< Luke 4 >

1 Jesu sì kún fún Ẹ̀mí Mímọ́, ó padà ti Jordani wá, a sì ti ọwọ́ Ẹ̀mí darí rẹ̀ sí ijù,
Andin Əysa Muⱪǝddǝs Roⱨⱪa tolup, Iordan dǝryasidin ⱪaytip kelip, Roⱨ tǝripidin qɵl-bayawanƣa elip berildi.
2 Ogójì ọjọ́ ni a fi dán an wò lọ́wọ́ èṣù. Kò sì jẹ ohunkóhun ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì: nígbà tí wọ́n sì parí, lẹ́yìn náà ni ebi wá ń pa á.
U u yǝrdǝ ⱪiriⱪ kün Iblis tǝripidin sinaldi. U bu künlǝrdǝ ⱨeqnǝrsǝ yemidi. Künlǝr ayaƣlaxⱪanda, uning ⱪorsiⱪi taza aqⱪanidi.
3 Èṣù sì wí fún un pé, “Bí ìwọ bá ṣe Ọmọ Ọlọ́run, pàṣẹ fún òkúta yìí kí ó di àkàrà.”
Əmdi Iblis uningƣa: — Sǝn ǝgǝr Hudaning Oƣli bolsang, muxu taxⱪa: «Nanƣa aylan!» dǝp buyruƣin — dedi.
4 Jesu sì dáhùn, ó wí fún un pé, “A ti kọ̀wé rẹ̀ pé, ‘Ènìyàn kì yóò wà láààyè nípa àkàrà nìkan.’”
Əysa uningƣa jawabǝn: — [Tǝwratta]: «Insan pǝⱪǝt nan bilǝnla ǝmǝs, bǝlki Hudaning ⱨǝrbir sɵzi bilǝnmu yaxaydu» dǝp yezilƣan, — dedi.
5 Lójúkan náà, èṣù sì mú un lọ sí orí òkè gíga, ó sì fi gbogbo ilẹ̀ ọba ayé hàn án.
Iblis yǝnǝ uni egiz bir taƣⱪa baxlap qiⱪip, bir dǝⱪiⱪǝ iqidǝ dunyadiki barliⱪ dɵlǝtlǝrni uningƣa kɵrsǝtti.
6 Èṣù sì wí fún un pé, “Ìwọ ni èmi ó fi gbogbo agbára yìí àti ògo wọn fún: nítorí á sá ti fi fún mi. Ẹnikẹ́ni tí ó bá sì wù mí, èmi a fi í fún.
Iblis uningƣa: — Mǝn bu ⱨakimiyǝtning ⱨǝmmisini wǝ uningƣa tǝwǝ barliⱪ xanuxǝwkǝtlǝrni sanga tǝⱪdim ⱪilimǝn; qünki bular manga tapxurulƣan, mǝn uni kimgǝ berixni halisam, xuningƣa berimǝn.
7 Ǹjẹ́ bí ìwọ bá foríbalẹ̀ fún mi, gbogbo rẹ̀ ni yóò jẹ́ tìrẹ.”
Əgǝr bax ⱪoyup manga sǝjdǝ ⱪilsang, bularning ⱨǝmmisi seningki bolidu, — dedi.
8 Jesu sì dáhùn ó sì wí fún un pé, “Kúrò lẹ́yìn mi, Satani, nítorí tí a kọ̀wé rẹ̀ pé, ‘Ìwọ foríbalẹ̀ fún Olúwa Ọlọ́run rẹ, òun nìkan ṣoṣo ni kí ìwọ kí ó sì máa sìn.’”
Əysa uningƣa jawab berip: — [Tǝwratta]: «Pǝrwǝrdigar Hudayingƣila ibadǝt ⱪil, pǝⱪǝt Uningla ⱪulluⱪida bol!» dǝp yezilƣan, — dedi.
9 Èṣù sì mú un lọ sí Jerusalẹmu, ó sì gbé e lé ibi ṣóńṣó tẹmpili, ó sì wí fún un pé, “Bí ìwọ bá ṣe Ọmọ Ọlọ́run, bẹ́ sílẹ̀ fún ara rẹ láti ibí yìí.
Andin Iblis uni Yerusalemƣa elip bardi wǝ uni ibadǝthanining ǝng egiz jayiƣa turƣuzup: — Hudaning Oƣli bolsang, ɵzüngni pǝskǝ taxlap baⱪⱪin!
10 A sá ti kọ̀wé rẹ̀ pé, “‘Yóò pàṣẹ fún àwọn angẹli rẹ̀ nítorí rẹ, láti máa ṣe ìtọ́jú rẹ;
Qünki [Tǝwratta]: «[Huda] Ɵz pǝrixtilirigǝ seni ⱪoƣdax ⱨǝⱪⱪidǝ ǝmr ⱪilidu»;
11 àti pé ní ọwọ́ wọn ni wọn ó gbé ọ sókè, kí ìwọ kí ó má ba à fi ẹsẹ̀ rẹ gbún òkúta.’”
wǝ, «Putungning taxⱪa urulup kǝtmǝsliki üqün, ular seni ⱪollirida kɵtürüp yüridu» dǝp yezilƣan, — dedi.
12 Jesu sì dáhùn ó wí fún un pé, “A ti kọ́ pé, ‘Ìwọ kò gbọdọ̀ dán Olúwa Ọlọ́run rẹ wò.’”
Əysa uningƣa: — «[Tǝwratta]: «Pǝrwǝrdigar Hudayingni siniƣuqi bolma!» dǝpmu yezilƣan, — dedi.
13 Nígbà tí èṣù sì parí ìdánwò náà gbogbo, ó fi í sílẹ̀ lọ fun sá à kan.
Iblis barliⱪ sinaxlarni ixlitip qiⱪⱪandin keyin, uni waⱪtinqǝ taxlap ketip ⱪaldi.
14 Jesu sì fi agbára Ẹ̀mí padà wá sí Galili, òkìkí rẹ̀ sì kàn kálẹ̀ ní gbogbo agbègbè tí ó yí i ká.
Əysa Roⱨning küq-ⱪudriti iqidǝ Galiliyǝ ɵlkisigǝ ⱪaytip kǝldi. Xuning bilǝn uning hǝwǝr-xɵⱨriti ǝtraptiki ⱨǝrbir yurtlarƣa tarⱪaldi.
15 Ó sì ń kọ́ni nínú Sinagọgu wọn; a ń yìn ín lógo láti ọ̀dọ̀ gbogbo àwọn ènìyàn wá.
U ularning sinagoglirida tǝlim bergili turdi wǝ ularning uluƣlaxliriƣa sazawǝr boldi.
16 Ó sì wá sí Nasareti, níbi tí a gbé ti tọ́ ọ dàgbà: bí ìṣe rẹ̀ ti rí, ó sì wọ inú Sinagọgu lọ ní ọjọ́ ìsinmi, ó sì dìde láti kàwé.
U ɵzi beⱪip qong ⱪilinƣan yurti Nasarǝtkǝ kelip, xabat küni adǝttikidǝk sinagogⱪa kirdi wǝ xundaⱪla [muⱪǝddǝs yazmilarni] oⱪuxⱪa ɵrǝ turdi
17 A sì fi ìwé wòlíì Isaiah fún un. Nígbà tí ó sì ṣí ìwé náà, ó rí ibi tí a gbé kọ ọ́ pé:
wǝ Tǝwrattiki «Yǝxaya» degǝn ⱪisim uningƣa tapxuruldi. U oram yazmini eqip, munu sɵzlǝr yezilƣan yǝrni tepip oⱪudi:
18 “Ẹ̀mí Olúwa ń bẹ lára mi, nítorí tí ó fi àmì òróró yàn mí láti wàásù ìyìnrere fún àwọn òtòṣì. Ó ti rán mi wá láti wàásù ìdásílẹ̀ fún àwọn ìgbèkùn, àti ìmúnríran fún àwọn afọ́jú, àti láti jọ̀wọ́ àwọn tí a pa lára lọ́wọ́,
— «Pǝrwǝrdigarning Roⱨi mening wujudumda, Qünki U meni yoⱪsullarƣa hux hǝwǝrlǝr yǝtküzüxkǝ mǝsiⱨ ⱪildi. Tutⱪunlarƣa azadliⱪni, Wǝ korlarƣa kɵrüx xipasini jakarlaxⱪa, Ezilgǝnlǝrni halas ⱪilixⱪa, Pǝrwǝrdigarning xapaǝt kɵrsitidiƣan yilini jakarlaxⱪa meni ǝwǝtti».
19 láti kéde ọdún ojúrere Olúwa.”
20 Ó sì pa ìwé náà dé, ó fi í fún ìránṣẹ́, ó sì jókòó. Gbogbo àwọn tí ó ń bẹ nínú Sinagọgu sì tẹjúmọ́ ọn.
U yazmini türüwetip, sinagog hizmǝtqisigǝ ⱪayturup berip, olturdi. Sinagogta olturƣanlarning ⱨǝmmisining kɵzliri uningƣa tikilip turatti.
21 Ó sì bẹ̀rẹ̀ sí í wí fún wọn pé, “Lónìí ìwé mímọ́ yìí ṣẹ ní etí yín.”
U kɵpqilikkǝ: — Mana bu ayǝt bügün ⱪuliⱪinglarƣa anglanƣinida ǝmǝlgǝ axurulmaⱪta, — dedi.
22 Gbogbo wọn sì jẹ́rìí rẹ̀, háà sì ṣe wọ́n sí ọ̀rọ̀ oore-ọ̀fẹ́ tí ń jáde ní ẹnu rẹ̀, wọ́n sì wí pé, “Ọmọ Josẹfu kọ́ yìí?”
Ⱨǝmmisi uning yahxi gepini ⱪilixip, uning aƣzidin qiⱪiwatⱪan xapaǝtlik sɵzlirigǝ ⱨǝyran ⱪelixip: — Bu Yüsüpning oƣli ǝmǝsmu? — deyixti.
23 Jesu sì wí fún wọn pé, “Lóòótọ́ ni ẹ̀yin ó pa òwe yìí sí mi pé, ‘Oníṣègùn, wo ara rẹ̀ sàn! Àwọn ohun tí àwa gbọ́ pé o ti ọwọ́ rẹ ṣe ní Kapernaumu, ṣe é níhìn-ín yìí pẹ̀lú ní ilẹ̀ ara rẹ.’”
U ularƣa: — Xübⱨisizki, silǝr manga «Əy tewip, awwal ɵzüngni saⱪayt!» degǝn tǝmsilni kǝltürüp, «Hǝwǝr tapⱪinimizdǝk, Kǝpǝrnaⱨum xǝⱨiridǝ nemǝ ixlar yüz bǝrgǝn bolsa, muxu yǝrdimu, ɵz yurtungdimu xularni kɵrsǝtmǝmsǝn?» dǝwatisilǝr, — dedi.
24 Ó sì wí pé, “Lóòótọ́ ni mo wí fún un yín, kò sí wòlíì tí a tẹ́wọ́gbà ní ilẹ̀ baba rẹ̀.
— Biraⱪ xuni silǝrgǝ bǝrⱨǝⱪ eytip ⱪoyayki, ⱨeqⱪandaⱪ pǝyƣǝmbǝr ɵz yurti tǝripidin ⱪobul ⱪilinƣan ǝmǝs.
25 Ṣùgbọ́n mo wí fún un yín nítòótọ́, opó púpọ̀ ni ó wà ní Israẹli nígbà ọjọ́ wòlíì Elijah, nígbà tí ọ̀run fi sé ní ọdún mẹ́ta òun oṣù mẹ́fà, nígbà tí ìyàn ńlá fi mú ká ilẹ̀ gbogbo.
Mǝn silǝrgǝ xu ⱨǝⱪiⱪǝtni ǝslitimǝnki, Ilyas [pǝyƣǝmbǝr]ning waⱪtida, asman uda üq yil altǝ ay etilip, dǝⱨxǝtlik bir ⱪǝⱨǝtqilik barliⱪ zeminni basⱪanda, Israilda nurƣun tul ayallar bar idi;
26 Kò sì sí ẹnìkan nínú wọn tí a rán Elijah sí, bí kò ṣe sí obìnrin opó kan ní Sarefati, ìlú kan ní Sidoni.
biraⱪ Ilyas ularning ⱨeqⱪaysisining ⱪexiƣa ǝmǝs, bǝlki Zidonning Zarǝfat xǝⱨiridiki bir tul ayalning ⱪexiƣila ǝwǝtilgǝn.
27 Adẹ́tẹ̀ púpọ̀ ní sì ń bẹ ní Israẹli nígbà wòlíì Eliṣa; kò sì ṣí ọ̀kan nínú wọn tí a wẹ̀nùmọ́, bí kò ṣe Naamani ará Siria.”
Wǝ [xuningƣa ohxax], Elixa pǝyƣǝmbǝrning waⱪtida, Israilda mahaw kesiligǝ giriptar bolƣanlar nurƣun bolsimu, lekin Suriyǝlik Naamandin baxⱪa, ⱨeqⱪaysisi saⱪaytilƣan ǝmǝs! — dedi.
28 Nígbà tí gbogbo àwọn tí ó wà nínú Sinagọgu gbọ́ nǹkan wọ̀nyí, inú bi wọ́n gidigidi,
Sinagogdikilǝr bu sɵzlǝrni anglap, ⱨǝmmisi ⱪattiⱪ ƣǝzǝplǝndi;
29 wọ́n sì dìde, wọ́n tì í sóde sí ẹ̀yìn ìlú, wọ́n sì fà á lọ sí bèbè òkè níbi tí wọ́n gbé tẹ ìlú wọn dó, kí wọn bá à lè sọ sílẹ̀ ní ògèdèǹgbé.
ornidin turuxup, uni xǝⱨǝrdin ⱨǝydǝp qiⱪirip, xu xǝⱨǝr jaylaxⱪan taƣning lewigǝ ǝqiⱪip, tik yardin taxliwǝtmǝkqi boluxti.
30 Ṣùgbọ́n ó kọjá láàrín wọn, ó bá tirẹ̀ lọ.
Lekin u ularning arisidin bimalal ɵtüp, ɵz yoliƣa qiⱪip kǝtti.
31 Ó sì sọ̀kalẹ̀ wá sí Kapernaumu, ìlú kan ní Galili, ó sì ń kọ́ wọn ní ọjọ́ ìsinmi.
U Galiliyǝ ɵlkisining Kǝpǝrnaⱨum degǝn bir xǝⱨirigǝ qüxti, u yǝrdǝ xabat künliridǝ hǝlⱪⱪǝ tǝlim berǝtti.
32 Ẹnu sì yà wọ́n sí ẹ̀kọ́ rẹ̀: nítorí tàṣẹtàṣẹ ni ọ̀rọ̀ rẹ̀.
Ular uning tǝlimigǝ ⱨǝyran ⱪelixti, qünki uning sɵzi tolimu nopuzluⱪ idi.
33 Ọkùnrin kan sì wà nínú Sinagọgu, ẹni tí ó ní ẹ̀mí àìmọ́, ó kígbe ní ohùn rara,
Əmdi sinagogta napak jinning roⱨi qaplaxⱪan bir kixi bolup, [uningdiki jin] ⱪattiⱪ awazda:
34 “Ó wí pé, kín ni ṣe tàwa tìrẹ, Jesu ará Nasareti? Ìwọ́ wá láti pa wá run bí? Èmí mọ ẹni tí ìwọ í ṣe, Ẹni Mímọ́ Ọlọ́run.”
— Əy Nasarǝtlik Əysa, sening biz bilǝn nemǝ karing?! Bizni yoⱪatⱪili kǝldingmu? Mǝn sening kimlikingni bilimǝn, Hudaning Muⱪǝddǝs Bolƣuqisisǝn! — dǝp towlap kǝtti.
35 Jesu sì bá a wí gidigidi, ó wí fun pe, “Pa ẹnu rẹ mọ́, kí o sì jáde lára rẹ̀.” Nígbà tí ẹ̀mí èṣù náà sì gbé e ṣánlẹ̀ ní àwùjọ, ó jáde kúrò lára rẹ̀, kò sì pa á lára.
Lekin Əysa jinƣa tǝnbiⱨ berip: — Aƣzingni yum! Uningdin qiⱪ! — dewidi, jin ⱨeliⱪi adǝmni halayiⱪ otturisida yiⱪitiwetip, uningdin qiⱪip kǝtti. Lekin uningƣa ⱨeq zǝrǝr yǝtküzmidi.
36 Ẹnu sì ya gbogbo wọn, wọ́n sì ń bá ara wọn sọ wí pé, “Irú ẹ̀kọ́ kín ni èyí? Nítorí pẹ̀lú àṣẹ àti agbára ni ó fi bá àwọn ẹ̀mí àìmọ́ wí, wọ́n sì jáde kúrò.”
Ⱨǝmmǝylǝn buningdin ⱪattiⱪ ⱨǝyran boluxup, bir-birigǝ: — Bu zadi ⱪandaⱪ ix! U dǝrwǝⱪǝ ⱨoⱪuⱪ wǝ ⱪudrǝt bilǝn napak roⱨlarƣa ǝmr ⱪilsila, ular qiⱪip ketidikǝn, — deyixti.
37 Òkìkí rẹ̀ sì kàn níbi gbogbo ní agbègbè ilẹ̀ náà yíká.
Xuning bilǝn uning hǝwǝr-xɵⱨriti ǝtraptiki ⱨǝrbir yurtlarƣa tarⱪaldi.
38 Nígbà tí ó sì dìde kúrò nínú Sinagọgu, ó sì wọ̀ ilé Simoni lọ; ibà sì ti dá ìyá ìyàwó Simoni dùbúlẹ̀, wọ́n sì bẹ̀ ẹ́ nítorí rẹ̀.
Əysa sinagogtin qiⱪip, Simonning ɵyigǝ kirdi. Lekin Simonning ⱪeynanisi eƣir tǝp kesili bolup ⱪalƣanidi; ular Əysadin uning ⱨajitidin qiⱪixini ɵtündi.
39 Ó sì súnmọ́ ọ, ó bá ibà náà wí; ibà sì náà sì fi sílẹ̀. O sì dìde lọ́gán, ó ń ṣe ìránṣẹ́ fún wọn.
U ayalning bexida turup, tǝpkǝ tǝnbiⱨ beriwidi, tǝp xuan uningdin kǝtti. U dǝrⱨal ornidin turup, ularni kütüxkǝ baxlidi.
40 Nígbà tí oòrùn sì ń wọ̀, àwọn ènìyàn gbe àwọn aláìsàn, tó ní onírúurú àìsàn wá sọ́dọ̀ Jesu; ó sì fi ọwọ́ lé olúkúlùkù wọn, ó sì mú wọn láradá.
Kün petixi bilǝnla, kixilǝr ⱨǝrhil kesǝllǝrgǝ giriptar bolƣan yeⱪinliri bolsila, ularni uning aldiƣa elip kelixti. U ularƣa bir-birlǝp ⱪolini tǝgküzüp, ularni saⱪaytti.
41 Àwọn ẹ̀mí èṣù sì jáde lára ẹni púpọ̀ pẹ̀lú, wọ́n ń kígbe, wí pé, “Ìwọ ni Ọmọ Ọlọ́run!” Ó sì ń bá wọn wí kò sì jẹ́ kí wọn kí ó fọhùn, nítorí tí wọ́n mọ̀ pé Òun ni Kristi náà.
Kixilǝrgǝ qaplaxⱪan nurƣun jinlar ulardin qiⱪip: «Sǝn Hudaning Oƣli!» dǝp towlap ketǝtti. Lekin u ularƣa tǝnbiⱨ berip, sɵz ⱪilixiƣa yol ⱪoymidi; qünki ular uning Mǝsiⱨ ikǝnlikini bilǝtti.
42 Nígbà tí ilẹ̀ sì mọ́, Jesu sì jáde lọ, ó sì ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀. Ìjọ ènìyàn sì ń wá a kiri, wọ́n sì tọ̀ ọ́ wá, wọ́n sì dá a dúró, nítorí kí ó má ba à lọ kúrò lọ́dọ̀ wọn.
Kün qiⱪixi bilǝn, u xǝⱨǝrdin qiⱪip, pinⱨan bir jayƣa kǝtti. Biraⱪ top-top halayiⱪ uni izdǝp yürǝtti; ular uni tapⱪanda aldiƣa kelip, uni arimizda ⱪalsun dǝp ketixidin tosmaⱪqi boluxti.
43 Ṣùgbọ́n ó sì wí fún wọn pé, “Èmi kò lè ṣàìmá wàásù ìyìnrere ti ìjọba Ọlọ́run fún àwọn ìlú mìíràn pẹ̀lú, nítorí náà ni a sá ṣe rán mi.”
Lekin u ularƣa: — Hudaning padixaⱨliⱪining hux hǝwirini baxⱪa xǝⱨǝr-yezilarƣimu yǝtküzüxüm kerǝk; qünki mǝn dǝl bu ixⱪa ǝwǝtilgǝnmǝn, — dedi.
44 Ó sì ń wàásù nínú Sinagọgu ti Judea.
Xuning bilǝn u Galiliyǝdiki sinagoglarda tǝlim berip yüriwǝrdi.

< Luke 4 >