< Luke 7 >

1 Nígbà tí ó sì parí gbogbo ọ̀rọ̀ rẹ̀ fun àwọn ènìyàn, ó wọ Kapernaumu lọ.
Dunu huluane da amo sia: nabi dagoi. Sia: dagoloba, Yesu da asili, Gabena: iame moilaiga doaga: i.
2 Ọmọ ọ̀dọ̀ balógun ọ̀rún kan, tí ó ṣọ̀wọ́n fún un, ṣàìsàn, ó sì ń kú lọ.
Amo moilai ganodini da Louma dadi gagui ouligisu dunu esalu. Ea hawa: hamosu dunu afae, ema e da bagadewane asigisu, amo da oloi bagadeba: le, bogomuwane dialu.
3 Nígbà tí ó sì gbúròó Jesu, ó rán àwọn àgbàgbà Júù sí i, ó ń bẹ̀ ẹ́ pé kí ó wá mú ọmọ ọ̀dọ̀ òun láradá.
Dadi gagui ouligisu dunu da Yesu misi nababeba: le, Yu asigilai dunu Yesuma asunasi. Yesu da ea dogolegei hawa: hamosu dunu uhinisima: ne misa: ne sia: musa: , e da ili asunasi.
4 Nígbà tí wọ́n sì dé ọ̀dọ̀ Jesu, wọ́n fi ìtara bẹ̀ ẹ́, pé, “Ó yẹ ní ẹni tí òun ìbá ṣe èyí fún.
Yu asigilai dunu da Yesuma doaga: le, ilia da ha: giwane amane adole ba: i, “Dia da dadi gagui ouligisu dunu fidimu da defea!
5 Nítorí tí ó fẹ́ràn orílẹ̀-èdè wa, ó sì ti kọ́ Sinagọgu kan fún wa.”
E da ninia soge fi ilima bagade asigisa. E da ninia sinagoge diasu gagui dagoi.”
6 Jesu sì ń bá wọn lọ. Nígbà tí kò sì jìn sí etí ilé mọ́, balógun ọ̀rún náà rán àwọn ọ̀rẹ́ sí i, pé, “Olúwa, má ṣe yọ ara rẹ lẹ́nu, nítorí tí èmi kò yẹ tí ìwọ ìbá fi wọ abẹ́ òrùlé mi.
Amalalu, ilia da Yesu sigi ahoanoba, E da dadi gagui ouligisu dunu ea diasu gadenenewane doaga: loba, dadi gagui ouligisu dunu da ea na: iyado dunu Yesuma asunasi. Ilia da dadi gagui ouligisu dunu ea sia: , Yesuma amane olelei, “Hina! Mae dawa: ma! Dia na diasu ganodini golili sa: imu da defea hame galebe. Bai na hou da defele hame gala.
7 Nítorí náà èmi kò sì rò pé èmi náà yẹ láti tọ̀ ọ́ wá, ṣùgbọ́n sọ ní gbólóhùn kan, a ó sì mú ọmọ ọ̀dọ̀ mi láradá.
Amaiba: le na da Dima hame misi. Be Dia sia: beba: le fawane, na hawa: hamosu dunu da uhimu.
8 Nítorí èmi náà pẹ̀lú jẹ́ ẹni tí a fi sí abẹ́ àṣẹ, tí ó ní ọmọ-ogun lẹ́yìn mi, mo sì wí fún ọ̀kan pé, ‘Lọ,’ a sì lọ; àti fún òmíràn pé, ‘Wá,’ a sì wá; àti fún ọmọ ọ̀dọ̀ mi pé, ‘Ṣe èyí,’ a sì ṣe é.”
Na dawa: Na hina dunu da esala, amola na da eno dadi gagui dunuma hina esala. Dunu afadafa ema na da ‘Masa!’ sia: beba: le, e da ahoa. Enoma na da ‘Misa!’ sia: beba: le, e da maha. Na hawa: hamosu dunuma na da, ‘Agoane hamoma!’ sia: sea, e da agoane hamosa.”
9 Nígbà tí Jesu gbọ́ nǹkan wọ̀nyí, ẹnu sì yà, ó sì yípadà sí ìjọ ènìyàn tí ń tọ̀ ọ́ lẹ́yìn, ó wí pé, “Mo wí fún yín pé èmi kò rí irú ìgbàgbọ́ ńlá bí èyí nínú àwọn ènìyàn Israẹli.”
Amo sia: nababeba: le, Yesu da fofogadigili, sinidigili, dunu bagohame ea baligia aligi ilima amane sia: i, “Na dafawane sia: sa! Na da Isala: ili fi ganodini agoaiwane bagade dafawaneyale dawa: su hou hamedafa ba: i.”
10 Nígbà tí àwọn oníṣẹ́ sì padà sí ilé, wọ́n bá ọmọ ọ̀dọ̀ náà tí ń ṣàìsàn, ara rẹ̀ ti dá.
Amalalu, dadi gagui ea asunasi dunu da sinidigili, ea diasuga bu doaga: le, ea hawa: hamosu dunu uhi dagoi ba: i.
11 Ní ọjọ́ kejì, ó lọ sí ìlú kan tí a ń pè ní Naini, àwọn púpọ̀ nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì ń bá a lọ àti ọ̀pọ̀ ìjọ ènìyàn.
Amalalu, Yesu da Na: ine moilaiga asi. Ea ado ba: su dunu amola eno dunu bagohame ea baligia aligili asi.
12 Bí ó sì ti súnmọ́ ẹnu ibodè ìlú náà, sì kíyèsi i, wọ́n ń gbé òkú ọkùnrin kan jáde, ọmọ kan ṣoṣo náà tí ìyá rẹ̀ bí, ó sì jẹ́ opó: ọ̀pọ̀ ìjọ ènìyàn ìlú náà sì wà pẹ̀lú rẹ̀.
E da moilai logo holei amoga doaga: loba, dunu da bogoi dunu doufa amoga ligisili, dunuga gadili gaguli manebe ba: i. Bogoi da uda didalo ea mano afadafa fawane esalu bogoi. Asigiba: le, dunu bagohame amo didalo e sigi manebe ba: i.
13 Nígbà tí Olúwa sì rí i, àánú rẹ̀ ṣe é, ó sì wí fún un pé, “Má sọkún mọ́.”
Amo didalo ba: loba, Yesu da bagadewane asigiba: le, ema amane sia: i, “Mae dima!”
14 Ó sì wá, ó sì fi ọwọ́ tọ́ pósí náà: àwọn tí ń rù ú dúró jẹ́. Ó sì wí pé, “Ọ̀dọ́mọkùnrin, mo wí fún ọ, dìde!”
Amalalu, bogoi ea doufa amoga doaga: loba, amo doufa E da digili ba: beba: le, gagui dunu da ouligi. Yesu E amane sia: i, “Goi ayeligi! Na dima sia: sa! wa: legadoma!”
15 Ẹni tí ó kú náà sì dìde jókòó, ó bẹ̀rẹ̀ sí i fọhùn. Ó sì fà á lé ìyá rẹ̀ lọ́wọ́.
Amalalu, bogoi da bu uhini, wa: legadole sia: baoulalu. Yesu da amo dunu ea amema bu i.
16 Ẹ̀rù sì ba gbogbo wọn: wọ́n sì yin Ọlọ́run lógo, pé, “Wòlíì ńlá dìde nínú wa,” àti pé, “Ọlọ́run sì wá bẹ àwọn ènìyàn rẹ̀ wò!”
Dunu huluane da bagade beda: ne, Godema nodone sia: i, “Balofede dunu bagadedafa da ninima doaga: i dagoi.” Eno ilia sia: i, “Gode da Ea fidafa gaga: musa: misi dagoi.”
17 Òkìkí rẹ̀ sì kàn ní gbogbo Judea, àti gbogbo agbègbè tí ó yí i ká.
Amalalu, Yudia soge ganodini amola eno gadenene soge huluane ganodini, dunu huluane da Yesu Ea hou nababeba: le gilisili sia: dasu.
18 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Johanu sì sọ gbogbo nǹkan wọ̀nyí fún un.
Yone Ba: bodaise ea ado ba: su dunu da amo hou huluane Yonema olelei.
19 Nígbà tí Johanu sì pe àwọn méjì nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó rán wọn sọ́dọ̀ Olúwa, wí pé, “Ìwọ ni ẹni tí ń bọ̀, tàbí kí a máa retí ẹlòmíràn?”
Amalalu, Yone da ado ba: su dunu aduna Yesuma sia: ma: ne asunasi. E amane sia: i, “Yesuma amane adole ba: ma, ‘Yone da Mesaia misunu sia: i dagoi. Di da amo dunula: ? O ninia eno dunu misa: ne ouesaloma: bela: ?’”
20 Nígbà tí àwọn ọkùnrin náà sì dé ọ̀dọ̀ rẹ̀, wọ́n wí pé, “Johanu onítẹ̀bọmi rán wa sọ́dọ̀ rẹ, pé, ‘Ìwọ ni ẹni tí ń bọ̀, tàbí kí a máa retí ẹlòmíràn?’”
Amo dunu, Yesuma doaga: le, amane sia: i, “Yone Ba: bodaise da ani dima amane sia: ma: ne asunasi, amo ‘Di da Yone musa: misunu sia: i Dunu amola: ? O ninia eno misa: ne ouesaloma: bela: ?’”
21 Ní wákàtí náà, ó sì ṣe ìmúláradá ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn nínú àìsàn, àti ààrùn, àti ẹ̀mí búburú; ó sì fi ìríran fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn afọ́jú.
Ela mabe galu, Yesu da oloi bagade madelai dunu amola dunu ilia dogo ganodini Fio liligi aligila sa: i, amo bagohame uhininanebe ba: i. E da si dofoi dunu bagohame ilia si fadegalalu.
22 Jesu sì dáhùn ó wí fún wọn pé, “Ẹ padà lọ, ẹ ròyìn nǹkan tí ẹ̀yin rí, tí ẹ̀yin sì gbọ́ fún Johanu: àwọn afọ́jú ń ríran, àwọn amúnkùn ún rìn, a sọ àwọn adẹ́tẹ̀ di mímọ́, àwọn adití ń gbọ́rọ̀, a ń jí àwọn òkú dìde, àti fún àwọn òtòṣì ni à ń wàásù ìyìnrere.
Yesu da Yone ea adola ahoasu dunu elama amane adole i, “Yonema buhagili, alia waha ba: i liligi amola nabi liligi amo Yonema olelema. Si dofoi dunu da waha noga: i ba: sa. Emo gasuga: igi dunu da hahawane lala. Aiya madelai dunu da bahoi dagoi. Ge ga: i da waha naba. Bogoi da wa: legadoi dagoi. Hame gagui dunu da waha Gode Ea Sia: ida: iwane naba.
23 Alábùkún fún sì ni ẹnikẹ́ni tí kò kọsẹ̀ lára mi.”
Amola nowa dunu da Nama dafawaneyale dawa: su hame fisisia, e da hahawane gala!”
24 Nígbà tí àwọn oníṣẹ́ Johanu padà lọ, ó bẹ̀rẹ̀ sí í sọ fún ìjọ ènìyàn ní ti Johanu pé, “Kí ni ẹ̀yin jáde lọ sí ijù lọ wò? Ewéko tí afẹ́fẹ́ ń mì?
Yone ea adola ahoasu dunu ela da bu fisili asili dagoloba, dunu bagohame gilisili esalu ilima Yesu da Yone Ba: bodaise ea hou amane olelei, “Dilia da hafoga: i sogega Yonema ahoanoba, adi ba: la asibela: ? Dilia da gisi foga ugugui, amo ba: la asibela: ?
25 Ṣùgbọ́n kín ni ẹ̀yin jáde lọ wò? Ọkùnrin tí a wọ̀ ní aṣọ fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́? Wò ó, àwọn tí á wọ̀ ní aṣọ ògo, tí wọ́n sì ń jayé, ń bẹ ní ààfin ọba!
Adi ba: la gadili asibela; ? Be dilia dunu abula ida: iwane amoga idiniginisi ba: la asibela: ? Abula ida: iwane idiniginisi bagade gagui dunu ilia da osobo bagade hina bagade amo ilia diasu ganodini esalebe ba: sa!
26 Ṣùgbọ́n kí ni ẹ̀yin jáde lọ wò? Wòlíì? Lóòótọ́ ni mo wí fún yín, ó sì ju wòlíì lọ!
Nama adoma! Dilia adi ba: la asibela: ? Balofede dunula: ? Dafawane! Dilia balofede ea hou baligisu dunu ba: i dagoi.
27 Èyí yìí ni ẹni tí a ti kọ̀wé nítorí rẹ̀ pé: “‘Wò ó, èmi yóò rán oníṣẹ́ mi síwájú rẹ; ẹni tí yóò tún ọ̀nà rẹ ṣe níwájú rẹ.’
Bai Yone ea hou olelema: ne, Gode Sia: da agoane dedei diala, ‘Gode da amane sia: i, Na alofesu dunu amo Dia logo fodomusa: , Na da asunasimu.’
28 Mo wí fún yín nínú àwọn tí a bí nínú obìnrin, kò sí wòlíì tí ó pọ̀ ju Johanu Onítẹ̀bọmi lọ, ṣùgbọ́n ẹni tí ó kéré jùlọ ní ìjọba Ọlọ́run, ó pọ̀jù ú lọ.”
Na dilima dafawane sia: sa. Yone Ba: bodaise ea hou da udama lalelegei mano ilia hou huluane baligi dagoi. Be Gode Ea Hinadafa Hou Fi ganodini, baligili fonobahadidafa dunu da Yone ea hou baligisa!”
29 (Gbogbo àwọn ènìyàn tí ó gbọ́ àti àwọn agbowó òde, wọ́n dá Ọlọ́run láre, nítorí tí a fi ìtẹ̀bọmi Johanu tẹ̀ wọn bọ mi.
Dunu bagohame amola su lidisu dunu, ilia da Gode Ea moloidafa hamoma: ne sia: i nababeba: le, Yone ea hanoga fane salasu hou musa: lai dagoiba: le, ilia da Yesu Ea sia: hahawane nabi.
30 Ṣùgbọ́n àwọn Farisi àti àwọn amòfin kọ ète Ọlọ́run fún ara wọn, a kò bamitiisi wọn lọ́dọ̀ rẹ̀.)
Be Fa: lisi dunu amola sema olelesu dunu ilia da Gode Ea hou hame lalegagui amola Yone Ba: bodaise ea hanoga fane salasu hou higabeba: le, hanoga fane salasu hame hamoi.
31 Jesu sì wí pé, “Kí ni èmi ìbá fi àwọn ènìyàn ìran yìí wé? Kí ni wọ́n sì jọ?
Amalalu, Yesu E amane sia: i, “Na da wali esalebe dunu ilia hou olelemusa: , adi fedege sia: olelema: bela: ? Ilia da adi agoanela: ?
32 Wọ́n dàbí àwọn ọmọ kékeré tí ó jókòó ní ibi ọjà, tí wọ́n sì ń kọ sí ara wọn, tí wọ́n sì ń wí pé, “‘Àwa fọn fèrè fún yín, ẹ̀yin kò jó, àwa sì ṣọ̀fọ̀ fún yín, ẹ̀yin kò sọkún!’
Ilia da mano fonobahadi bidiga lama: ne diasu ganodini esalebe, mano enoma da mano enoma wele sia: nanebe agoane ba: sa, agoane, ‘Ninia da uda lasu gilisisu amoga baidama dubiba: le, dilia da hame gosa: i. Ninia didigia: beba: le, dilia da hame di.’
33 Nítorí Johanu Onítẹ̀bọmi wá, kò jẹ àkàrà, bẹ́ẹ̀ ni kò sì mu ọtí wáìnì, ẹ̀yin sì wí pé, ‘Ó ní ẹ̀mí èṣù?’
Be Yone Ba: bodaise da ha: i mae nawane, waini mae nawane doaga: i dagoiba: le, ea dogoga Fio liligi da aligila sa: i, dilia sia: sa.
34 Ọmọ ènìyàn dé, ó ń jẹ, ó sì ń mu, ẹ̀yin sì wí pé, ‘Wò ó, ọ̀jẹun, àti ọ̀mùtí, ọ̀rẹ́ àwọn agbowó òde àti àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀!’
Be Dunu Egefe da ha: i amola waini nana misiba: le, ‘Amo dunu ba: ma! Uasu amola feloasu dunu da goea! Su lidisu amola wadela: i hou hamosu dunu ilia na: iyado da goea!’ dilia da agoane sia: sa.
35 Ṣùgbọ́n ọgbọ́n ni a dá láre nípasẹ̀ ọmọ rẹ.”
Be Gode Ea dawa: sudafa hou da moloidafa. Nowa dunu da amo dawa: sudafa lalegagusia, ilia da Gode Ea hou da moloidafa amo olelesa.”
36 Farisi kan sì rọ̀ ọ́ kí ó wá bá òun jẹun, ó sì wọ ilé Farisi náà lọ ó sì jókòó láti jẹun.
Fa: lisi dunu afae e da ea diasuga ha: i manusa: Yesu misa: ne sia: si. Amalalu, Yesu da ea diasuga doaga: le, ha: i manusa: fi dialu.
37 Sì kíyèsi i, obìnrin kan wà ní ìlú náà, ẹni tí i ṣe ẹlẹ́ṣẹ̀, nígbà tí ó mọ̀ pé Jesu jókòó, ó ń jẹun ní ilé Farisi, ó mú ṣágo kékeré alabasita òróró ìkunra wá,
Moilai fi wadela: i hou hamosu uda da Yesu E da Fa: lisi ea diasuga misi nabi dagoi. Amalalu, e da manoma gabusiga: gala amo igi faigelei ganodini sali, gaguli misini, doaga: i.
38 Ó sì dúró tì í lẹ́bàá ẹsẹ̀ rẹ̀ lẹ́yìn, ó ń sọkún, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí i fi omijé wẹ̀ ẹ́ ní ẹsẹ̀, ó sì ń fi irun orí rẹ nù ún nù, ó sì ń fi ẹnu kò ó ní ẹsẹ̀, ó sì ń fi òróró kùn wọ́n.
Amalalu, e da Yesu Ea baligia Ea emo gadenenewane lela, dinanu. E da Yesu Ea emo amo ea si hanoga dodofelalu, ea dialuma hinabo amoga doga: i. E da Yesu Ea emo nonogone, amola amoga gabusiga: manoma sogagala: i.
39 Nígbà tí Farisi tí ó pè é sì rí i, ó wí nínú ara rẹ̀ pé, “Ọkùnrin yìí ìbá ṣe wòlíì, ìbá mọ ẹni àti irú ẹni tí obìnrin yìí jẹ́ tí ń fi ọwọ́ kàn an, nítorí ẹlẹ́ṣẹ̀ ni.”
Be Fa: lisi dunu (amo dunu da Yesu ea diasuga ha: i manusa: hiougi) amo hou ba: beba: le, ea dogo ganodini amane dawa: i, “Amo dunu da balofededafa esala ganiaba, E da amo uda waha Ea da: i digili ba: lalebe, amo ea wadela: i hou E da dawa: la: loba!”
40 Jesu sì dáhùn, ó wí fún un pé, “Simoni, Mo ní ohun kan sọ fún ọ.” Ó sì dáhùn pé, “Olùkọ́ máa wí.”
Be Yesu da ema bu adole i, “Saimone! Na da dima sia: mu galebe!” Saimone da amane sia: i, “Defea! Olelesu! Di sia: ma!”
41 “Ayánilówó kan wà tí ó ní ajigbèsè méjì: ọ̀kan jẹ ẹ́ ní ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta owó idẹ, èkejì sì jẹ ẹ́ ní àádọ́ta.
Amalalu, Yesu E amane sia: i, “Dunu aduna esalu! Afae da eno bagade gagui dunuma 500 gina dabe bu imunu galu. Eno da ema50gina fawane bu dabe imunu galu.
42 Nígbà tí wọn kò sì ní ohun tí wọn ó san, ó dáríjì àwọn méjèèjì. Wí nínú àwọn méjèèjì, ta ni yóò fẹ́ ẹ jù?”
Be ela amo dabe bu imunu hamedeiba: le, bagade gagui dunu da dabe mae lale, ela hou gogolema: ne olofoi. Amaiba: le, nowa dunu da amo bagade gagui dunuma baligiliwane asigima: bela: ?”
43 Simoni dáhùn wí pé, “Mo ṣe bí ẹni tí ó dáríjì jù ni.” Jesu wí fún un pé, “Ìwọ ti dájọ́ náà dáradára.”
Saimone da bu adole i, “Amabela: ? Dunu amo bagade gagui dunu da baligili dabe mae lale gogolema: ne olofoi, amo dunu da ema baligiliwane asigimu.” Yesu E amane sia: i, “Hananewane! Di da moloiwane sia: i!”
44 Ó sì yípadà sí obìnrin náà, ó wí fún Simoni pé, “Wo obìnrin yìí? Èmi wọ ilé rẹ, ìwọ kò fi omi wẹ ẹsẹ̀ fún mi: ṣùgbọ́n, omijé rẹ̀ ni ó fi ń rọ̀jò sí mi lẹ́sẹ̀ irun orí ni ó fi ń nù wọ́n nù.
Amalalu, Yesu da amo udama sinidigili, Saimonema amane sia: i, “Dia da amo uda ea hou ba: bela: ? Na da dia diasuga golili sa: ili, di da Na emo dodofemusa: hano hame i. Be e da ea si hanoga Na emo dodofelalu, amola ea dialuma hinaboga doga: le dagoi.
45 Ìwọ kò fi ìfẹnukonu fún mi: ṣùgbọ́n òun, nígbà tí mo ti wọ ilé, kò dẹ́kun ẹnu fífi kò mí lẹ́sẹ̀.
Di da Nama hame nonogoi. Be Na misini, mae yolelewane e da Na emo nonogonana.
46 Ìwọ kò fi òróró pa mí lórí, ṣùgbọ́n òun ti fi òróró pa mí lẹ́sẹ̀.
Dia da Na dialuma da: iya susuligi hame sogadigi. Be e da Na emoga gabusiga: manoma sogagala: su.
47 Ǹjẹ́ mo wí fún ọ, A dárí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ tí ó pọ̀ jì í: nítorí tí ó ní ìfẹ́ púpọ̀: ẹni tí a sì dárí díẹ̀ jì, òun náà ni ó ní ìfẹ́ díẹ̀.”
Amaiba: le, Na dima sia: sa, ‘Gode da ea wadela: i hou bagohame dialu, amo gogolema: ne olofoi dagoi. Amo dawa: beba: le, ea asigi hou da bagade baligiliwane diala. Be nowa da wadela: i hou fonobahadi fawane Gode da gogolema: ne olofosea, amo dunu ea asigi hou da fonobahadi fawane.”
48 Ó sì wí fún un pé, “A dárí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ jì ọ́!”
Amalalu, Yesu da amo udama amane sia: i, “Dia wadela: i hou da gogolema: ne olofoi dagoi!”
49 Àwọn tí ó bá a jókòó jẹun sì bẹ̀rẹ̀ sí í rò nínú ara wọn pé, “Ta ni èyí tí ń dárí ẹ̀ṣẹ̀ ji ni pẹ̀lú?”
Eno dunu Yesu amola gilisili ha: i nanebe, da amane sia: dasu, “Amo dunu da nowa dunula: ? E da wadela: i hou gogolema: ne olofosu hamobeba: le, e da nowala: ?”
50 Ó sì dáhùn wí fún obìnrin náà pé, “Ìgbàgbọ́ rẹ gbà ọ́ là, máa lọ ní àlàáfíà.”
Amalalu, Yesu da udama amane sia: i, “Di da dafawaneyale dawa: beba: le, Gode Ea Gaga: su lai dagoi. Olofole masa!”

< Luke 7 >