< Luke 9 >
1 Ó sì pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ méjìlá jọ, ó sì fún wọn ní agbára àti àṣẹ lórí àwọn ẹ̀mí èṣù gbogbo, àti láti wo ààrùn sàn.
Iyesus tatse git b́woshtswotsi b́maand s'eegdek't fo'erawwotsi kishosh, shod jam kashiy, angonat alon b́ imi.
2 Ó sì rán wọn lọ wàásù ìjọba Ọlọ́run, àti láti mú àwọn ọlọkùnrùn láradá.
Ik'i mengsti jango ash jamosh bo keewitwok'o shodetswotsno bo kashitwok'o boon b́ woshi.
3 Ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ má ṣe mú nǹkan lọ́wọ́ fún àjò yín, ọ̀pá, tàbí àpò tàbí àkàrà, tàbí owó, bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ̀yin má sì ṣe ní ẹ̀wù méjì.
Hank'owa boosh bí et, «It werindosh wotitwo eegor deshdek' k'ayere, gumbonor b́wotiyal, k'arc'itonor, galonor, gizonor, woniyet tahonor dab daamk'ayere.
4 Ní ilékílé tí ẹ̀yin bá sì wọ̀, níbẹ̀ ni kí ẹ̀yin gbé, láti ibẹ̀ ni kí ẹ̀yin sì ti jáde.
Ibo amr maa ikots it kindor gálmanitse keer it amfetsosh maa man mec'rotse teyere.
5 Iye àwọn tí kò bá si gbà yín, nígbà tí ẹ̀yin bá jáde kúrò ní ìlú náà, ẹ gbọn eruku ẹsẹ̀ yín fún ẹ̀rí sí wọn.”
Asha ashwots itn ibiyo bok'azetk wotiyalmó gálmani fakshr it amor it tufatsi k'undo tebk'rar ameree, manwere boats gaw wotitwe.»
6 Wọ́n sì lọ, wọ́n ń la ìletò kọjá wọ́n sì ń wàásù ìyìnrere, wọ́n sì ń mú ènìyàn láradá níbi gbogbo.
Mansh wosheetsots maniye kesht doo shishyo daniyfetst shodetswotsi kashiyifere gál gálotse boguurefoni.
7 Herodu tetrarki gbọ́ nǹkan gbogbo èyí tí a ṣe láti ọ̀dọ̀ rẹ̀ wá: ó sì dààmú, nítorí tí àwọn ẹlòmíràn ń wí pé, Johanu ni ó jíǹde kúrò nínú òkú,
Ash ik iko «Gpfo Yohans k'irotse k'az tuure» ett bo keewirwotse Gelil dats k'eezfo Herodis Iyesus fints jamo b́ shishor daand b́wutsi.
8 Àwọn ẹlòmíràn sì wí pé Elijah ni ó farahàn; àwọn ẹlòmíràn sì wí pé, ọ̀kan nínú àwọn wòlíì àtijọ́ ni ó jíǹde.
Mank'o ik ikwots «Nebiyo Eliyas aanat waare, » bo etor k'atswotsmó «Shints nebiywotsitse iko k'irotse k'az tuure, » bo etiri.
9 Herodu sì wí pé, “Johanu ni mo ti bẹ́ lórí, ṣùgbọ́n ta ni èyí tí èmi ń gbọ́ irú nǹkan wọ̀nyí sí?” Ó sì ń fẹ́ láti rí i.
Herodiswe b́ kaaton «Taa Yohans tooko k'ut'rere, eshe, jaman k'alirwe ett keeweyirwo kone eshna?» bí etfo. Bín bek'ono b́ tewnfo.
10 Nígbà tí àwọn aposteli sì padà dé, wọ́n ròyìn ohun gbogbo fún un tí wọ́n ti ṣe. Ó sì mú wọn, lọ sí apá kan níbi tí a ń pè ní Betisaida.
B́woshefwots bowoshetsoke aani wáát bok'alts jamo Iyesussh bokeewi. Bíwere Betesayida eteets kitu ganoke fa'a jokats bo aali dek't bíami.
11 Nígbà tí ọ̀pọ̀ ènìyàn sì mọ̀, wọ́n tẹ̀lé e: ó sì gbà wọ́n, ó sì sọ̀rọ̀ ìjọba Ọlọ́run fún wọn; àwọn tí ó fẹ́ ìmúláradá, ni ó sì mú láradá.
Ash ashonwre Iyesus beyoko áwok b́woto bo daniyakon b́shuutso shoy dek't botuw, bíwere boon dek't Ik'i mengsti jango boosh b́ daniyi, boshodatse kasho geeyat waats jamwotsno bo shodotse b́ kashi.
12 Nígbà tí ọjọ́ bẹ̀rẹ̀ sí rọlẹ̀, àwọn méjìlá wá, wọ́n sì wí fún un pé, “Tú ìjọ ènìyàn ká, kí wọn lè lọ sí ìletò àti sí ìlú yíká, kí wọn lè wò, àti kí wọn lè wá oúnjẹ: nítorí ijù ni àwa sá wà níhìn-ín.”
Aawo ilosh bí'etfere, b́danif tatse gitwots Iyesus maants t'int «No beyirwokanwo woorwere, eshe ash ashuwotsi gúranatse fa'a kitwotsnat gat'eriwotsits amr mishonat k'eyokon gee bodek'etwok'o fakshk'rowe, » bo et.
13 Ṣùgbọ́n ó wí fún wọn pé, “Ẹ fi oúnjẹ fún wọn jẹ!” Wọ́n sì wí fún un pé, “Àwa kò ní ju ìṣù àkàrà márùn-ún lọ, pẹ̀lú ẹja méjì: bí kò ṣe pé àwa lọ ra oúnjẹ fún gbogbo àwọn ènìyàn wọ̀nyí.”
Iyesusmó «It it tookon bometwo boosh imere, » bí eti. Bowere «Noo nodetsiye úts mishunat git mus' mec'riye, man b́wottsotse no kewiyala bako jam ashaansh boratse, » bo eti.
14 Nítorí àwọn ọkùnrin náà tó ìwọ̀n ẹgbẹ̀rún márùn-ún ènìyàn. Ó sì wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Kí wọ́n mú wọn jókòó lẹ́gbẹ̀ẹ̀gbẹ́, ní àràádọ́ta.”
Ash ashonwere úts kumk'oyi b́tesh. Iyesus b́ danifwotssh «Ash asho b'alk'ts b'alk'tson kayide'er bo bedek'etwoko woshwere» bíet.
15 Wọ́n sì ṣe bẹ́ẹ̀, wọ́n sì mú gbogbo wọn jókòó.
B́ danifwotswere bí'ettsuk'o ash ashuwotsi bobetwok'o woshbok'ri.
16 Nígbà náà ni ó mú ìṣù àkàrà márùn-ún, àti ẹja méjì náà, nígbà tí ó gbé ojú sókè ọ̀run, ó súre sí i, ó sì bù ú, ó sì fi fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, kí wọn gbé e kalẹ̀ níwájú àwọn ènìyàn.
Maniyere il Iyesus úts mishwotsnat mus' gitwotsn k'a'udek't daromaants kááwdek't s'iilt Ik'o b́údi, tishde'er ash ashosh bokayitwok'o b́ danifwotssh b́ ími.
17 Wọ́n sì jẹ, gbogbo wọn sì yó: wọ́n ṣa agbọ̀n méjìlá jọ nínú àjẹkù tí ó kù.
Jametswots maat bowori, b́ danifwots ash mááre oorts mishi fed'o tatse git ooshi s'eeno bo k'a'úwi.
18 Ó sì ṣe, nígbà tí ó ku òun nìkan ó gbàdúrà, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì wà lọ́dọ̀ rẹ̀: ó sì bi wọ́n pé, “Ta ni àwọn ènìyàn ń fi mí pè?”
Ik aaw Iyesus bí'yal Ik'o b́ k'onfere b́ danirwots waat bínton be bodek', bíwere, «Ash asho taan koni etfno?» ett bíaat.
19 Wọ́n sì dáhùn wí pé, “Johanu Onítẹ̀bọmi; ṣùgbọ́n ẹlòmíràn ní Elijah ni, àti àwọn ẹlòmíràn wí pé, ọ̀kan nínú àwọn wòlíì àtijọ́ ni ó jíǹde.”
Bowere «Ik iko ‹Gupfo Yohansiye, › k'atswots ‹Eliyasiye, › etfne neesha, ‹Yoots nebiyiwotsitsi iko k'irotse tuure, › etirwotsu fa'ane, » ett bísh bo aaniyi.
20 Ó sì bi wọ́n pé, “Ṣùgbọ́n ta ni ẹ̀yin ń fi èmi pè?” Peteru sì dáhùn, wí pe, “Kristi ti Ọlọ́run.”
Itmó eshe, «Taan koni etfte?» et boon bí aati. P'et'roswere, «Nee Ik'i mesihiyo neene, » ett bísh bí aaniy.
21 Ó sì kìlọ̀ fún wọn, pé, kí wọn má ṣe sọ èyí fún ẹnìkan.
Iyesusere han konshor bokeewrawok'o kup'idek't b́ keewi.
22 Ó sì wí pé, “Ọmọ ènìyàn yóò jìyà ohun púpọ̀, a ó sì kọ̀ ọ́ láti ọ̀dọ̀ àwọn alàgbà, olórí àlùfáà àti láti ọ̀dọ̀ àwọn akọ̀wé, a ó sì pa á, ní ọjọ́ kẹta a ó sì jí i dìde.”
Manats dabt Iyesus b́ danifwotssh hank'owa bí'et, «Ash na'o gond bek'o ayide bí'ats b́bodo jinatse, eenashwotsnat kahniy naashwotsn, Muse nemo danifwotsoke gac'etwe, úd'etwe, b́wotiyalor keezl aawon k'irotse tuwitwe.»
23 Ó sì wí fún gbogbo wọn pé, “Bí ẹnìkan bá ń fẹ́ láti máa tọ̀ mí lẹ́yìn, kí ó sẹ́ ara rẹ̀, kí ó sì gbé àgbélébùú rẹ̀ ní ọjọ́ gbogbo, kí ó sì máa tọ̀ mí lẹ́yìn.
Jametswotssh hank'wa bíet, «T shuuts waa geetso b́ beyal b́took keewo juk'rowe, aaw aawonowere b́ mask'aliyo kurde t shuutso sha'owa
24 Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ gba ọkàn rẹ̀ là, yóò sọ ọ́ nù: ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ ọkàn rẹ̀ nù nítorí mi, òun náà ni yóò sì gbà á là.
Taayere bogo b́ kasho shawsh geyitu jametswots t'ut'etúno, taasha err b́ kasho beshide'er imetwonmó ooridek'etwe.
25 Nítorí pé èrè kín ni fún ènìyàn, bí ó jèrè gbogbo ayé, tí ó sì sọ ara rẹ̀ nù tàbí kí ó fi ṣòfò.
Asho datsatsi gaal jamo b́datsiyal, b́ kashunmó b́ t'afiyal eege bísh b́k'aliti?
26 Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá tijú mi, àti ọ̀rọ̀ mi, òun ni Ọmọ Ènìyàn yóò tijú rẹ̀ nígbà tí ó bá dé inú ògo tirẹ̀, àti ti baba rẹ̀, àti ti àwọn angẹli mímọ́.
Taanat tdanits daniyi jangatse tuutson jitsitu jámo ash na'o b́mangonat b́ nih mangon, aani b́ melaki S'aynwots mangon b́ woor b́jangatse jitsitwe.
27 “Ṣùgbọ́n èmi wí fún yín nítòótọ́, ẹlòmíràn dúró níhìn-ín yìí, tí kì yóò rí ikú, títí wọn ó fi rí ìjọba Ọlọ́run.”
Arikoniye itsh t keewiri, and hanoke fa'úwotsitse Ik'i megstu bo bek'fetsosh k'irrawwots fa'ane.»
28 Ó sì ṣe bí ìwọ̀n ọjọ́ mẹ́jọ lẹ́yìn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí, ó mú Peteru àti Johanu àti Jakọbu, ó gun orí òkè lọ láti lọ gbàdúrà.
Iyesus han b́keewtsi shmt aawe hakon P'et'rosi, Yohansnat Yak'obn jishdek't Ik' k'onosh gur iko abaats keshb́dek'i.
29 Bí ó sì ti ń gbàdúrà, àwọ̀ ojú rẹ̀ yípadà, aṣọ rẹ̀ sì funfun gbòò,
Ik'o b́k'onfere bí'aro wone b́ wtsi, b́ tahonuwer nas' wotat b́ goli.
30 Sì kíyèsi i, àwọn ọkùnrin méjì, Mose àti Elijah, wọ́n ń bá a sọ̀rọ̀,
Mann! gawerawon git ashuwots waat bínton bokeweyir, boowere Musenat Elyasna bo teshi.
31 tí wọ́n fi ara hàn nínú ògo, wọ́n sì ń sọ̀rọ̀ ikú rẹ̀, tí òun yóò ṣe parí ní Jerusalẹmu.
Mangon be'eyat keewefetst bo teshtsonwere, Iyesus Iyerusalemitse gond bek'o bí'ats b́ bodetwok'onat b́ k'iritwok'ona b́teshi.
32 Ṣùgbọ́n ojú Peteru àti ti àwọn tí ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀ wúwo fún oorun. Nígbà tí wọ́n sì tají, wọ́n rí ògo rẹ̀, àti ti àwọn ọkùnrin méjèèjì tí ó bá a dúró.
Manór P'et'rosnat b́ tohwotsn tokron maawutsat k'egutserno boteshi, tokrotse bo tuwtsok'nmo Iyesus mangonat bínton teshts ash gitwotsn bo bek'i.
33 Ó sì ṣe, nígbà tí wọ́n lọ kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, Peteru wí fún Jesu pé, “Olùkọ́, ó dára fún wa kí a máa gbé ìhín yìí, jẹ́ kí àwa pa àgọ́ mẹ́ta, ọ̀kan fún ìwọ, àti ọ̀kan fún Mose, àti ọ̀kan fún Elijah.” (Kò mọ èyí tí òun ń wí.)
Ash gitwots Iyesusatse k'aleyat bo amtsok'on P'et'ros Iyesussh «Danifono, hanoke beyo noosh shenge, eshe iko neesh, iko Musesh, ikono Eliyassh, keez gofuwotsi áá de'one!» bí et, P'et'ros han bietoor b́ keewirwo danatse.
34 Bí ó ti ń sọ báyìí, ìkùùkuu kan wá, ó síji bò wọ́n: ẹ̀rù sì bà wọ́n nígbà tí wọ́n ń wọ inú ìkùùkuu lọ.
P'et'ros man keewoke b́befre daawno waat boon degbdek', dawnonwere boon degb́dek'tsok'on shat bowtsi.
35 Ohùn kan sì ti inú ìkùùkuu wá wí pé, “Èyí yìí ni àyànfẹ́ ọmọ mi: ẹ máa gbọ́ tirẹ̀.”
Dawnmanitsno, «T marat'tso t na'o haniye, bín k'ewere!» etiru k'ááro b́ waa.
36 Nígbà tí ohùn náà sì dákẹ́, Jesu nìkan ṣoṣo ni a rí. Wọ́n sì pa á mọ́, wọn kò sì sọ ohunkóhun tí wọ́n rí fún ẹnikẹ́ni ní ọjọ́ wọ̀nyí.
K'armanwere b́ shisheyahakon Iyesus bíaali wotat b́ daatseyi, b́ danifwotswere bo bek'ts jamo konshor bo kewrawon s'ket be bowts.
37 Ó sì ṣe, ní ọjọ́ kejì, nígbà tí wọ́n sọ̀kalẹ̀ wá láti orí òkè, ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn wá pàdé rẹ̀.
Yatsok'on Iyesusnat b́ danif keezwotsn guri abaatse bo oot'tsok'on ay asho Iyesusi amt gonkbodek'i.
38 Sì kíyèsi i, ọkùnrin kan nínú ìjọ ènìyàn kígbe sókè pé, “Olùkọ́ mo bẹ̀ ọ́, wo ọmọ mi: nítorí ọmọ mi kan ṣoṣo náà ni.
Ash ash dagotse ash iko hank'o ett b́kuh! «Danifono! na'an taash iks'uz b́wottsotse taash n kashiytwok'o neen k'onre,
39 Sì kíyèsi i, ẹ̀mí èṣù a máa mú un, a sì máa kígbe lójijì; a sì máa nà án tàntàn títí yóò fi yọ ìfófó lẹ́nu, a máa pa á lára, kì í tilẹ̀ ń fẹ́ fi í sílẹ̀ lọ.
Hambe! Kim shayiran gawerawo detsdek't b́ kuhirye, datsats dikdek't úmbo kishifetst b́ s'ik'iyriye, bí atsono gaawit gondo b́ bek'shiyakon b́fakshfoni.
40 Mo sì bẹ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ láti lé e jáde: wọn kò sì lè ṣe é.”
Kim shayiran bo kishitwok'o n danifwotssh keewre b́tesh, ernmó falratsne.»
41 Jesu sì dáhùn pé, “Ìran aláìgbàgbọ́ àti àrékérekè, èmi ó ti bá yín gbé pẹ́ tó? Èmi yóò sì ti ṣe sùúrù fún yín pẹ́ tó? Fa ọmọ rẹ wá níhìn-ín yìí.”
Iyesuswere hanko bí et «It amaneraw k'uurts s'oot'wotso! awrifetsone itnton t beeti? awrifetsoshe it keewo t k'amiti? aab n na'o hakan de'ewowe.»
42 Bí ó sì ti ń bọ̀, ẹ̀mí èṣù náà gbé e ṣánlẹ̀, ó sì nà án tàntàn. Jesu sì bá ẹ̀mí àìmọ́ náà wí, ó sì mú ọmọ náà láradá, ó sì fà á lé baba rẹ̀ lọ́wọ́.
Na'onwere Iyesus maants b́ t'intsok'on fo'erawo datsats dikdek't b́ s'ik'i, Iyesusmó kim shayirman hadat, na'onowere kashidek't b́ nihsh imb́k'ri.
43 Ẹnu sì ya gbogbo wọn sí iṣẹ́ títóbi Ọlọ́run, ṣùgbọ́n nígbà tí hà sì ń ṣe gbogbo wọn sí ohun gbogbo tí Jesu ṣe, ó wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé,
Ash jamonwere Ik'i een ango bobek'tsotse bo adi. Jametsuwots Iyesus b́ k'alts keewmaanatse tuutson adoke bobefere b́ danifwotssh hank'o bíeti,
44 “Ẹ jẹ́ kí ọ̀rọ̀ wọ̀nyí wọ̀ yín létí, nítorí a ó fi Ọmọ Ènìyàn lé àwọn ènìyàn lọ́wọ́.”
«Itsh tkeewiru keewan nibn de t'iwintsde'ere! Hambe, Ash Na'o ashuwotssh beshide imetwe.»
45 Ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ náà kò yé wọn, ó sì ṣú wọn lójú, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò sì mọ̀ ọ́n: ẹ̀rù sì ń bà wọ́n láti béèrè ìdí ọ̀rọ̀ náà.
Boomó keewman t'iwintsde'atsno, b́keewirmanwere boosh aashgutsatni b́tesh, bín aatoshowere shat bowtsi.
46 Iyàn kan sì dìde láàrín wọn, ní ti ẹni tí yóò ṣe olórí nínú wọn.
B́ danifwots «No únetsitse bogo kone?» ett moosho tuuz bok'ri.
47 Nígbà tí Jesu sì mọ èrò ọkàn wọn, ó mú ọmọdé kan, ó gbé e jókòó lọ́dọ̀ rẹ̀.
Iyesusmó bo nibotse bo gawirwo dank'rat na'i marmat' iko dek' waat b́ ganok need'i b́k'ri,
48 Ó sì wí fún wọn pé, “Ẹnikẹ́ni tí ó bá gba ọmọdé yìí nítorí orúkọ mi, ó gbà mí: àti ẹnikẹ́ni tí ó bá gbà mí, ó gba ẹni tí ó rán mi: nítorí ẹni tí ó bá kéré jù nínú gbogbo yín, òun náà ni yóò pọ̀jù.”
Bíwere «Na'i marmat'han taasha err dek'etwo taane b́ dek'iy, taan dek'ts jamonwere taan woshtsonye bo dek'iye. Ititse it jametswotsitse dashtso bí jamoniyere bogee b́ wotitye, » bí et.
49 Johanu sì dáhùn ó sì wí fún un pé, “Olùkọ́, àwa rí ẹnìkan ó ń fi orúkọ rẹ lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde; àwa sì dá a lẹ́kun, nítorí tí kò bá wa tọ̀ ọ́ lẹ́yìn.”
Maniye hakon Yohans Iyesussh, «Danifono, ash iko n shútson fo'erawo b́ kishfere nobek'i, ernmó noonton b́woterawotse bazi nok'ri, » bíet.
50 Jesu sì wí fún un, pé, “Má ṣe dá a lẹ́kun mọ́: nítorí ẹni tí kò bá lòdì sí i yín, ó wà fún yín.”
Iyesuswere «Iti k'eferaw jamo it maants b́wottsotse k'ayere, bazik'ayere!» bí et.
51 Nígbà tí ọjọ́ àti gbà á sókè ń súnmọ́, ó pinnu láti lọ sí Jerusalẹmu.
Iyesusi daromadan b́ keshet aawo t'infere b́ waatsok'on Iyerusalem maants amoosh k'ut'dek't b́ tuwi.
52 Ó sì rán àwọn ìránṣẹ́ lọ sí iwájú rẹ̀. Nígbà tí wọ́n sì lọ wọ́n wọ ìletò kan tí í ṣe ti ará Samaria láti pèsè sílẹ̀ dè é.
Bíyere shin shino amet woshetawotsi woshb́k'ri, boowere jam keewo k'aniyosh Semaritse daatsets gal iku maants bo ami.
53 Wọn kò sì gbà á, nítorí pé ó ń lọ sí Jerusalẹmu.
Ernmó bí mann beshar Iyerusalemi bí'ametuwok'o bo dantsotse gal manitsi ashuwots bín dek'o geratsno bo tesh.
54 Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ Jakọbu àti Johanu sì rí i, wọ́n ní, “Olúwa wa, jẹ́ kí a pe iná láti ọ̀run wá, kí a sì pa wọ́n run, bí Elijah ti ṣe?”
B́danifuwots Yak'obnat Yohansn man bo bek'tsok'on, «Doonzono! darotse tawo ood'r ashaanotsi mits b́ bazetwok'o no k'alish eekineya?» bo et.
55 Ṣùgbọ́n Jesu yípadà, ó sì bá wọn wí.
Iyesusmó bo maants wongr ett aanat boon b́ hadi. [It aaw naari shayirokik it wottsok'o danatste, ash na'o b́awa ash kash worya bako, t'afiyaliye.]
56 Lẹ́yìn náà Jesu àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì lọ sí ìletò mìíràn.
Manoknowere tuut k'osh gaalo maants k'az bo ami.
57 Bí wọ́n ti ń lọ lọ́nà, ọkùnrin kan wí fún un pé, “Olúwa, Èmi ń fẹ́ láti máa tọ̀ ọ́ lẹ́yìn ní ibikíbi tí ìwọ bá ń lọ.”
Iyesusnat b́ danifwots weerindatse bo sha'efere ash iko Iyesussh «Taa ni'amiru jamok n shuutso shoyde'er amoosh geefe, » bí et.
58 Jesu sì wí fún un pé, “Àwọn kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ ní ihò, àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run sì ní ìtẹ́; ṣùgbọ́n Ọmọ Ènìyàn kò ní ibi tí yóò fi orí rẹ̀ lé.”
Iyesuswere «Waangwots gop'o detsfne, daritsi kafwotswere kúto detsfne, ashna'onmó dab b́ tooku bits b́ gedetwok wotts bewoku deshatse, » ett bísh bíaaniy.
59 Ó sì wí fún ẹlòmíràn pé, “Máa tọ̀ mí lẹ́yìn.” Ṣùgbọ́n èyí wí fún un pé, “Olúwa, jẹ́ kí èmi lọ sìnkú baba mi ná.”
K'osh ashosho, «T shuutso wowe» bí et. Ashmanmó «T doonzo! shino amr t nihi duh tdek'ish taash eekowe, » bi et.
60 Jesu sì wí fún un pé, “Jẹ́ kí àwọn òkú máa sìnkú ara wọn, ṣùgbọ́n ìwọ lọ kí o sì máa wàásù ìjọba Ọlọ́run.”
Iyesuswere «K'irtswotsi k'ayk'rowe, k'irts bokuwotsi duhde'enee, nemon amr Ik'i mengsti jango daniwe!» ett bí aaniyi.
61 Ẹlòmíràn sì wí fún un pé, “Olúwa, èmi yóò tọ̀ ọ́ lẹ́yìn ṣùgbọ́n jẹ́ kí n kọ́kọ́ lọ dágbére fún àwọn ará ilé mi.”
Maniye il k'osh ash iko «Doonzono, taa neenton sha'o geefe, wotowa bako shino amr t meyitsi ashuwotsi jamir t weetwok'o taash eekowe, » bí eti.
62 Jesu sì wí fún un pé, “Kò sí ẹni, tí ó fi ọwọ́ rẹ̀ lé ohun èlò ìtulẹ̀, tí ó sì wo ẹ̀yìn, tí ó yẹ fún ìjọba Ọlọ́run.”
Iyesuswere «Goshosh hordo kishon deshde'er shuutso maants s'iliru asho Ik'i mengstosh wotitkaliye, » et bíaanyi.