ìjọ ènìyàn ká, kí wọn lè lọ sí ìletò àti sí ìlú yíká, kí wọn lè wò, àti kí wọn lè wá oúnjẹ: nítorí ijù ni àwa sá wà níhìn-ín.”
Liuchova likhasila, na vala khinjigo na vavili vakhaluta khumwene khukhunchova, “Vavahenchie avanya lulundamano walute khukhaya icha pawpimu juni vakalonde apakhugatalukha ni khyakhulya ulwakhuva puutule khulinyasi.”
13 Ṣùgbọ́n ó wí fún wọn pé, “Ẹ fi oúnjẹ fún wọn jẹ!” Wọ́n sì wí fún un pé, “Àwa kò ní ju ìṣù àkàrà márùn-ún lọ, pẹ̀lú ẹja méjì: bí kò ṣe pé àwa lọ ra oúnjẹ fún gbogbo àwọn ènìyàn wọ̀nyí.”
Ulwakhu akhavavula, “Umwe vakhanchova.”Tulivuvule ukhulutilila utuvungutulilo tuhano utwa khisyesye ne somba ivili, ulwakhuva tukhetwiluta nu khugula ikhikyakhila kya lulundamano ulwa vani.” Kwale na vagosi avaelfu vahano.
14 Nítorí àwọn ọkùnrin náà tó ìwọ̀n ẹgbẹ̀rún márùn-ún ènìyàn. Ó sì wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Kí wọ́n mú wọn jókòó lẹ́gbẹ̀ẹ̀gbẹ́, ní àràádọ́ta.”
Akhavavula avakhangi vamwene. “Muvatamikhe avanu pasi kipuga avanu havisinihanisini.
15 Wọ́n sì ṣe bẹ́ẹ̀, wọ́n sì mú gbogbo wọn jókòó.
Puvakhavomba evo pu avanu vakhatawa pasi khipugakhipuga.
16 Nígbà náà ni ó mú ìṣù àkàrà márùn-ún, àti ẹja méjì náà, nígbà tí ó gbé ojú sókè ọ̀run, ó súre sí i, ó sì bù ú, ó sì fi fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, kí wọn gbé e kalẹ̀ níwájú àwọn ènìyàn.
Akhatola ifisyesye fivili akhalola khukyanya akhafisaya nu khumenyuluna tuvinituvini, nu khuvopa avakhangi, ukhuta vavagivile avanyalulunelamano.
17 Wọ́n sì jẹ, gbogbo wọn sì yó: wọ́n ṣa agbọ̀n méjìlá jọ nínú àjẹkù tí ó kù.
Valile avanu voni vakhiguta nukhusigancha, amalagalila ga kyakhula, vakhalola nukhudincha ifitundu khinchigo na fivili.
18 Ó sì ṣe, nígbà tí ó ku òun nìkan ó gbàdúrà, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì wà lọ́dọ̀ rẹ̀: ó sì bi wọ́n pé, “Ta ni àwọn ènìyàn ń fi mí pè?”
Usikhi vuikhisaya alimwene, avakhongi vamwene vale paninie, nukhuvavuncha ukhuta, “Avanu vita une nene veni?”
19 Wọ́n sì dáhùn wí pé, “Johanu Onítẹ̀bọmi; ṣùgbọ́n ẹlòmíràn ní Elijah ni, àti àwọn ẹlòmíràn wí pé, ọ̀kan nínú àwọn wòlíì àtijọ́ ni ó jíǹde.”
Vakhanda vakta, “Vita veveYohani uvikhwoncha, na vange vinchova vita veve Eliya, nu yunge ita ulinyamalago nu uskhi ugwa khatale ulwakhuva anchokhile.”
20 Ó sì bi wọ́n pé, “Ṣùgbọ́n ta ni ẹ̀yin ń fi èmi pè?” Peteru sì dáhùn, wí pe, “Kristi ti Ọlọ́run.”
Akhavavula, “Akhala umwe mwita une niene veni?” U Petro akhatave, “Kriste ukhuhuma khwa Nguluve.”
21 Ó sì kìlọ̀ fún wọn, pé, kí wọn má ṣe sọ èyí fún ẹnìkan.
Ulwakhuva, ukhuvavunga, ukhusita ukhunchova imbombo inchi,
22 Ó sì wí pé, “Ọmọ ènìyàn yóò jìyà ohun púpọ̀, a ó sì kọ̀ ọ́ láti ọ̀dọ̀ àwọn alàgbà, olórí àlùfáà àti láti ọ̀dọ̀ àwọn akọ̀wé, a ó sì pa á, ní ọjọ́ kẹta a ó sì jí i dìde.”
Umwana va Adamu akhanchova akhata, huba ukhuvungiwa ne mbombo inyingi nu khubeliwa ne vagogolo na vavakha avakhilungana vavingi, ukhuta ibudiwa ne sikhu uyadatu inchokha.
23 Ó sì wí fún gbogbo wọn pé, “Bí ẹnìkan bá ń fẹ́ láti máa tọ̀ mí lẹ́yìn, kí ó sẹ́ ara rẹ̀, kí ó sì gbé àgbélébùú rẹ̀ ní ọjọ́ gbogbo, kí ó sì máa tọ̀ mí lẹ́yìn.
Akhavavula voni, “Akhata umunu anganogwe ukhungonga ihumye yuywa, atole ikhhikovekhano khu ifigono fyoni ang'onge.
24 Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ gba ọkàn rẹ̀ là, yóò sọ ọ́ nù: ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ ọkàn rẹ̀ nù nítorí mi, òun náà ni yóò sì gbà á là.
Uvanchage agelale ukhugapokha imitamilo ayikhugayancha, luno uvavenchaga uviikhugayancha initanilo gujamwene mukhupilila khuvuvaha wango, ayipokha imitanulo gyaniwene.
25 Nítorí pé èrè kín ni fún ènìyàn, bí ó jèrè gbogbo ayé, tí ó sì sọ ara rẹ̀ nù tàbí kí ó fi ṣòfò.
Lino khikhutanga khikhi umunu, angave ikhupila inchakhilunga nchoni, upu iyancha nukhuwopila uvuvivi munubili gwamwene?
26 Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá tijú mi, àti ọ̀rọ̀ mi, òun ni Ọmọ Ènìyàn yóò tijú rẹ̀ nígbà tí ó bá dé inú ògo tirẹ̀, àti ti baba rẹ̀, àti ti àwọn angẹli mímọ́.
Uvavenchaga ikhumbonela isoni une na mamenyu gango, khumwene, umwana va Adamu ayikhumbonela isone upuyakhiva khuvuvalanche, nu vuvalanche wa Dada na vasugwa avavalanche.
27 “Ṣùgbọ́n èmi wí fún yín nítòótọ́, ẹlòmíràn dúró níhìn-ín yìí, tí kì yóò rí ikú, títí wọn ó fi rí ìjọba Ọlọ́run.”
Lino nikhuvavula uvuwa jilweli, khuvale avannge khulwimwe savalafwa, bakhu alava ikhuvuvona uvutwa wa Nguluve.”
28 Ó sì ṣe bí ìwọ̀n ọjọ́ mẹ́jọ lẹ́yìn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí, ó mú Peteru àti Johanu àti Jakọbu, ó gun orí òkè lọ láti lọ gbàdúrà.
Neha fike isikhu khunsi khi u Yisu akhanchova amamenyu ukhuta akhavatola paninye u Petro, Yohana nu, Yakobo, vakhatoga khukyamba khukhisaya.
29 Bí ó sì ti ń gbàdúrà, àwọ̀ ojú rẹ̀ yípadà, aṣọ rẹ̀ sì funfun gbòò,
Usikhi uguale pagwisaya, uvuvonekhi wa miho wahambwikhe, nagimweyenda gwiyahambwikhe, gikhava miwalafu nukhulangala.
30 Sì kíyèsi i, àwọn ọkùnrin méjì, Mose àti Elijah, wọ́n ń bá a sọ̀rọ̀,
Lola, pale na vagosi vavili u Mose nu Eliya,
31 tí wọ́n fi ara hàn nínú ògo, wọ́n sì ń sọ̀rọ̀ ikú rẹ̀, tí òun yóò ṣe parí ní Jerusalẹmu.
valikhunchova nave, Vavonikhe khu vuvalanche. Vanchovaga ukhega kwamwene, yalembombo yakhuhegelela ukhumala khu Yelusalemu.
32 Ṣùgbọ́n ojú Peteru àti ti àwọn tí ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀ wúwo fún oorun. Nígbà tí wọ́n sì tají, wọ́n rí ògo rẹ̀, àti ti àwọn ọkùnrin méjèèjì tí ó bá a dúró.
Lino u Peteli na vanine avu vale paninie vale ni tulo inchitu. Lino vuvasisimwikhe, vakhavuvona uvuvalanche, na avagosi vawili vaimile pupaniny nu mwene.
33 Ó sì ṣe, nígbà tí wọ́n lọ kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, Peteru wí fún Jesu pé, “Olùkọ́, ó dára fún wa kí a máa gbé ìhín yìí, jẹ́ kí àwa pa àgọ́ mẹ́ta, ọ̀kan fún ìwọ, àti ọ̀kan fún Mose, àti ọ̀kan fún Elijah.” (Kò mọ èyí tí òun ń wí.)
Yikhahumila ukhuta, vuvihega khwa u Yisu, Petro akhanchova, “Itwa, lunavu khulyufwe ukhutama bahapa yinogyiwa tunchenga ifivanga vitatu. Ikyavi Yisu ikya Eliya nu Mose, “Salumanye ikhianchovaga.
34 Bí ó ti ń sọ báyìí, ìkùùkuu kan wá, ó síji bò wọ́n: ẹ̀rù sì bà wọ́n nígbà tí wọ́n ń wọ inú ìkùùkuu lọ.
Usikhi uguanchovaga ago, likhinchailifunde; likhavagubikha vakhadwadavuvilola viwonavanjonguliwe na mafunde.
35 Ohùn kan sì ti inú ìkùùkuu wá wí pé, “Èyí yìí ni àyànfẹ́ ọmọ mi: ẹ máa gbọ́ tirẹ̀.”
Inyilango ikhaluma khumafunde iyiyita, “Uywuya mwana vango uviahalilwe. Mupulikhage umwene.”
36 Nígbà tí ohùn náà sì dákẹ́, Jesu nìkan ṣoṣo ni a rí. Wọ́n sì pa á mọ́, wọn kò sì sọ ohunkóhun tí wọ́n rí fún ẹnikẹ́ni ní ọjọ́ wọ̀nyí.
Inyilango vuyiutsige mye, u Yisu akhava mwene. Vatemile miyee, khusikulyo nu khusita unchova khinu ukhwa venjaga muvala avalivwene.
37 Ó sì ṣe, ní ọjọ́ kejì, nígbà tí wọ́n sọ̀kalẹ̀ wá láti orí òkè, ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn wá pàdé rẹ̀.
Isikhu iyiyakhongile, vuvahuvunile khukyamba, lulundamano uluvaha ulwa vanu vakhagana nave.
38 Sì kíyèsi i, ọkùnrin kan nínú ìjọ ènìyàn kígbe sókè pé, “Olùkọ́ mo bẹ̀ ọ́, wo ọmọ mi: nítorí ọmọ mi kan ṣoṣo náà ni.
Lola, gosi ukhuhuma khululundamano alyelile khulimenyu, ilivaha akhata, “Imanyisi nikhukhudova uudole u mwana vango, ulwakhuva mwana vango alimwene yuyuywa.
39 Sì kíyèsi i, ẹ̀mí èṣù a máa mú un, a sì máa kígbe lójijì; a sì máa nà án tàntàn títí yóò fi yọ ìfófó lẹ́nu, a máa pa á lára, kì í tilẹ̀ ń fẹ́ fi í sílẹ̀ lọ.
Wilola inumbula injafu nu khwibata, nukwava mukhuvikha ihya nchelihano nu khuhuma amatutumelo mundomo.
40 Mo sì bẹ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ láti lé e jáde: wọn kò sì lè ṣe é.”
Lyoyihuma khulususuvelo, iyeyikhumbikhauluvavo uluvivi. Navumilinche avakhongi ukhulole ihume savawesye.”
41 Jesu sì dáhùn pé, “Ìran aláìgbàgbọ́ àti àrékérekè, èmi ó ti bá yín gbé pẹ́ tó? Èmi yóò sì ti ṣe sùúrù fún yín pẹ́ tó? Fa ọmọ rẹ wá níhìn-ín yìí.”
UYisu aandile akhanchova, “Umwe mwikhikholo ikhisakhwidikha na khila ikhiyagile, ukhuhumaga ndili nu khutama numwe nukhutolana iminjigo numwe? Undete umwana.”
42 Bí ó sì ti ń bọ̀, ẹ̀mí èṣù náà gbé e ṣánlẹ̀, ó sì nà án tàntàn. Jesu sì bá ẹ̀mí àìmọ́ náà wí, ó sì mú ọmọ náà láradá, ó sì fà á lé baba rẹ̀ lọ́wọ́.
Udimi uyu ainchaga, unumbula ikhagwisa pasi nu khusukhanje khumakha. Lino u Yisu adukhile inumbula imbivi, pu akhaponya udimi, nu khupa udadaye.
43 Ẹnu sì ya gbogbo wọn sí iṣẹ́ títóbi Ọlọ́run, ṣùgbọ́n nígbà tí hà sì ń ṣe gbogbo wọn sí ohun gbogbo tí Jesu ṣe, ó wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé,
Voni vadegile nu uvuvaha uwa uwa Nguluve. Upu vale valikhudega mambo goni ugukhavombikhe, anchovile na vakhongi vamwene,
44 “Ẹ jẹ́ kí ọ̀rọ̀ wọ̀nyí wọ̀ yín létí, nítorí a ó fi Ọmọ Ènìyàn lé àwọn ènìyàn lọ́wọ́.”
Amamenyu gatamage vuvubulukhutu mbene, ulwakhuva u Mwana va Adamu ayihumya mumovokho ga vanu.”
45 Ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ náà kò yé wọn, ó sì ṣú wọn lójú, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò sì mọ̀ ọ́n: ẹ̀rù sì ń bà wọ́n láti béèrè ìdí ọ̀rọ̀ náà.
Ulwakhuva savalumanye amamenyu ago ukhuta gafihiwe muuliho gavene mukhuta vakekhe ukulumanya, vadwadile ukhuvuncha khulimenyu ilyo.
46 Iyàn kan sì dìde láàrín wọn, ní ti ẹni tí yóò ṣe olórí nínú wọn.
Pu uvuhomelehaniye vukhatengula mumbene vene uvakhuva imbaha.
47 Nígbà tí Jesu sì mọ èrò ọkàn wọn, ó mú ọmọdé kan, ó gbé e jókòó lọ́dọ̀ rẹ̀.
Pu u Yisu vualumanyile ikhivavuncha niyaga muvumbula nchavene, akhatola umwana ndebe, nu khuvikha khumwene,
48 Ó sì wí fún wọn pé, “Ẹnikẹ́ni tí ó bá gba ọmọdé yìí nítorí orúkọ mi, ó gbà mí: àti ẹnikẹ́ni tí ó bá gbà mí, ó gba ẹni tí ó rán mi: nítorí ẹni tí ó bá kéré jù nínú gbogbo yín, òun náà ni yóò pọ̀jù.”
Pu akhata, “Umunu uvikwipila umwana udebe, khulitawa lyango, amakhile une nu vavenchaga, angamokhele une apokhile uviasuhile, umwe, veni udebe umwe mwivoni viiva imbakha”
49 Johanu sì dáhùn ó sì wí fún un pé, “Olùkọ́, àwa rí ẹnìkan ó ń fi orúkọ rẹ lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde; àwa sì dá a lẹ́kun, nítorí tí kò bá wa tọ̀ ọ́ lẹ́yìn.”
U Yohani akhanda akhata, “ITwa, twambene unu vuivinga ilungoluve khuliwa lyakho pu tukhabencha, ulwa khuva sigenda nufwe.”
50 Jesu sì wí fún un, pé, “Má ṣe dá a lẹ́kun mọ́: nítorí ẹni tí kò bá lòdì sí i yín, ó wà fún yín.”
Pu u Yisu akhambula, “Mlabenchaga, alekhe ukhuva khusana khulyomwe vinyo”
51 Nígbà tí ọjọ́ àti gbà á sókè ń súnmọ́, ó pinnu láti lọ sí Jerusalẹmu.
Usikhi vugufikhe ugwa khuluta khukyanya, amicho gamwene galikhulola khu Yelusalemo.
52 Ó sì rán àwọn ìránṣẹ́ lọ sí iwájú rẹ̀. Nígbà tí wọ́n sì lọ wọ́n wọ ìletò kan tí í ṣe ti ará Samaria láti pèsè sílẹ̀ dè é.
Akhasukha avafuasi khuvolongolo khumwenen, na vene vakhaluta nu kwingela khukhi jiji ikyava Samaria vavunganiye apakhuva.
53 Wọn kò sì gbà á, nítorí pé ó ń lọ sí Jerusalẹmu.
Pu avanu avakhusamaria savapokhele, ulwakhuva alolile anuho khu Yelusalemu.
54 Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ Jakọbu àti Johanu sì rí i, wọ́n ní, “Olúwa wa, jẹ́ kí a pe iná láti ọ̀run wá, kí a sì pa wọ́n run, bí Elijah ti ṣe?”
Avakhongi va mwene u Yakobo nu Yohani vuvalolile eli, vakhanchova, “UTwa inongwa tulamule umwoto gwikhe pasi ukhuhuma khukyanya gavanyanye?”
55 Ṣùgbọ́n Jesu yípadà, ó sì bá wọn wí.
Pu akhavasyetukhila akhava dukha.
56 Lẹ́yìn náà Jesu àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì lọ sí ìletò mìíràn.
Pu vakhaluta ikhijii iginge.
57 Bí wọ́n ti ń lọ lọ́nà, ọkùnrin kan wí fún un pé, “Olúwa, Èmi ń fẹ́ láti máa tọ̀ ọ́ lẹ́yìn ní ibikíbi tí ìwọ bá ń lọ.”
Vuviluta munjila ya vene umunu yumo akhavavula, nikhuvakhonga padebepadebe khuwiluta.”
58 Jesu sì wí fún un pé, “Àwọn kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ ní ihò, àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run sì ní ìtẹ́; ṣùgbọ́n Ọmọ Ènìyàn kò ní ibi tí yóò fi orí rẹ̀ lé.”
U Yisu akhambula akhata, “Mbweha valineliguli ifidege ifya khukyanya filine nu uvufumba, lino mwana wa Adamu imbula apakhuvikha utwe gwamwe.”
59 Ó sì wí fún ẹlòmíràn pé, “Máa tọ̀ mí lẹ́yìn.” Ṣùgbọ́n èyí wí fún un pé, “Olúwa, jẹ́ kí èmi lọ sìnkú baba mi ná.”
Pu akhambula umunu uyunge, “Ung'ongagae pu umwene akhanjova akhata, “ITwa, nidova tasi nikha siyele udada vango,”
60 Jesu sì wí fún un pé, “Jẹ́ kí àwọn òkú máa sìnkú ara wọn, ṣùgbọ́n ìwọ lọ kí o sì máa wàásù ìjọba Ọlọ́run.”
Pu umwene akhambula, “Valekhe vasilanage avafyule, vavasilye avafu, lino uve lutaga ukhanchovage uvuvakha wa Nguluve ikhilunga kyoni.”
61 Ẹlòmíràn sì wí fún un pé, “Olúwa, èmi yóò tọ̀ ọ́ lẹ́yìn ṣùgbọ́n jẹ́ kí n kọ́kọ́ lọ dágbére fún àwọn ará ilé mi.”
Pu umu uyunge akhata. “Nikhukhukhonga, Utwa, pu nita uwe isikhi tasi nikhilage khuvanu avitami khunyumba yango.”
62 Jesu sì wí fún un pé, “Kò sí ẹni, tí ó fi ọwọ́ rẹ̀ lé ohun èlò ìtulẹ̀, tí ó sì wo ẹ̀yìn, tí ó yẹ fún ìjọba Ọlọ́run.”
Pu u Yisu ambula akhata asikhuli umunu uvikwingi ncha amavokho ga mwene ukhulima nu khulola khusana uviiva nu ludeva ulwa khukyanya khwa Nguluve.”

< Luke 9 >