< Luke 6 >

1 Ní ọjọ́ ìsinmi kejì, Jesu ń kọjá láàrín oko ọkà; àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì ń ya ìpẹ́ ọkà, wọ́n sì ń jẹ ẹ́.
اَچَرَنْچَ پَرْوَّنو دْوِتِییَدِناتْ پَرَں پْرَتھَمَوِشْرامَوارے شَسْیَکْشیتْرینَ یِیشورْگَمَنَکالے تَسْیَ شِشْیاح کَنِشَں چھِتّوا کَریشُ مَرْدَّیِتْوا کھادِتُماریبھِرے۔
2 Àwọn kan nínú àwọn Farisi sì wí fún wọn pé, “Ki lo de tí ẹ̀yin fi ń ṣe èyí tí kò yẹ láti ṣe ní ọjọ́ ìsinmi?”
تَسْماتْ کِیَنْتَح پھِرُوشِنَسْتانَوَدَنْ وِشْرامَوارے یَتْ کَرْمَّ نَ کَرْتَّوْیَں تَتْ کُتَح کُرُتھَ؟
3 Jesu sì dá wọn lóhùn pé, “Ẹ̀yin kò kà nípa ohun tí Dafidi ṣe, nígbà tí ebi ń pa òun tìkára rẹ̀ àti àwọn tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ̀;
یِیشُح پْرَتْیُواچَ دایُودْ تَسْیَ سَنْگِنَشْچَ کْشُدھارْتّاح کِں چَکْرُح سَ کَتھَمْ اِیشْوَرَسْیَ مَنْدِرَں پْرَوِشْیَ
4 bi ó ti wọ ilé Ọlọ́run lọ, tí ó sì mú àkàrà ìfihàn tí ó sì jẹ ẹ́, tí ó sì fi fún àwọn tí ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú; tí kò yẹ fún un láti jẹ, bí kò ṣe fún àwọn àlùfáà nìkan ṣoṣo?”
یے دَرْشَنِییاح پُوپا یاجَکانْ وِنانْیَسْیَ کَسْیاپْیَبھوجَنِییاسْتانانِییَ سْوَیَں بُبھَجے سَنْگِبھْیوپِ دَدَو تَتْ کِں یُشْمابھِح کَداپِ ناپاٹھِ؟
5 Ó sì wí fún wọn pé, “Ọmọ Ènìyàn ni Olúwa Ọjọ́ Ìsinmi.”
پَشْچاتْ سَ تانَوَدَتْ مَنُجَسُتو وِشْرامَوارَسْیاپِ پْرَبھُ رْبھَوَتِ۔
6 Ní ọjọ́ ìsinmi mìíràn, ó wọ inú Sinagọgu lọ, ó sì ń kọ́ni, ọkùnrin kan sì ń bẹ níbẹ̀ tí ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ rọ.
اَنَنْتَرَمْ اَنْیَوِشْرامَوارے سَ بھَجَنَگیہَں پْرَوِشْیَ سَمُپَدِشَتِ۔ تَدا تَتْسْتھانے شُشْکَدَکْشِنَکَرَ ایکَح پُمانْ اُپَتَسْتھِوانْ۔
7 Àwọn akọ̀wé àti àwọn Farisi ń ṣọ́ ọ, bóyá yóò mú un láradá ní ọjọ́ ìsinmi; kí wọn lè rí ọ̀nà láti fi ẹ̀sùn kàn án.
تَسْمادْ اَدھْیاپَکاح پھِرُوشِنَشْچَ تَسْمِنْ دوشَماروپَیِتُں سَ وِشْرامَوارے تَسْیَ سْواسْتھْیَں کَروتِ نَویتِ پْرَتِیکْشِتُماریبھِرے۔
8 Ṣùgbọ́n ó mọ èrò inú wọn, ó sì wí fún ọkùnrin náà tí ọwọ́ rẹ̀ rọ pé, “Dìde, kí o sì dúró láàrín.” Ó sì dìde dúró.
تَدا یِیشُسْتیشاں چِنْتاں وِدِتْوا تَں شُشْکَکَرَں پُماںسَں پْروواچَ، تْوَمُتّھایَ مَدھْیَسْتھانے تِشْٹھَ۔
9 Nígbà náà ni Jesu wí fún wọn pé, “Èmi bi yín léèrè, Ó ha tọ́ láti máa ṣe rere ni ọjọ́ ìsinmi, tàbí láti máa ṣe búburú? Láti gba ọkàn là, tàbí láti pa á run?”
تَسْماتْ تَسْمِنْ اُتّھِتَوَتِ یِیشُسْتانْ وْیاجَہارَ، یُشْمانْ اِماں کَتھاں پرِچّھامِ، وِشْرامَوارے ہِتَمْ اَہِتَں وا، پْرانَرَکْشَنَں پْرانَناشَنَں وا، ایتیشاں کِں کَرْمَّکَرَنِییَمْ؟
10 Nígbà tí ó sì wo gbogbo wọn yíká, ó wí fún ọkùnrin náà pé, “Na ọwọ́ rẹ.” Ó sì ṣe bẹ́ẹ̀: ọwọ́ rẹ̀ sì padà bọ̀ sípò gẹ́gẹ́ bí èkejì.
پَشْچاتْ چَتُرْدِکْشُ سَرْوّانْ وِلوکْیَ تَں مانَوَں بَبھاشے، نِجَکَرَں پْرَسارَیَ؛ تَتَسْتینَ تَتھا کرِتَ اِتَرَکَرَوَتْ تَسْیَ ہَسْتَح سْوَسْتھوبھَوَتْ۔
11 Wọ́n sì kún fún ìbínú gbígbóná; wọ́n sì bá ara wọn rò ohun tí àwọn ìbá ṣe sí Jesu.
تَسْماتْ تے پْرَچَنْڈَکوپانْوِتا یِیشُں کِں کَرِشْیَنْتِیتِ پَرَسْپَرَں پْرَمَنْتْرِتاح۔
12 Ni ọ̀kan nínú àwọn ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, Jesu lọ sí orí òkè láti gbàdúrà, ó sì fi gbogbo òru náà gbàdúrà sí Ọlọ́run.
تَتَح پَرَں سَ پَرْوَّتَمارُہْییشْوَرَمُدِّشْیَ پْرارْتھَیَمانَح کرِتْسْناں راتْرِں یاپِتَوانْ۔
13 Nígbà tí ilẹ̀ sì mọ́, ó pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀; nínú wọn ni ó sì yan méjìlá, tí ó sì sọ ní aposteli:
اَتھَ دِنے سَتِ سَ سَرْوّانْ شِشْیانْ آہُوتَوانْ تیشاں مَدھْیی
14 Simoni (ẹni tí a pè ní Peteru) àti Anderu arákùnrin rẹ̀, Jakọbu, Johanu, Filipi, Bartolomeu,
پِتَرَنامْنا کھْیاتَح شِمونْ تَسْیَ بھْراتا آنْدْرِیَشْچَ یاکُوبْ یوہَنْ چَ پھِلِپْ بَرْتھَلَمَیَشْچَ
15 Matiu, Tomasi, Jakọbu ọmọ Alfeu, Simoni tí a ń pè ní Sealoti,
مَتھِح تھوما آلْپھِییَسْیَ پُتْرو یاکُوبْ جْوَلَنْتَنامْنا کھْیاتَح شِمونْ
16 Judea arákùnrin Jakọbu, àti Judasi Iskariotu tí ó di ọ̀dàlẹ̀.
چَ یاکُوبو بھْراتا یِہُوداشْچَ تَں یَح پَرَکَریشُ سَمَرْپَیِشْیَتِ سَ اِیشْکَرِییوتِییَیِہُوداشْچَیتانْ دْوادَشَ جَنانْ مَنونِیتانْ کرِتْوا سَ جَگْراہَ تَتھا پْریرِتَ اِتِ تیشاں نامَ چَکارَ۔
17 Ó sì bá wọn sọ̀kalẹ̀, ó sì dúró ní pẹ̀tẹ́lẹ̀, pẹ̀lú ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, àti ọ̀pọ̀ ìjọ ènìyàn, láti gbogbo Judea, àti Jerusalẹmu, àti agbègbè Tire àti Sidoni, tí wọ́n wá láti gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀, àti láti gba ìmúláradá kúrò nínú ààrùn wọn;
تَتَح پَرَں سَ تَیح سَہَ پَرْوَّتادَوَرُہْیَ اُپَتْیَکایاں تَسْتھَو تَتَسْتَسْیَ شِشْیَسَنْگھو یِہُودادیشادْ یِرُوشالَمَشْچَ سورَح سِیدونَشْچَ جَلَدھے رودھَسو جَنَنِہاشْچَ ایتْیَ تَسْیَ کَتھاشْرَوَنارْتھَں روگَمُکْتْیَرْتھَنْچَ تَسْیَ سَمِیپے تَسْتھُح۔
18 àti àwọn tí ara wọn kún fún ẹ̀mí àìmọ́ ni ó sì mú láradá.
اَمیدھْیَبھُوتَگْرَسْتاشْچَ تَنِّکَٹَماگَتْیَ سْواسْتھْیَں پْراپُح۔
19 Gbogbo ìjọ ènìyàn sì ń fẹ́ láti fọwọ́ kàn án, nítorí tí àṣẹ ń jáde lára rẹ̀, ó sì mú gbogbo wọn láradá.
سَرْوّیشاں سْواسْتھْیَکَرَنَپْرَبھاوَسْیَ پْرَکاشِتَتْواتْ سَرْوّے لوکا ایتْیَ تَں سْپْرَشْٹُں ییتِرے۔
20 Nígbà tí ó sì gbé ojú rẹ̀ sókè sí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó ní: “Alábùkún fún ni ẹ̀yin òtòṣì, nítorí tiyín ni ìjọba Ọlọ́run.
پَشْچاتْ سَ شِشْیانْ پْرَتِ درِشْٹِں کُتْوا جَگادَ، ہے دَرِدْرا یُویَں دھَنْیا یَتَ اِیشْوَرِییے راجْیے وودھِکاروسْتِ۔
21 Alábùkún fún ni ẹ̀yin tí ebi ń pa nísinsin yìí; nítorí tí ẹ ó yóò. Alábùkún fún ni ẹ̀yin tí ń sọkún nísinsin yìí: nítorí tí ẹ̀yin ó rẹ́rìn-ín.
ہے اَدھُنا کْشُدھِتَلوکا یُویَں دھَنْیا یَتو یُویَں تَرْپْسْیَتھَ؛ ہے اِہَ رودِنو جَنا یُویَں دھَنْیا یَتو یُویَں ہَسِشْیَتھَ۔
22 Alábùkún fún ni ẹ̀yin, nígbà tí àwọn ènìyàn bá kórìíra yín, tí wọ́n bá yà yín kúrò nínú ẹgbẹ́ wọn, tí wọ́n bá gàn yín, tí wọ́n bá ta orúkọ yín nù bí ohun búburú, nítorí Ọmọ Ènìyàn.
یَدا لوکا مَنُشْیَسُونو رْنامَہیتو رْیُشْمانْ رِتِییِشْیَنْتے پرِتھَکْ کرِتْوا نِنْدِشْیَنْتِ، اَدھَمانِوَ یُشْمانْ سْوَسَمِیپادْ دُورِیکَرِشْیَنْتِ چَ تَدا یُویَں دھَنْیاح۔
23 “Ẹ jẹ́ kí inú yín dùn, kí ẹ sì fò fún ayọ̀, nítorí púpọ̀ ní èrè yín ni ọ̀run. Báyìí ni àwọn baba yín ṣe ṣe sí àwọn wòlíì.
سْوَرْگے یُشْماکَں یَتھیشْٹَں پھَلَں بھَوِشْیَتِ، ایتَدَرْتھَں تَسْمِنْ دِنے پْرولَّسَتَ آنَنْدینَ نرِتْیَتَ چَ، تیشاں پُورْوَّپُرُشاشْچَ بھَوِشْیَدْوادِنَح پْرَتِ تَتھَیوَ وْیَواہَرَنْ۔
24 “Ègbé ni fún ẹ̀yin ọlọ́rọ̀ nítorí ẹ ti gba ìtùnú yín.
کِنْتُ ہا ہا دھَنَوَنْتو یُویَں سُکھَں پْراپْنُتَ۔ ہَنْتَ پَرِترِپْتا یُویَں کْشُدھِتا بھَوِشْیَتھَ؛
25 Ègbé ni fún ẹ̀yin tí ó yó, nítorí ebi yóò pa yín, Ègbé ni fún ẹ̀yin tí ń rẹ́rìn-ín nísinsin yìí, nítorí tí ẹ̀yin ó ṣọ̀fọ̀, ẹ̀yin ó sì sọkún.
اِہَ ہَسَنْتو یُویَں وَتَ یُشْمابھِح شوچِتَوْیَں رودِتَوْیَنْچَ۔
26 Ègbé ni fún yín, nígbà tí gbogbo ènìyàn bá ń sọ̀rọ̀ yín ní rere, nítorí bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni àwọn baba wọn ṣe sí àwọn wòlíì èké.
سَرْوَّیلاکَے رْیُشْماکَں سُکھْیاتَو کرِتایاں یُشْماکَں دُرْگَتِ رْبھَوِشْیَتِ یُشْماکَں پُورْوَّپُرُشا مرِشابھَوِشْیَدْوادِنَح پْرَتِ تَدْوَتْ کرِتَوَنْتَح۔
27 “Ṣùgbọ́n mo wí fún ẹ̀yin tí ń gbọ́ mi, ẹ fẹ́ àwọn ọ̀tá yín, ṣoore fún àwọn tí ó kórìíra yín.
ہے شْروتارو یُشْمَبھْیَمَہَں کَتھَیامِ، یُویَں شَتْرُشُ پْرِییَدھْوَں یے چَ یُشْمانْ دْوِشَنْتِ تیشامَپِ ہِتَں کُرُتَ۔
28 Súre fún àwọn tí ń fi yín ré, sì gbàdúrà fún àwọn tí ń kẹ́gàn yín.
یے چَ یُشْمانْ شَپَنْتِ تیبھْیَ آشِشَں دَتَّ یے چَ یُشْمانْ اَوَمَنْیَنْتے تیشاں مَنْگَلَں پْرارْتھَیَدھْوَں۔
29 Ẹni tí ó bá sì lù ọ́ ní ẹ̀rẹ̀kẹ́ kan, yí kejì sí i pẹ̀lú; àti ẹni tí ó gba agbádá rẹ, má ṣe dá a dúró láti gba ẹ̀wù àwọ̀tẹ́lẹ̀ rẹ pẹ̀lú.
یَدِ کَشْچِتْ تَوَ کَپولے چَپیٹاگھاتَں کَروتِ تَرْہِ تَں پْرَتِ کَپولَمْ اَنْیَں پَراوَرْتّیَ سَمُّکھِیکُرُ پُنَشْچَ یَدِ کَشْچِتْ تَوَ گاتْرِییَوَسْتْرَں ہَرَتِ تَرْہِ تَں پَرِدھییَوَسْتْرَمْ اَپِ گْرَہِیتُں ما وارَیَ۔
30 Sì fi fún gbogbo ẹni tí ó tọrọ lọ́dọ̀ rẹ; lọ́dọ̀ ẹni tí ó sì kó ọ ní ẹrù, má sì ṣe padà béèrè.
یَسْتْواں یاچَتے تَسْمَے دیہِ، یَشْچَ تَوَ سَمْپَتِّں ہَرَتِ تَں ما یاچَسْوَ۔
31 Gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yin sì ti fẹ́ kí ènìyàn ṣe sí yín, kí ẹ̀yin sì ṣe bẹ́ẹ̀ sí wọn pẹ̀lú.
پَریبھْیَح سْوانْ پْرَتِ یَتھاچَرَنَمْ اَپیکْشَدھْوے پَرانْ پْرَتِ یُویَمَپِ تَتھاچَرَتَ۔
32 “Ǹjẹ́ bí ẹ̀yin bá fẹ́ àwọn tí ó fẹ́ yín, ọpẹ́ kí ni ẹ̀yin ní? Àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ pẹ̀lú ń fẹ́ àwọn tí ó fẹ́ wọn.
یے جَنا یُشْماسُ پْرِییَنْتے کیوَلَں تیشُ پْرِییَمانیشُ یُشْماکَں کِں پھَلَں؟ پاپِلوکا اَپِ سْویشُ پْرِییَمانیشُ پْرِییَنْتے۔
33 Bí ẹ̀yin sì ṣoore fún àwọn tí ó ṣoore fún yín, ọpẹ́ kín ni ẹ̀yin ní? Àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ pẹ̀lú ń ṣe bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́.
یَدِ ہِتَکارِنَ ایوَ ہِتَں کُرُتھَ تَرْہِ یُشْماکَں کِں پھَلَں؟ پاپِلوکا اَپِ تَتھا کُرْوَّنْتِ۔
34 Bí ẹ̀yin bá fi fún ẹni tí ẹ̀yin ń retí láti rí gbà padà, ọpẹ́ kín ni ẹ̀yin ní? Àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ pẹ̀lú ń yá ẹlẹ́ṣẹ̀, kí wọn lè gba ìwọ̀n bẹ́ẹ̀ padà.
ییبھْیَ رِنَپَرِشودھَسْیَ پْراپْتِپْرَتْیاشاسْتے کیوَلَں تیشُ رِنے سَمَرْپِتے یُشْماکَں کِں پھَلَں؟ پُنَح پْراپْتْیاشَیا پاپِیلوکا اَپِ پاپِجَنیشُ رِنَمْ اَرْپَیَنْتِ۔
35 Ṣùgbọ́n kí ẹ̀yin fẹ́ àwọn ọ̀tá yín kí ẹ sì ṣoore, kí ẹ̀yin sì yá ẹlòmíràn, kí ẹ̀yin má ṣe retí láti rí nǹkan gbà padà; èrè yín yóò sì pọ̀, àwọn ọmọ Ọ̀gá-ògo ni a ó sì máa pè yín: nítorí tí ó ṣe rere fún aláìmoore àti fún ẹni búburú.
اَتو یُویَں رِپُشْوَپِ پْرِییَدھْوَں، پَرَہِتَں کُرُتَ چَ؛ پُنَح پْراپْتْیاشاں تْیَکْتْوا رِنَمَرْپَیَتَ، تَتھا کرِتے یُشْماکَں مَہاپھَلَں بھَوِشْیَتِ، یُویَنْچَ سَرْوَّپْرَدھانَسْیَ سَنْتانا اِتِ کھْیاتِں پْراپْسْیَتھَ، یَتو یُشْماکَں پِتا کرِتَگھْناناں دُرْوْٹَتّانانْچَ ہِتَماچَرَتِ۔
36 Ǹjẹ́ kí ẹ̀yin ní àánú, gẹ́gẹ́ bí Baba yín sì ti ní àánú.
اَتَ ایوَ سَ یَتھا دَیالُ رْیُویَمَپِ تادرِشا دَیالَوو بھَوَتَ۔
37 “Ẹ má ṣe dá ni lẹ́jọ́, a kì yóò sì dá yín lẹ́jọ́: ẹ má ṣe dá ni lẹ́bi, a kì yóò sì dá yín lẹ́bi: ẹ dáríjì, a ó sì dáríjì yín.
اَپَرَنْچَ پَرانْ دوشِنو ما کُرُتَ تَسْمادْ یُویَں دوشِیکرِتا نَ بھَوِشْیَتھَ؛ اَدَنْڈْیانْ ما دَنْڈَیَتَ تَسْمادْ یُویَمَپِ دَنْڈَں نَ پْراپْسْیَتھَ؛ پَریشاں دوشانْ کْشَمَدھْوَں تَسْمادْ یُشْماکَمَپِ دوشاح کْشَمِشْیَنْتے۔
38 Ẹ fi fún ni, a ó sì fi fún yín; òsùwọ̀n dáradára, àkìmọ́lẹ̀, àti àmìpọ̀, àkúnwọ́sílẹ̀, ni a ó wọ́n si àyà yín: nítorí òsùwọ̀n náà tí ẹ̀yin fi wọ́n, òun ni a ó padà fi wọ́n fún yín.”
دانانِدَتَّ تَسْمادْ یُویَں دانانِ پْراپْسْیَتھَ، وَرَنْچَ لوکاح پَرِمانَپاتْرَں پْرَدَلَیَّ سَنْچالْیَ پْرونْچالْیَ پَرِپُورْیَّ یُشْماکَں کْروڈیشُ سَمَرْپَیِشْیَنْتِ؛ یُویَں یینَ پَرِمانینَ پَرِماتھَ تینَیوَ پَرِمانینَ یُشْمَتْکرِتے پَرِماسْیَتے۔
39 Ó sì pa òwe kan fún wọn wí pé, “Afọ́jú ha lè ṣe amọ̀nà afọ́jú bí? Àwọn méjèèjì kọ́ ni yóò ṣubú sínú ihò bí?
اَتھَ سَ تیبھْیو درِشْٹانْتَکَتھامَکَتھَیَتْ، اَنْدھو جَنَح کِمَنْدھَں پَنْتھانَں دَرْشَیِتُں شَکْنوتِ؟ تَسْمادْ اُبھاوَپِ کِں گَرْتّے نَ پَتِشْیَتَح؟
40 Ẹni tí a ń kọ́ kì í ju olùkọ́ rẹ̀ lọ: ṣùgbọ́n olúkúlùkù ẹni tí a bá kọ dáradára, yóò dàbí olùkọ́ rẹ̀.
گُروح شِشْیو نَ شْریشْٹھَح کِنْتُ شِشْیے سِدّھے سَتِ سَ گُرُتُلْیو بھَوِتُں شَکْنوتِ۔
41 “Èétiṣe tí ìwọ fi ń wo ẹ̀rún igi tí ń bẹ ní ojú arákùnrin rẹ, ṣùgbọ́n ìwọ kò kíyèsi ìtì igi tí ń bẹ ní ojú ara rẹ?
اَپَرَنْچَ تْوَں سْوَچَکْشُشِ ناسامْ اَدرِشْٹْوا تَوَ بھْراتُشْچَکْشُشِ یَتّرِنَمَسْتِ تَدیوَ کُتَح پَشْیَمِ؟
42 Tàbí ìwọ ó ti ṣe lè wí fún arákùnrin rẹ pé, ‘Arákùnrin, jẹ́ kí èmi yọ ẹ̀rún igi tí ń bẹ lójú rẹ,’ nígbà tí ìwọ tìkára rẹ kò kíyèsi ìtì igi tí ń bẹ lójú rẹ? Ìwọ àgàbàgebè, kọ́kọ́ yọ ìtí igi jáde kúrò lójú ara rẹ ná, nígbà náà ni ìwọ ó sì tó ríran gbangba láti yọ èérún igi tí ń bẹ lójú arákùnrin rẹ kúrò.
سْوَچَکْشُشِ یا ناسا وِدْیَتے تامْ اَجْناتْوا، بھْراتَسْتَوَ نیتْراتْ ترِنَں بَہِح کَرومِیتِ واکْیَں بھْراتَرَں کَتھَں وَکْتُں شَکْنوشِ؟ ہے کَپَٹِنْ پُورْوَّں سْوَنَیَناتْ ناساں بَہِح کُرُ تَتو بھْراتُشْچَکْشُشَسْترِنَں بَہِح کَرْتُّں سُدرِشْٹِں پْراپْسْیَسِ۔
43 “Nítorí igi rere kì í so èso búburú; bẹ́ẹ̀ ni igi búburú kì í so èso rere.
اَنْیَنْچَ اُتَّمَسْتَرُح کَداپِ پھَلَمَنُتَّمَں نَ پھَلَتِ، اَنُتَّمَتَرُشْچَ پھَلَمُتَّمَں نَ پھَلَتِ کارَنادَتَح پھَلَیسْتَرَوو جْنایَنْتے۔
44 Olúkúlùkù igi ni a ń fi èso rẹ̀ mọ̀ ọn; nítorí lórí ẹ̀gún òṣùṣú, ènìyàn kì í ká èso ọ̀pọ̀tọ́ bẹ́ẹ̀ ni lórí ẹ̀gún ọ̀gàn a kì í ká èso àjàrà.
کَنْٹَکِپادَپاتْ کوپِ اُڈُمْبَرَپھَلانِ نَ پاتَیَتِ تَتھا شرِگالَکولِورِکْشادَپِ کوپِ دْراکْشاپھَلَں نَ پاتَیَتِ۔
45 Ènìyàn rere láti inú yàrá ìṣúra rere ọkàn rẹ̀ ní mú ohun rere jáde wá; àti ènìyàn búburú láti inú ìṣúra búburú ọkàn rẹ̀ ní í mú ohun búburú jáde wá: nítorí láti inú ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ọkàn ní ẹnu ti máa sọ jáde.
تَدْوَتْ سادھُلوکونْتَحکَرَنَرُوپاتْ سُبھانْڈاگارادْ اُتَّمانِ دْرَوْیانِ بَہِح کَروتِ، دُشْٹو لوکَشْچانْتَحکَرَنَرُوپاتْ کُبھانْڈاگاراتْ کُتْسِتانِ دْرَوْیانِ نِرْگَمَیَتِ یَتونْتَحکَرَناناں پُورْنَبھاوانُرُوپانِ وَچاںسِ مُکھانِّرْگَچّھَنْتِ۔
46 “Nítorí náà, èéṣe tí ẹ̀yin ń pè mí ní, ‘Olúwa, Olúwa,’ tí ẹ̀yin kò sì ṣe ohun tí mo wí?
اَپَرَنْچَ مَماجْنانُرُوپَں ناچَرِتْوا کُتو ماں پْرَبھو پْرَبھو اِتِ وَدَتھَ؟
47 Ẹnikẹ́ni tí ó tọ̀ mí wá, tí ó sì ń gbọ́ ọ̀rọ̀ mi, tí ó sì ń ṣe é, èmi yóò fi ẹni tí ó jọ hàn yín.
یَح کَشْچِنْ مَمَ نِکَٹَمْ آگَتْیَ مَمَ کَتھا نِشَمْیَ تَدَنُرُوپَں کَرْمَّ کَروتِ سَ کَسْیَ سَدرِشو بھَوَتِ تَدَہَں یُشْمانْ جْناپَیامِ۔
48 Ó jọ ọkùnrin kan, tí ó kọ́ ilé, tí ó sì wa ilẹ̀ jìn, tí ó sì fi ìpìlẹ̀ sọlẹ̀ lórí àpáta, nígbà tí kíkún omi sì dé, ìgbì omi kọlu ilé náà, kò sì lè mì ín nítorí tí a fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ lórí àpáta.
یو جَنو گَبھِیرَں کھَنِتْوا پاشانَسْتھَلے بھِتِّں نِرْمّایَ سْوَگرِہَں رَچَیَتِ تینَ سَہَ تَسْیوپَما بھَوَتِ؛ یَتَ آپْلاوِجَلَمیتْیَ تَسْیَ مُولے ویگینَ وَہَدَپِ تَدْگیہَں لاڈَیِتُں نَ شَکْنوتِ یَتَسْتَسْیَ بھِتِّح پاشانوپَرِ تِشْٹھَتِ۔
49 Ṣùgbọ́n ẹni tí ó gbọ́, tí kò sì ṣe é, ó dàbí ọkùnrin tí ó kọ́ ilé sí orí ilẹ̀ láìní ìpìlẹ̀; nígbà tí ìgbì omi kọlù ú, lọ́gán, ó sì wó; wíwó ilé náà sì pọ̀ púpọ̀.”
کِنْتُ یَح کَشْچِنْ مَمَ کَتھاح شْرُتْوا تَدَنُرُوپَں ناچَرَتِ سَ بھِتِّں وِنا مرِدُپَرِ گرِہَنِرْمّاتْرا سَمانو بھَوَتِ؛ یَتَ آپْلاوِجَلَماگَتْیَ ویگینَ یَدا وَہَتِ تَدا تَدْگرِہَں پَتَتِ تَسْیَ مَہَتْ پَتَنَں جایَتے۔

< Luke 6 >