< Luke 8 >

1 Ó sì ṣe lẹ́yìn náà, tí ó ń lá gbogbo ìlú àti ìletò kọjá lọ, ó ń wàásù, ó ń ròyìn ayọ̀ ìjọba Ọlọ́run. Àwọn méjìlá sì ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀,
ⲁ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲥϣⲱⲡⲓ ⲙⲉⲛⲉⲛⲥⲁ ⲛⲁⲓ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲑⲟϥ ⲛⲁϥⲙⲟϣⲓ ⲕⲁⲧⲁ ⲃⲁⲕⲓ ⲛⲉⲙ ϯⲙⲓ ⲉϥϩⲓⲱⲓϣ ⲟⲩⲟϩ ⲉϥϩⲓϣⲉⲛⲛⲟⲩϥⲓ ⲛϯⲙⲉⲧⲟⲩⲣⲟ ⳿ⲛⲧⲉ ⲫϯ ⲟⲩⲟϩ ⲡⲓⲓ̅ⲃ̅ ⲉⲩⲛⲉⲙⲁϥ.
2 àti àwọn obìnrin kan, tí a ti mú láradá kúrò lọ́wọ́ àwọn ẹ̀mí búburú àti nínú àìlera wọn, Maria tí a ń pè ní Magdalene, lára ẹni tí ẹ̀mí èṣù méje ti jáde kúrò.
ⲃ̅ⲛⲉⲙ ϩⲁⲛⲕⲉϩⲓ⳿ⲟⲙⲓ ⲛⲏⲉⲧⲁϥⲉⲣⲫⲁϧⲣⲓ ⳿ⲉⲣⲱⲟⲩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ϩⲁⲛⲡ͞ⲛⲁ̅ ⲉⲩϩⲱⲟⲩ ⲛⲉⲙ ϩⲁⲛϣⲱⲛⲓ ⲙⲁⲣⲓ⳿ⲁ ⲑⲏ ⲉⲧⲟⲩⲙⲟⲩϯ ⳿ⲉⲣⲟⲥ ϫⲉ ϯⲙⲁⲅⲇⲁⲗⲓⲛⲏ ⲑⲏ ⲉⲧⲁϥϩⲓ ⲡⲓⲍ̅ ⳿ⲛⲇⲉⲙⲱⲛ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϩⲓⲱⲧⲥ.
3 Àti Joanna aya Kusa tí í ṣe ìríjú Herodu, àti Susana, àti àwọn púpọ̀ mìíràn, tí wọ́n ń ṣe ìránṣẹ́ fún un nínú ohun ìní wọn.
ⲅ̅ⲛⲉⲙ ⲓⲱⲁⲛⲛⲁ ⳿ⲧ⳿ⲥϩⲓⲙⲓ ⲛⲭⲟⲩⲍⲁ ⲡⲓ⳿ⲉⲡⲓ⳿ⲧⲣⲟⲡⲟⲥ ⳿ⲛⲧⲉ ⲏⲣⲱⲇⲏⲥ ⲛⲉⲙ ⲥⲟⲩⲥⲁⲛⲛⲁ ⲛⲉⲙ ϩⲁⲛⲕⲉⲭⲱⲟⲩⲛⲓ ⲉⲩⲟϣ ⲛⲏ ⳿ⲉⲛⲁⲩϣⲉⲙϣⲓ ⳿ⲙⲙⲟϥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲛⲟⲩϩⲩⲡⲁⲣⲭⲟⲛⲧ⳿ⲁ.
4 Nígbà tí ọ̀pọ̀ ìjọ ènìyàn péjọpọ̀, àwọn ènìyàn láti ìlú gbogbo sì tọ̀ ọ́ wá, ó fi òwe bá wọn sọ̀rọ̀ pé,
ⲇ̅ⲉϥⲑⲟⲩⲏⲧ ⲇⲉ ⳿ⲛϫⲉ ⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲙⲙⲏϣ ⲛⲉⲙ ⲛⲏ ⳿ⲉⲛⲁⲩⲛⲏⲟⲩ ϩⲁⲣⲟϥ ⲕⲁⲧⲁ ⲃⲁⲕⲓ ⲡⲉϫⲁϥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϩⲓⲧⲉⲛ ⲟⲩⲡⲁⲣⲁⲃⲟⲗⲏ.
5 “Afúnrúgbìn kan jáde lọ láti fún irúgbìn rẹ̀: bí ó sì ti ń fúnrúgbìn, díẹ̀ bọ́ sí ẹ̀bá ọ̀nà, a sì tẹ̀ ẹ́ mọ́lẹ̀, àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run sì ṣà á jẹ.
ⲉ̅ⲁϥ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲛϫⲉ ⲫⲏⲉⲧⲥⲓϯ ⳿ⲉⲥⲓϯ ⳿ⲙⲡⲉϥ⳿ϫⲣⲟϫ ⲟⲩⲟϩ ϧⲉⲛ ⳿ⲡϫⲓⲛ⳿ⲑⲣⲉϥⲥⲓϯ ⲟⲩⲁⲓ ⲙⲉⲛ ⲁϥϩⲉⲓ ϧⲁⲧⲉⲛ ⲡⲓⲙⲱⲓⲧ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩϩⲉⲙϩⲱⲙϥ ⲟⲩⲟϩ ⲛⲓϩⲁⲗⲁϯ ⳿ⲛⲧⲉ ⲧⲫⲉ ⲁⲩⲟⲩⲟⲙϥ.
6 Òmíràn sì bọ́ sórí àpáta; bí ó sì ti hù jáde, ó gbẹ nítorí tí kò ní omi.
ⲋ̅ⲟⲩⲟϩ ⲕⲉⲟⲩⲁⲓ ⲁϥϩⲉⲓ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⲟⲩⲡⲉⲧⲣⲁ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥⲣⲱⲧ ⲁϥϣⲱⲟⲩ⳿ⲓ ⲉⲑⲃⲉϫⲉ ⳿ⲙⲙⲟⲛⲧⲉϥ ϭⲛⲟⲛⲓ ⳿ⲙⲙⲁⲩ.
7 Òmíràn sì bọ́ sínú ẹ̀gún; ẹ̀gún sì dàgbà pẹ̀lú rẹ̀ sókè, ó sì fún un pa.
ⲍ̅ⲟⲩⲟϩ ⲉⲟⲩⲁⲓ ⲁϥϩⲉⲓ ϧⲉⲛ ⳿ⲑⲙⲏϯ ⳿ⲛⲛⲓⲥⲟⲩⲣⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲉⲧⲁϥⲣⲱⲧ ⲛⲉⲙⲁϥ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲓⲥⲟⲩⲣⲓ ⲁⲩⲟϫϩϥ.
8 Òmíràn sì bọ́ sí ilẹ̀ rere, ó sì hù sókè, ó sì so èso ọ̀rọ̀ọ̀rún ju èyí ti a gbin lọ.” Nígbà tí ó sì wí nǹkan wọ̀nyí tán, ó pariwo sókè pé, “Ẹni tí ó bá ní etí láti fi gbọ́, kí ó gbọ́!”
ⲏ̅ⲟⲩⲟϩ ⲕⲉⲟⲩⲁⲓ ⲁϥϩⲉⲓ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⲡⲓⲕⲁϩⲓ ⲉⲑⲛⲁⲛⲉϥ ⲩⲟϩ ⲉⲧⲁϥⲣⲱⲧ ⲁϥ⳿ⲉⲛ ⲟⲩⲧⲁϩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲛⲣ̅ ⳿ⲛⲕⲱⲃ ⲛⲁⲓ ⲉϥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲱⲟⲩ ⲛⲁϥⲙⲟⲩϯ ⲡⲉ ϫⲉ ⲫⲏⲉⲧⲉ ⲟⲩⲟⲛ ⲟⲩⲙⲁϣϫ ⳿ⲙⲙⲟϥ ⳿ⲉⲥⲱⲧⲉⲙ ⲁⲣⲉϥⲥⲱⲧⲉⲙ.
9 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì bi í léèrè, pé, “Kí ni a lè mọ òwe yìí sí?”
ⲑ̅ⲛⲁⲩϣⲓⲛⲓ ⲇⲉ ⳿ⲙⲙⲟϥ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲉϥⲙⲁⲑⲏⲧⲏⲥ ϫⲉ ⲟⲩ ⲧⲉ ⲧⲁⲓⲡⲁⲣⲁⲃⲟⲗⲏ.
10 Ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ni a fi fún láti mọ ohun ìjìnlẹ̀ ìjọba Ọlọ́run; ṣùgbọ́n fún àwọn ẹlòmíràn wọn yóò jẹ́ òwe, pé ní rí rí, “‘kí wọn má ba à rí, àti ní gbígbọ́ kí ó má lè yé wọn.’
ⲓ̅⳿ⲛⲑⲟϥ ⲇⲉ ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲱⲟⲩ ϫⲉ ⳿ⲛⲑⲱⲧⲉⲛ ⲉⲧⲉⲥⲧⲟⲓ ⲛⲱⲧⲉⲛ ⳿ⲉ⳿ⲉⲙⲓ ⳿ⲉⲛⲓⲙⲩⲥⲧⲏⲣⲓⲟⲛ ⳿ⲛⲧⲉ ϯⲙⲉⲧⲟⲩⲣⲟ ⳿ⲛⲧⲉ ⲫϯ ⳿ⲡⲥⲱϫⲡ ⲇⲉ ϧⲉⲛ ϩⲁⲛⲡⲁⲣⲁⲃⲟⲗⲏ ϩⲓⲛⲁ ⲉⲩⲛⲁⲩ ⳿ⲛⲧⲟⲩ⳿ϣⲧⲉⲙⲛⲁⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲩⲥⲱⲧⲉⲙ ⳿ⲛⲧⲟⲩ⳿ϣⲧⲉⲙⲥⲱⲧⲉⲙ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲧⲟⲩ⳿ϣⲧⲉⲙⲕⲁϯ.
11 “Ǹjẹ́ òwe náà ni èyí: irúgbìn ni ọ̀rọ̀ Ọlọ́run.
ⲓ̅ⲁ̅ϯⲡⲁⲣⲁⲃⲟⲗⲏ ⲇⲉ ⲑⲁⲓ ⲧⲉ ⲡⲓ⳿ϫⲣⲟϫ ⲡⲉ ⲡⲓⲥⲁϫⲓ ⳿ⲛⲧⲉ ⲫϯ.
12 Àwọn ti ẹ̀bá ọ̀nà ni àwọn tí ó gbọ́ nígbà náà ni èṣù wá ó sì mú ọ̀rọ̀ náà kúrò ní ọkàn wọn, kí wọn má ba à gbàgbọ́, kí a sì gbà wọ́n là.
ⲓ̅ⲃ̅ⲛⲏ ⲇⲉ ⲧϧⲁⲧⲉⲛ ⲡⲓⲙⲱⲓⲧ ⲛⲉ ⲛⲏⲉⲧⲥⲱⲧⲉⲙ ⳿ⲓⲧⲁ ϣⲁϥ⳿ⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲡⲓⲇⲓ⳿ⲁⲃⲟⲗⲟⲥ ⲟⲩⲟϩ ϣⲁϥⲱⲗⲓ ⳿ⲙⲡⲓⲥⲁϫⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲡⲟⲩϩⲏ ⲧ ϩⲓⲛⲁ ⲙⲏⲡⲱⲥ ⳿ⲛⲥⲉⲛⲁϩϯ ⲩⲟϩ ⳿ⲛⲥⲉⲛⲟϩⲉⲙ.
13 Àwọn ti orí àpáta ni àwọn, tí wọ́n gbọ́, wọ́n fi ayọ̀ gba ọ̀rọ̀ náà, àwọn wọ̀nyí kò sì ní gbòǹgbò, wọ́n á gbàgbọ́ fún sá à díẹ̀; nígbà ìdánwò, wọn á padà sẹ́yìn.
ⲓ̅ⲅ̅ⲛⲏ ⲇⲉ ⲉⲧϩⲓϫⲉⲛ ϯⲡⲉⲧⲣⲁ ⲛⲉ ⲛⲏ ϩⲟⲧⲁⲛ ⲁⲩϣⲁⲛⲥⲱⲧⲉⲙ ϣⲁⲩϣⲉⲡ ⲡⲓⲥⲁϫⲓ ⳿ⲉⲣⲱⲟⲩ ϧⲉⲛ ⲟⲩⲣⲁϣⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲛⲁⲓ ⲙⲙⲟⲛⲧⲟⲩ ⲛⲟⲩⲛⲓ ⳿ⲙⲙⲁⲩ ⲛⲏⲉⲑⲛⲁϩϯ ⳿ⲡⲣⲟⲥ ⲟⲩⲥⲏⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ϧⲉⲛ ⳿ⲡⲥⲏⲟⲩ ⳿ⲛⲟⲩⲡⲓⲣⲁⲥⲙⲟⲥ ϣⲁⲩⲭⲁⲧⲟⲧⲟⲩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ.
14 Àwọn tí ó bọ́ sínú ẹ̀gún ni àwọn, tí wọ́n gbọ́ tán, wọ́n ti n lọ, wọn a sì fi ìtọ́jú àti ọrọ̀ àti ìrora ayé fún un pa, wọn kò sì lè so èso àsogbó.
ⲓ̅ⲇ̅ⲫⲏ ⲇⲉ ⲉⲧⲁϥϩⲉⲓ ⲉⲛ ⲛⲓⲥⲟⲩⲣⲓ ⲛⲁⲓ ⲛⲉ ⲛⲏⲉⲧⲥⲱⲧⲉⲙ ⲟⲩⲟϩ ⲛⲓⲣⲱⲟⲩϣ ⲛⲉⲙ ⲛⲓⲙⲉⲧⲣⲁⲙⲁ⳿ⲟ ⲛⲉⲙ ⲛⲓϩⲩⲇⲟⲛⲏ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲁⲓϫⲓⲛⲱⲛϧ ⲉⲩⲙⲟϣⲓ ⳿ⲛϧⲏⲧⲟⲩ ϣⲁⲩⲟϫϩⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲙⲡⲁⲩ⳿ⲉⲛ ⲟⲩⲧⲁϩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ.
15 Ṣùgbọ́n ti ilẹ̀ rere ni àwọn tí wọ́n fi ọkàn òtítọ́ àti rere gbọ́ ọ̀rọ̀ náà, wọ́n dìímú ṣinṣin, wọ́n sì fi sùúrù so èso.
ⲓ̅ⲉ̅ⲫⲏ ⲇⲉ ⲉⲧⲁϥϩⲉⲓ ϧⲉⲛ ⲡⲓⲕⲁϩⲓ ⲉⲑⲛⲁⲛⲉϥ ⲛⲁⲓ ⲛⲉ ⲛⲏⲉⲧⲥⲱⲧⲉⲙ ⳿ⲉⲡⲓⲥⲁϫⲓ ϧⲉⲛ ⲟⲩϩⲏⲧ ⳿ⲉⲛⲁⲛⲉϥ ⲟⲩⲟϩ ⲛ⳿ⲁⲅⲁⲑⲟⲛ ⲉⲩ⳿ⲁⲙⲟⲛⲓ ⳿ⲙⲙⲟϥ ⲟⲩⲟϩ ϣⲁⲩ⳿ⲉⲛ ⲟⲩⲧⲁϩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲟⲩϩⲩⲡⲟⲙⲟⲛⲏ.
16 “Kò sí ẹnikẹ́ni, nígbà tí ó bá tán fìtílà tan, tí yóò fi ohun èlò bò ó mọ́lẹ̀, tàbí tí yóò gbé e sábẹ́ àkéte; bí kò ṣe kí ó gbé e ka orí ọ̀pá fìtílà, kí àwọn tí ń wọ ilé lè rí ìmọ́lẹ̀.
ⲓ̅ⲋ̅⳿ⲙⲡⲁⲣⲉ ⳿ϩⲗⲓ ϭⲉⲣⲉ ⲟⲩϧⲏⲃⲥ ⳿ⲛⲧⲉϥϩⲟⲃⲥϥ ϧⲉⲛ ⲩ⳿ⲥⲕⲉⲩⲟⲥ ⲓⲉ ⳿ⲛⲧⲉϥⲭⲁϥ ⲥⲁ⳿ⲉ⳿ϧⲣⲏ ⲓ ⳿ⲛⲟⲩϭⲗⲟϫ ⲁⲗⲗⲁ ⳿ⲉϣⲁⲩⲭⲁϥ ϩⲓϫⲉⲛ ⲟⲩⲗⲩⲭⲛⲓ⳿ⲁ ϩⲓⲛⲁ ⲛⲏⲉⲑⲛⲁ⳿ⲓ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲛⲧⲟⲩⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲡⲓⲟⲩⲱⲓⲛⲓ.
17 Nítorí kò sí ohun tí ó fi ara sin, tí a kì yóò fihàn, tàbí ohun tí a fi pamọ́, ti a kì yóò sì mọ̀ kí ó sì yọ sí gbangba.
ⲓ̅ⲍ̅ⲙⲙⲟⲛ ⲡⲉⲧϩⲏⲡ ⲅⲁⲣ ϫⲉ ⳿ϥⲛⲁⲟⲩⲱⲛϩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲁⲛ ⲟⲩⲇⲉ ⳿ⲙⲙⲟⲛ ⲡⲉⲧⲭⲏⲡ ϫⲉ ⲥⲉⲛⲁ⳿ⲉⲙⲓ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⲁⲛ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲧⲉϥ⳿ⲓ ⳿ⲉ⳿ⲑⲙⲏϯ.
18 Ǹjẹ́ kí ẹ̀yin máa kíyèsára bí ẹ̀yin ti ń gbọ́: nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá ní, lọ́wọ́ rẹ̀ ni a ó sì gba èyí tí ó ṣe bí òun ní.”
ⲓ̅ⲏ̅⳿ⲁⲛⲁⲩ ⲟⲩⲛ ϫⲉ ⲧⲁⲣⲉⲧⲉⲛⲥⲱⲧⲉⲙ ⳿ⲛⲁϣ ⳿ⲛⲣⲏϯ ⲫⲏ ⲅⲁⲣ ⲉⲧⲉ ⲟⲩⲟⲛ ⳿ⲛⲧⲁϥ ⲉⲩ⳿ⲉϯ ⲛⲁϥ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉⲧⲉ⳿ⲙⲙⲟⲛ ⳿ⲛⲧⲁϥ ⲡⲓⲕⲉⲟⲩⲁⲓ ⳿ⲉⲧⲉϥⲙⲉⲩⲓ ⳿ⲉⲣⲟϥ ϫⲉ ⳿ϥⲉⲛⲧⲟⲧϥ ⲩ⳿ⲉⲟⲗϥ ⳿ⲛⲧⲟⲧϥ.
19 Nígbà náà ní ìyá rẹ̀ àti àwọn arákùnrin rẹ̀ tọ̀ ọ́ wá, wọn kò sì lè súnmọ́ ọn nítorí ọ̀pọ̀ ènìyàn.
ⲓ̅ⲑ̅ⲁⲥ⳿ⲓ ⲇⲉ ϩⲁⲣⲟϥ ⳿ⲛϫⲉ ⲧⲉϥⲙⲁⲩ ⲛⲉⲙ ⲛⲉϥ⳿ⲥⲛⲏⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲛⲁⲩ⳿ϣϫⲉⲙϫⲟⲙ ⲁⲛ ⲡⲉ ⳿ⲉϯⲙⲁϯ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⲉⲑⲃⲉ ⲡⲓⲙⲏϣ.
20 Wọ́n sì wí fún un pé, “Ìyá rẹ àti àwọn arákùnrin rẹ dúró lóde, wọn fẹ́ rí ọ.”
ⲕ̅ⲁⲩⲧⲁⲙⲟϥ ⲇⲉ ϫⲉ ⲓⲥ ⲧⲉⲕⲙⲁⲩ ⲛⲉⲙ ⲛⲉⲕ⳿ⲥⲛⲏⲟⲩ ⲥⲉ⳿ⲟϩⲓ ⳿ⲉⲣⲁⲧⲟⲩ ⲥⲁⲃⲟⲗ ⲉⲩⲟⲩⲱϣ ⳿ⲉⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲣⲟⲕ.
21 Ó sì dáhùn wí fún wọn pé, “Ìyá mi àti àwọn arákùnrin mi ni àwọn wọ̀nyí tí wọ́n ń gbọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, tí wọ́n sì ń ṣe é.”
ⲕ̅ⲁ̅⳿ⲛⲑⲟϥ ⲇⲉ ⲁϥⲉⲣⲟⲩⲱ ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲱⲟⲩ ϫⲉ ⲧⲁⲙⲁⲩ ⲛⲉⲙ ⲛⲁ⳿ⲥⲛⲏⲟⲩ ⲛⲁⲓ ⲛⲉ ⲛⲏⲉⲧⲥⲱⲧⲉⲙ ⳿ⲉⲡⲓⲥⲁϫⲓ ⳿ⲛⲧⲉ ⲫϯ ⲟⲩⲟϩ ⲉⲧ⳿ⲓⲣⲓ ⳿ⲙⲙⲟϥ.
22 Ní ọjọ́ kan, ó sì wọ ọkọ̀ ojú omi kan lọ òun pẹ̀lú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀. O sì wí fún wọn pé, “Ẹ jẹ́ kí a rékọjá lọ sí ìhà kejì adágún.” Wọ́n sì ṣíkọ̀ láti lọ.
ⲕ̅ⲃ̅ⲁⲥϣⲱⲡⲓ ⲇⲉ ϧⲉⲛ ⲟⲩⲁⲓ ⳿ⲛⲛⲓ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⳿ⲛⲑⲟϥ ϥ⳿ⲁⲗⲏⲓ ⳿ⲉⲟⲩϫⲟⲓ ⲛⲉⲙ ⲛⲉϥⲙⲁⲑⲏⲧⲏⲥ ⲟⲩⲟϩ ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲱⲟⲩ ϫⲉ ⲙⲁⲣⲉⲛϣⲉ ⲛⲁⲛ ⳿ⲉⲙⲏⲣ ⳿ⲉϯⲗⲩⲙⲛⲏ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩⲥⲱⲕ ⳿ⲉⲃⲟⲗ.
23 Bí wọ́n sì ti ń lọ, ó sùn; ìjì ńlá sì dé, ó ń fẹ́ lójú adágún; omi si wọ inú ọkọ, wọ́n sì wà nínú ewu.
ⲕ̅ⲅ̅ⲉⲩⲉⲣϩⲱⲧ ⲇⲉ ϥⲉⲛⲕⲟⲧ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥ⳿ⲓ ⳿ⲉ⳿ϧⲣⲏⲓ ⳿ⲉϯⲗⲩⲙⲛⲏ ⳿ⲛϫⲉ ⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲛⲑⲏⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲛⲁϥⲕⲱϯ ⳿ⲉⲣⲱⲟⲩ ⲡⲉ ⲟⲩⲟϩ ⲛⲁⲩⲉⲣⲕⲓⲛⲇⲩⲛⲉⲩⲓⲛ.
24 Wọ́n sì tọ̀ ọ́ wá wọ́n sì jí i, wí pé, “Olùkọ́, Olùkọ́, àwa yóò ṣègbé!” Nígbà náà ni ó dìde, ó sì bá ìjì líle àti ríru omi wí; wọ́n sì dúró, ìdákẹ́rọ́rọ́ sì dé.
ⲕ̅ⲇ̅ⲉⲧⲁⲩ⳿ⲓ ⲇⲉ ⲩⲛⲉϩⲥⲓ ⳿ⲙⲙⲟϥ ⲉⲩϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ⳿ⲫⲣⲉϥϯ⳿ⲥⲃⲱ ⲧⲉⲛⲛⲁⲧⲁⲕⲟ ⳿ⲛⲑⲟϥ ⲇⲉ ⲉⲧⲁϥⲧⲱⲛϥ ⲁϥⲉⲣⲉⲡⲓⲧⲓⲙⲁⲛ ⳿ⲙⲡⲓⲑⲏⲟⲩ ⲛⲉⲙ ⲛⲓϩⲱⲓⲙⲓ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲓⲙⲱⲟⲩ ⲩⲟϩ ⲁⲩϩⲉⲣⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲥϣⲱⲡⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲛϫⲁⲙⲏ.
25 Ó sì wí fún wọn pé, “Ìgbàgbọ́ yín dà?” Bí ẹ̀rù ti ń ba gbogbo wọn, tí hà sì ń ṣe wọ́n, wọ́n ń bi ara wọn pé, “Irú ọkùnrin wo ni èyí, nítorí ó bá ìjì líle àti ríru omi wí, wọ́n sì gbọ́ tirẹ̀?”
ⲕ̅ⲉ̅ⲟⲩⲟϩ ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲱⲟⲩ ϫⲉ ⲁϥⲑⲱⲛ ⲡⲉⲧⲉⲛⲛⲁϩϯ ⳿ⲛⲑⲱⲟⲩ ⲇⲉ ⲉⲧⲁⲩⲉⲣϩⲟϯ ⲩⲉⲣ⳿ϣⲫⲏ ⲣⲓ ⲉⲩϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⳿ⲛⲛⲟⲩⲉⲣⲏⲟⲩ ϫⲉ ⲛⲓⲙ ϩⲁⲣⲁ ⲡⲉ ⲫⲁⲓ ϫⲉ ⳿ϥⲟⲩⲁϩⲥⲁϩⲛⲓ ⳿ⲛⲛⲓⲕⲉⲑⲏⲟⲩ ⲛⲉⲙ ⲛⲓⲙⲱⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲥⲉⲥⲱⲧⲉⲙ ⲛⲁϥ.
26 Wọ́n sì gúnlẹ̀ ní ilẹ̀ àwọn ará Gadara, tí ó kọjú sí Galili.
ⲕ̅ⲋ̅ⲩⲟϩ ⲁⲩⲉⲣϩⲱⲧ ⳿ⲉ⳿ⲧⲭⲱⲣⲁ ⳿ⲛⲧⲉ ⲛⲓⲅⲉⲣⲅⲉⲥⲏ ⲛⲟⲥ ⲉⲧⲉ ⲑⲏ ⲧⲉ ⲉⲧϩⲓⲙⲏⲣ ⲟⲩⲃⲉ ϯⲅⲁⲗⲓⲗⲉ⳿ⲁ.
27 Nígbà tí ó sì sọ̀kalẹ̀, ọkùnrin kan pàdé rẹ̀ lẹ́yìn ìlú náà, tí ó ti ní àwọn ẹ̀mí èṣù fún ìgbà pípẹ́, tí kì í wọ aṣọ, bẹ́ẹ̀ ni kì í jókòó ní ilé kan, bí kò ṣe ní ibojì.
ⲕ̅ⲍ̅ⲉⲧⲁϥ⳿ⲓ ⲇⲉ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲉⲡⲓⲕⲁϩⲓ ⲁϥ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϩⲁⲣⲟϥ ⳿ⲛϫⲉ ⲟⲩⲣⲱⲙⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ϯⲃⲁⲕⲓ ⳿ⲉⲟⲩⲟⲛ ϩⲁⲛⲇⲉⲙⲱⲛ ⲛⲉⲙⲁϥ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉⲁϥⲉⲣⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲛ⳿ⲭⲣⲟⲛⲟⲥ ⳿ⲙⲡⲉϥϯ⳿ϩⲃⲟⲥ ϩⲓⲱⲧϥ ⲟⲩⲟϩ ⲙⲡⲉϥϣⲱⲡⲓ ϧⲉⲛ ⲏⲓ ⲁⲗⲗⲁ ϧⲉⲛ ⲛⲓ⳿ⲙϩⲁⲩ.
28 Nígbà tí ó rí Jesu, ó ké, ó wólẹ̀ níwájú rẹ̀, ó wí lóhùn rara, pé, “Kí ni mo ní í ṣe pẹ̀lú rẹ, Jesu, ìwọ Ọmọ Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo? Èmi bẹ̀ ọ́ má ṣe dá mi lóró.”
ⲕ̅ⲏ̅ⲉⲧⲁϥⲛⲁⲩ ⲇⲉ ⳿ⲉⲒⲏ̅ⲥ̅ ⲁϥⲱϣ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲁϥϩⲓⲧϥ ⳿ⲉ⳿ϧⲣⲏⲓ ϧⲁⲣⲁⲧϥ ⲟⲩⲟϩ ⲡⲉϫⲁϥ ϧⲉⲛ ⲟⲩⲛⲓϣϯ ⲛ⳿ⲥⲙⲏ ϫⲉ ⳿ⲁϧⲟⲕ ⲛⲉⲙⲏⲓ ⳿ⲡϣⲏⲣⲓ ⳿ⲙⲫϯ ⲉⲧⲟⲛϧ ϯϯϩⲟ ⳿ⲉⲣⲟⲕ ⳿ⲙⲡⲉⲣϯ⳿ⲙⲕⲁϩ ⲛⲏⲓ.
29 (Nítorí tí ó ti wí fún ẹ̀mí àìmọ́ náà pé, kí ó jáde kúrò lára ọkùnrin náà. Nígbàkígbà ni ó ń mú un: wọn a sì fi ẹ̀wọ̀n àti ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ dè é; a sì ja gbogbo ìdè náà, ẹ̀mí èṣù náà a sì darí rẹ̀ sí ijù).
ⲕ̅ⲑ̅⳿ⲛⲑⲟϥ ⲇⲉ ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲱⲟⲩ ϫⲉ ⲙⲏⲛ ϯϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⲛⲱⲧⲉⲛ ϫⲉ ⳿ⲙⲙⲟⲛ ⳿ϩⲗⲓ ⳿ⲉⲁϥⲭⲁ ⲏⲓ ⳿ⲛⲥⲱϥ ⲓⲉ ⲟⲩ⳿ⲥϩⲓⲙⲓ ⲓⲉ ϩⲁⲛ⳿ⲥⲛⲏⲟⲩ ⲓⲉ ϩⲁⲛⲓⲟϯ ⲓⲉ ϩⲁⲛϣⲏⲣⲓ ⲉⲑⲃⲉ ϯⲙⲉⲧⲟⲩⲣⲟ ⳿ⲛⲧⲉ ⲫϯ.
30 Jesu sì bi í pé, “Kí ni orúkọ rẹ?” Ó sì dáhùn pé, “Ligioni,” nítorí ẹ̀mí èṣù púpọ̀ ni ó wa nínú rẹ.
ⲗ̅ⲁϥϣⲉⲛϥ ⲇⲉ ⳿ⲛϫⲉ ⲏ̅ⲥ̅ ϫⲉ ⲛⲓⲙ ⲡⲉ ⲡⲉⲕⲣⲁⲛ ⳿ⲛⲑⲟϥ ⲇⲉ ⲡⲉϫⲁϥ ϫⲉ ⲗⲉⲅⲓⲱⲛ ϫⲉ ⲁⲩϣⲉ ⲛⲱⲟⲩ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⳿ⲛϫⲉ ⲟⲩⲙⲏϣ ⳿ⲛⲇⲉⲙⲱⲛ.
31 Wọ́n sì bẹ̀ ẹ́ pé, kí ó má ṣe rán wọn lọ sínú ọ̀gbun. (Abyssos g12)
ⲗ̅ⲁ̅ⲟⲩⲟϩ ⲛⲁⲩϯϩⲟ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⲉ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲧⲉϥ⳿ϣⲧⲉⲙⲟⲩⲁϩⲥⲁϩⲛⲓ ⲛⲱⲟⲩ ⳿ⲉϣⲉ ⳿ⲉ⳿ⲫⲛⲟⲩⲛ. (Abyssos g12)
32 Agbo ẹlẹ́dẹ̀ púpọ̀ sì ń bẹ níbẹ̀ tí ń jẹ lórí òkè: wọ́n sì bẹ̀ ẹ́ kí ó jẹ́ kí àwọn wọ inú wọn lọ. Ó sì gba fún wọn.
ⲗ̅ⲃ̅ⲛⲉ ⲟⲩⲟⲛ ⲟⲩ⳿ⲟϩⲓ ⲇⲉ ⳿ⲛⲣⲓⲣ ⳿ⲙⲙⲁⲩ ⲉⲩⲙⲟⲛⲓ ϧⲉⲛ ⲡⲓⲧⲱⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲛⲁⲩϯϩⲟ ⲉⲣⲟϥ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲧⲉϥⲭⲁⲩ ⳿ⲉϣⲉ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉⲛⲏ ⳿ⲉⲧⲉ⳿ⲙⲙⲁⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥⲭⲁⲩ.
33 Nígbà tí àwọn ẹ̀mí èṣù sì jáde kúrò lára ọkùnrin náà, wọ́n sì wọ inú àwọn ẹlẹ́dẹ̀ lọ. Agbo ẹlẹ́dẹ̀ sì tú ka, wọ́n sí súré rọ́ gììrì sọ̀kalẹ̀ sì bèbè odò bọ́ sínú adágún náà, wọ́n sì rì sínú rẹ̀.
ⲗ̅ⲅ̅ⲉⲧⲁⲩ⳿ⲓ ⲇⲉ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϩⲓ ⲡⲓⲣⲱⲙⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲓⲇⲉⲙⲱⲛ ⲁⲩϣⲉ ⲛⲱⲟⲩ ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉⲛⲓ⳿ⲉϣⲁⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲥ⳿ⲓ ⳿ⲛϫⲉ ϯⲁⲅⲉⲗⲏ ⳿ⲛⲣⲓⲣ ⳿ⲉ⳿ϧⲣⲏⲓ ⳿ⲉϯ ⲗⲩⲙⲛⲏ ϧⲉⲛ ⲡⲓϫⲁϫⲣⲓⲙ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩⲱϫϩ.
34 Nígbà tí àwọn tí n bọ́ wọn rí ohun tí ó ṣẹlẹ̀, wọ́n sá, wọ́n sì lọ, wọ́n sì ròyìn ní ìlú àti ní ilẹ̀ náà.
ⲗ̅ⲇ̅ⲉⲧⲁⲩⲛⲁⲩ ⲇⲉ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲏⲉⲑⲙⲟⲛⲓ ⲉⲫⲏⲉⲧⲁϥϣⲱⲡⲓ ⲁⲩⲫⲱⲧ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩⲧⲁⲙⲉ ⲛⲏⲉⲧϧⲉⲛ ϯⲃⲁⲕⲓ ⲛⲉⲙ ⲛⲏⲉⲧϧⲉⲛ ⳿ⲧⲕⲟⲓ.
35 Nígbà náà ni wọ́n jáde lọ wo ohun náà tí ó ṣẹlẹ̀, wọ́n sì tọ Jesu wá, wọ́n sì rí ọkùnrin náà, lára ẹni tí àwọn ẹ̀mí èṣù ti jáde lọ, ó jókòó lẹ́bàá ẹsẹ̀ Jesu, ó wọ aṣọ, iyè rẹ̀ sì bọ́ sí ipò: ẹ̀rù sì bà wọ́n.
ⲗ̅ⲉ̅ⲁⲩ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲉⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲫⲏⲉⲧⲁϥϣⲱⲡⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩ⳿ⲓ ⲁ Ⲓⲏ̅ⲥ̅ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩϫⲓⲙⲓ ⳿ⲙⲡⲓⲣⲱⲙⲓ ⲉϥϩⲉⲙⲥⲓ ⲫⲏⲉⲧⲁ ⲛⲓⲇⲉⲙⲱⲛ ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲛϧⲏⲧϥ ⲉϥⲟⲓ ⳿ⲛⲥⲁⲃⲉ ⲉⲣⲉ ⲛⲉϥ⳿ϩⲃⲱⲥ ⲧⲟⲓ ϩⲓⲱⲧϥ ⲉϥⲭⲏ ϧⲁⲧⲉⲛ ⲉⲛϭⲁⲗⲁⲩϫ ⳿ⲛⲒⲏ̅ⲥ̅ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩⲉⲣϩⲟϯ.
36 Àwọn tí ó rí i ròyìn fún wọn bí ó ti ṣe mú ẹni tí ó ní ẹ̀mí èṣù náà láradá.
ⲗ̅ⲋ̅ⲁⲩⲧⲁⲙⲱⲟⲩ ⲇⲉ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲏⲉⲧⲁⲩⲛⲁⲩ ϫⲉ ⲉⲧⲁϥⲛⲟϩⲉⲙ ⳿ⲛⲁϣ ⳿ⲛⲣⲏϯ ⳿ⲛϫⲉ ⲫⲏ ⳿ⲉⲛⲁⲣⲉ ⲛⲓⲇⲉⲙⲱⲛ ⲉⲙⲁϥ.
37 Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn láti ilẹ̀ Gadara yíká bẹ̀ ẹ́ pé, kí ó lọ kúrò lọ́dọ̀ wọn; nítorí ẹ̀rù bà wọ́n gidigidi. Ó sì bọ́ sínú ọkọ̀ ojú omi, ó si kúrò.
ⲗ̅ⲍ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩϯϩⲟ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⳿ⲛϫⲉ ⲡⲓⲙⲏϣ ⲧⲏⲣϥ ⳿ⲛⲧⲉ ϯⲡⲉⲣⲓⲭⲱⲣⲟⲥ ⳿ⲛⲧⲉ ⲛⲓⲅⲉⲣⲅⲉⲥⲏⲛⲟⲥ ϫⲉ ⳿ⲛⲧⲉϥϣⲉ ⲛⲁϥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϩⲁⲣⲱⲟⲩ ϫⲉ ⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲛϩⲟϯ ⲡⲉ ⳿ⲉⲛⲁⲩⲭⲏ ⳿ⲛϧⲏⲧⲥ ⳿ⲛⲑⲟϥ ⲇⲉ ⲁϥⲁⲗⲏⲓ ⳿ⲉ⳿ⲡϫⲟⲓ ⲁϥⲧⲁⲥⲑⲟ.
38 Ǹjẹ́ ọkùnrin náà tí ẹ̀mí èṣù jáde kúrò lára rẹ̀, bẹ̀ ẹ́ kí òun lè máa bá a gbé: ṣùgbọ́n Jesu rán an lọ, wí pé,
ⲗ̅ⲏ̅ⲛⲁϥϯϩⲟ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⳿ⲛϫⲉ ⲡⲓⲣⲱⲙⲓ ⲫⲏⲉⲧⲁⲩ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲛϧⲏⲧϥ ⲛϫⲉ ⲛⲓⲇⲉⲙⲱⲛ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲧⲉϥⲟϩⲓ ⲛⲉⲙⲁϥ ⲁϥⲟⲩⲟⲣⲡϥ ⲇⲉ ⲉϥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⲛⲁϥ.
39 “Padà lọ sí ilé rẹ, kí o sì sọ ohun tí Ọlọ́run ṣe fún ọ bí ó ti pọ̀ tó.” Ó sì lọ, o sì ń ròyìn ka gbogbo ìlú náà bí Jesu ti ṣe ohun ńlá fún òun tó.
ⲗ̅ⲑ̅ϫⲉ ⲙⲁⲧⲁⲥⲑⲟ ⳿ⲉⲡⲉⲕⲏⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲥⲁϫⲓ ⳿ⲛⲛⲏⲉⲧⲁϥⲁⲓⲧⲟⲩ ⲉⲙⲁⲕ ⳿ⲛϫⲉ ⲫϯ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥϣⲉ ⲛⲁϥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ϯⲃⲁⲕⲓ ⲧⲏⲣⲥ ⲉϥϩⲓⲱⲓϣ ⳿ⲛⲛⲏⲉⲧⲁϥⲁⲓⲧⲟⲩ ⲛⲁϥ ⳿ⲛϫⲉ ⲫϯ.
40 Ó sì ṣe, nígbà tí Jesu padà lọ, àwọn ènìyàn tẹ́wọ́gbà á; nítorí tí gbogbo wọn ti ń retí rẹ̀.
ⲙ̅ⲉⲧⲁϥⲧⲁⲥⲑⲟ ⲇⲉ ⳿ⲛϫⲉ Ⲓⲏ̅ⲥ̅ ϥϣⲟⲡϥ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⳿ⲛϫⲉ ⲡⲓⲙⲏϣ ⲛⲁⲩϫⲟⲩϣⲧ ⲅⲁⲣ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲁϫⲱϥ ⲧⲏⲣⲟⲩ ⲡⲉ.
41 Sì kíyèsi i, ọkùnrin kan tí a ń pè ní Jairu, ọ̀kan nínú àwọn olórí Sinagọgu wá; ó sì wólẹ̀ lẹ́bàá ẹsẹ̀ Jesu, ó bẹ̀ ẹ́ pé, kí ó wá sí ilé òun,
ⲙ̅ⲁ̅ⲟⲩⲟϩ ϩⲏⲡⲡⲉ ⲁϥ⳿ⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲟⲩⲣⲱⲙⲓ ⳿ⲉⲡⲉϥⲣⲁⲛ ⲡⲉ ⲓⲁⲓⲣⲟⲥ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲓ ⲛⲉ ⲟⲩⲁⲣⲭ ⲱⲛ ⲡⲉ ⳿ⲛⲧⲉ ϯⲥⲩⲛⲁⲅⲱⲅⲏ ⲟⲩⲟϩ ⲉⲧⲁϥϩⲓⲧϥ ⳿ⲉ⳿ϧⲣⲏⲓ ϧⲁⲧⲉⲛ ⲛⲉⲛϭⲁⲗⲁⲩϫ ⳿ⲛⲒⲏ̅ⲥ̅ ⲛⲁϥϯϩⲟ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⲉⲑⲣⲉϥ⳿ⲓ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉⲡⲉϥⲏⲓ.
42 nítorí ó ní ọmọbìnrin kan ṣoṣo, ọmọ ìwọ̀n ọdún méjìlá, ti ó ń kú lọ. Bí ó sì ti ń lọ àwọn ènìyàn ko fun ni ààyè.
ⲙ̅ⲃ̅ⲉ ⲟⲩϣⲉⲣⲓ ⳿ⲙⲙⲁⲩⲁⲧⲥ ⳿ⲉⲛⲁⲥ⳿ⲛⲧⲁϥ ⲡⲉ ⲉⲥϧⲉⲛ ⲓ̅ⲃ̅ ⳿ⲛⲣⲟⲙⲡⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲑⲁⲓ ⲛⲁⲥⲛⲁⲙⲟⲩ ⲡⲉ ⲉϥⲛⲁ⳿ⲓ ⲇⲉ ⳿ⲛϫⲉ Ⲓⲏ̅ⲥ̅ ⲛⲁⲩϩⲟϫϩⲉϫ ⳿ⲙⲙⲟϥ ⲡⲉ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲓⲙⲏϣ.
43 Obìnrin kan tí ó sì ní ìsun ẹ̀jẹ̀ láti ìgbà ọdún méjìlá, tí ó ná ohun gbogbo tí ó ní fún àwọn oníṣègùn, tí kò sì sí ẹnìkan tí ó lè mú un láradá,
ⲙ̅ⲅ̅ⲟⲩⲟϩ ⲟⲩ⳿ⲥϩⲓⲙⲓ ⲛⲉ ⲟⲩⲟⲛ ⲟⲩ⳿ⲥⲛⲟϥ ⲭⲏ ϧⲁⲣⲟⲥ ⳿ⲙⲓ̅ⲃ̅ ⳿ⲛⲣⲟⲙⲡⲓ ⲑⲁⲓ ⲉⲧⲁⲥϭⲟ ⳿ⲙⲡⲉⲥⲱⲛϧ ⲏⲣϥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲛⲛⲓⲥⲏⲓⲛⲓ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲙⲡⲉⲥ⳿ϣϫⲉⲙϫⲟⲙ ⲉⲑⲣⲟⲩⲉⲣⲫⲁϧⲣⲓ ⳿ⲉⲣⲟⲥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϩⲓⲧⲉⲛ ⳿ϩⲗⲓ.
44 Ó wá sí ẹ̀yìn rẹ̀, ó fi ọwọ́ tọ́ ìṣẹ́tí aṣọ rẹ̀; lọ́gán ni ìsun ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sì ti gbẹ.
ⲙ̅ⲇ̅ⲉⲧⲁⲥ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϩⲓⲫⲁϩⲟⲩ ⲁⲥϭⲓ ⲛⲉⲙ ⳿ⲡ⳿ϣⲧⲁϯ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲉϥ⳿ϩⲃⲟⲥ ⲟⲩⲟϩ ⲥⲁⲧⲟⲧϥ ⲁϥⲟϩⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲓ⳿ⲥⲛⲟϥ ⳿ⲉⲛⲁϥϣⲁⲧ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲁⲣⲟⲥ.
45 Jesu sì wí pé, “Ta ni ó fi ọwọ́ kàn mí?” Nígbà tí gbogbo wọn sẹ́ Peteru àti àwọn tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀ sọ pé, “Olùkọ́, àwọn ènìyàn ko ní ààyè, wọ́n sì ń kọlù ọ́, ìwọ sì wí pé, Ta ni ó fi ọwọ́ kàn mi?”
ⲙ̅ⲉ̅ⲟⲩⲟϩ ⲡⲉϫⲉ Ⲓⲏ̅ⲥ̅ ϫⲉ ⲛⲓⲙ ⲡⲉⲧⲁϥϭⲓ ⲛⲉⲙⲏⲓ ⲉⲩϫⲱⲗ ⲇⲉ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲧⲏⲣⲟⲩ ⲡⲉϫⲉ ⲡⲉⲧⲣⲟⲥ ⲛⲉⲙ ⲛⲏ ⲑⲛⲉⲙⲁϥ ϫⲉ ⲡⲓⲣⲉϥϯ⳿ⲥⲃⲱ ⲛⲓⲙⲏϣ ⲉⲧⲕⲱϯ ⳿ⲉⲣⲟⲕ ⲟⲩⲟϩ ⲉⲧϩⲟϫϩⲉϫ ⳿ⲙⲙⲟⲕ.
46 Jesu sì wí pé, “Ẹnìkan fi ọwọ́ kàn mí: nítorí tí èmí mọ̀ pé, àṣẹ jáde lára mi.”
ⲙ̅ⲋ̅Ⲓⲏ̅ⲥ̅ ⲇⲉ ⲡⲉϫⲁϥ ϫⲉ ⲟⲩⲟⲛ ⲡⲉⲧⲁϥϭⲓ ⲛⲉⲙⲏⲓ ⳿ⲁⲛⲟⲕ ⲅⲁⲣ ⲓ⳿ⲉⲙⲓ ⳿ⲉⲟⲩϫⲟⲙ ⲁⲥ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲙⲙⲟⲓ.
47 Nígbà tí obìnrin náà sì mọ̀ pé òun kò fi ara sin, ó wárìrì, ó wá, ó sì wólẹ̀ níwájú rẹ̀, ó sì sọ fún un lójú àwọn ènìyàn gbogbo nítorí ohun tí ó ṣe, tí òun fi fi ọwọ́ kàn án, àti bí a ti mú òun láradá lójúkan náà.
ⲙ̅ⲍ̅ⲉⲧⲁⲥⲛⲁⲩ ⲇⲉ ⳿ⲛϫⲉ ϯ⳿ⲥϩⲓⲙⲓ ϫⲉ ⳿ⲙⲡⲉϥⲉⲣ⳿ⲡⲱⲃϣ ⲁⲥ⳿ⲓ ⲉⲥ⳿ⲥⲑⲉⲣⲧⲉⲣ ⲟⲩⲟϩ ⲉⲧⲁⲥϩⲓⲧⲥ ⳿ⲉ⳿ϧⲣⲏⲓ ϧⲁⲣⲁⲧϥ ⲥⲟⲩⲱⲛϩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲙⲡⲉ⳿ⲙⲑⲟ ⳿ⲙⲡⲓⲗⲁⲟⲥ ⲧⲏⲣϥ ϫⲉ ⲉⲑⲃⲉⲟⲩ ⳿ⲛ⳿ⲉⲧⲓ⳿ⲁ ⲁⲥϭⲓ ⲛⲉⲙⲁϥ ⲛⲉⲙ ⲡⲓⲣⲏϯ ⲉⲧⲁⲥⲟⲩϫⲁⲓ ⳿ⲙⲙⲟϥ ⲥⲁⲧⲟⲧⲥ.
48 Ó sì wí fún un pé, “Ọmọbìnrin, ìgbàgbọ́ rẹ mú ọ láradá, máa lọ ní Àlàáfíà.”
ⲙ̅ⲏ̅⳿ⲛⲑⲟϥ ⲡⲉϫⲁϥ ⲁⲥ ϫⲉ ⲧⲁϣⲉⲣⲓ ⲡⲉⲛⲁϩϯ ⲡⲉⲧⲁϥⲛⲁϩⲙⲓ ⲙⲁϣⲉ ⲛⲉ ϧⲉⲛ ⲟⲩϩⲓⲣⲏⲛⲏ.
49 Bí ó sì ti ń sọ̀rọ̀ lẹ́nu, ẹnìkan ti ilé olórí Sinagọgu wá, ó wí fún un pé, “Ọmọbìnrin rẹ kú; má yọ olùkọ́ni lẹ́nu mọ́.”
ⲙ̅ⲑ̅ⲉⲧⲓ ⲉϥⲥⲁϫⲓ ⲁϥ⳿ⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲟⲩⲁⲓ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲓⲁⲣⲭⲏⲥⲩⲛⲁⲅⲱⲅⲟⲥ ⲉϥϫⲱ ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ⲁⲥⲙⲟⲩ ⳿ⲛϫⲉ ⲧⲉⲕϣⲉⲣⲓ ⳿ⲙⲡⲉⲣϯ ϧⲓⲥⲓ ⳿ⲙⲡⲓⲣⲉϥϯ⳿ⲥⲃⲱ.
50 Ṣùgbọ́n nígbà tí Jesu gbọ́, ó dá a lóhùn, pé, “Má bẹ̀rù: sá gbàgbọ́ nìkan, a ó sì mú un láradá.”
ⲛ̅Ⲓⲏ̅ⲥ̅ ⲇⲉ ⲉⲧⲁϥⲥⲱⲧⲉⲙ ⲁϥⲉⲣⲟⲩⲱ ⲡⲉϫⲁϥ ϫⲉ ⳿ⲙⲡⲉⲣⲉⲣϩⲟϯ ⲙⲟⲛⲟⲛ ⲁϩϯ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲥⲛⲁⲛⲟϩⲉⲙ.
51 Ṣùgbọ́n nígbà tí Jesu sì wọ ilé, kò jẹ́ kí ẹnikẹ́ni wọlé, bí kò ṣe Peteru, àti Jakọbu, àti Johanu, àti baba àti ìyá ọmọbìnrin náà.
ⲛ̅ⲁ̅ⲉⲧⲁϥ⳿ⲓ ⲇⲉ ⳿ⲉⲡⲓⲏⲓ ⳿ⲙⲡⲉϥⲭⲁ ⳿ϩⲗⲓ ⳿ⲉ⳿ⲓ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⲛⲉⲙⲁϥ ⳿ⲉⲃⲏⲗ ⳿ⲉⲡⲉⲧⲣⲟⲥ ⲛⲉⲙ ⲓⲁⲕⲱⲃⲟⲥ ⲛⲉⲙ ⲓⲱⲁⲛⲛⲏⲥ ⲛⲉⲙ ⲫⲓⲱⲧ ⳿ⲛϯ⳿ⲁⲗⲟⲩ ⲛⲉⲙ ⲧⲉⲥⲙⲁⲩ.
52 Gbogbo wọn sì sọkún, wọ́n pohùnréré ẹkún rẹ̀: ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ má sọkún mọ́; kò kú, sísùn ni ó sùn.”
ⲛ̅ⲃ̅ⲛⲁⲩⲣⲓⲙⲓ ⲇⲉ ⲧⲏⲣⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲛⲁⲩⲛⲉϩⲡⲓ ⳿ⲉⲣⲟⲥ ⲡⲉ ⳿ⲛⲑⲟϥ ⲇⲉ ⲡⲉϫⲁϥ ϫⲉ ⳿ⲙⲡⲉⲣⲣⲓⲙⲓ ⳿ⲙⲡⲉⲥⲙⲟⲩ ⲅⲁⲣ ⲛϫⲉ ϯ⳿ⲁⲗⲟⲩ ⲁⲗⲗⲁ ⲁⲥ⳿ⲛⲕⲟⲧ.
53 Wọ́n sì fi í ṣẹ̀fẹ̀, wọ́n sá mọ̀ pé ó kú.
ⲛ̅ⲅ̅ⲟⲩⲟϩ ⲛⲁⲩⲥⲱⲃⲓ ⳿ⲙⲙⲟϥ ⲡⲉ ⲉⲩ⳿ⲉⲙⲓ ϫⲉ ⲁⲥⲙⲟⲩ.
54 Nígbà tí ó sì sé gbogbo wọn mọ́ òde, ó mú un lọ́wọ́, ó sì wí pé, “Ọmọbìnrin, dìde!”
ⲛ̅ⲇ̅⳿ⲛⲑⲟϥ ⲇⲉ ⲉⲧⲁϥϩⲓⲧⲟⲩ ⲧⲏⲣⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲉⲧⲁϥ⳿ⲁⲙⲟⲛⲓ ⳿ⲛⲧⲉⲥϫⲓϫ ⲁϥⲙⲟⲩϯ ⲉϥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ϯ⳿ⲁⲗⲟⲩ ⲧⲱⲟⲩⲛⲓ.
55 Ẹ̀mí rẹ̀ sì padà bọ̀, ó sì dìde lọ́gán: ó ní kí wọn fún un ní oúnjẹ.
ⲛ̅ⲉ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁϥⲕⲟⲧϥ ⳿ⲉⲣⲟⲥ ⳿ⲛϫⲉ ⲡⲉⲥⲡ͞ⲛⲁ̅ ⲟⲩⲟϩ ⲥⲁⲧⲟⲧⲥ ⲁⲥⲧⲱⲛⲥ ⲩⲟϩ ⲁϥⲟⲩⲁϩⲥⲁϩⲛⲓ ⳿ⲛⲧⲟⲩϯ ⲛⲁⲥ ⳿ⲉⲟⲩⲱⲙ.
56 Ẹnu sì ya àwọn òbí rẹ̀: ṣùgbọ́n ó kìlọ̀ fún wọn pé, kí wọn má ṣe wí fún ẹnìkan ohun tí a ṣe.
ⲛ̅ⲋ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩⲧⲱⲙⲧ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲉⲥⲓⲟϯ ⳿ⲛⲑⲟϥ ⲇⲉ ⲁϥϩⲟⲛϩⲉⲛ ⲛⲱⲟⲩ ⳿ⲉ⳿ϣⲧⲉⲙϫⲉ ⲫⲏⲉⲧⲁϥϣⲱⲡⲓ ⳿ⲛ⳿ϩⲗⲓ

< Luke 8 >