< Luke 19 >

1 Jesu sì wọ Jeriko lọ, ó sì ń kọjá láàrín rẹ̀.
Yeecu do yarico la cukenti morece.
2 Sì kíyèsi i, ọkùnrin kan wà tí a ń pè ní Sakeu, ó sì jẹ́ olórí agbowó òde kan, ó sì jẹ́ ọlọ́rọ̀.
Nikange wi deu cero zakka, dur nobo yo dortiye, nii cwika,
3 Ó sì ń fẹ́ láti rí ẹni tí Jesu jẹ́: kò sì lè rí i, nítorí ọ̀pọ̀ ènìyàn, àti nítorí tí òun jẹ́ ènìyàn kúkúrú.
Con mani no co to keno we yecudi. La co dol bo toka wor, nobo durce, take con nii bi kwen.
4 Ó sì súré síwájú, ó gun orí igi sikamore kan, kí ó bà lè rí i: nítorí tí yóò kọjá lọ níhà ibẹ̀.
Laco cukken kab ya con kwiken tii nyincin naco tom co, wori Yeecu acuwi fonure cuwonin.
5 Nígbà tí Jesu sì dé ibẹ̀, ó gbé ojú sókè, ó sì rí i, ó sì wí fún un pé, “Sakeu! Yára, kí o sì sọ̀kalẹ̀; nítorí pé èmi yóò wọ ilé rẹ lónìí.”
Kambo Yeecu lau weyeri kung nuwe dii layico ki zakka yi rau wulom daten mwo da lomo.
6 Ó sì yára, ó sọ̀kalẹ̀, ó sì fi ayọ̀ gbà á.
La yilau wulumm-wulum yuwo co ki fuwor neret.
7 Nígbà tí wọ́n sì rí i, gbogbo wọn ń kùn, wí pé, “Ó lọ bá ọkùnrin ẹlẹ́ṣẹ̀ náà ní àlejò.”
La gwam ciye cin to wori, ci ma fwennati ki, ya fura lo nii bwiranke.
8 Sakeu sì dìde, ó sì wí fún Olúwa pé, “Wò ó, Olúwa, ààbọ̀ ohun ìní mi ni mo fi fún tálákà; bí mo bá sì fi èké gba ohun kan lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, èmi san án padà ní ìlọ́po mẹ́rin!”
Zakka kweni tii, ki to Teluwe, man. Kabkangum cweka miko more yob nane fuwa wine tana man yodiger nii cum wo ma yotiyeri, ma yila neti kiriti na'ar.
9 Jesu sì wí fún un pé, “Lónìí ni ìgbàlà wọ ilé yìí, níwọ̀n bí òun pẹ̀lú ti jẹ́ ọmọ Abrahamu.
Yeecu yi coki duwen fuloka bou fo luwe wurini nii co bi bwe Ibrayim.
10 Nítorí Ọmọ Ènìyàn dé láti wá àwọn tí ó nù kiri, àti láti gbà wọ́n là.”
Bi bwe nii bo na do kange fuloka nobo leme.
11 Nígbà tí wọ́n sì ń gbọ́ nǹkan wọ̀nyí, ó sì tẹ̀síwájú láti pa òwe kan, nítorí tí ó súnmọ́ Jerusalẹmu, àti nítorí tí wọn ń rò pé, ìjọba Ọlọ́run yóò farahàn nísinsin yìí.
Di di nuwe digewo digewo nyer. Con yoten coti tokki ki danke, wori co bi dom kange Urcalima. Cin tuken liyar kwamaro biyeken nawo.
12 Ó sì wí pé, “Ọkùnrin ọlọ́lá kan lọ sí ìlú òkèrè láti gba ìjọba kí ó sì padà.
La con yiciki nii dur cu bitine kange, ya ca yo liyar na co yilam.
13 Ó sì pe àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ mẹ́wàá, ó fi owó mina mẹ́wàá fún wọn, ó sì wí fún wọn pé, ‘Ẹ máa ṣòwò títí èmi ó fi dé!’
Con co, cangace kwob, la yi ciki kom yila kangi, ko tiye kom miye nakom fiya mwen dorcet, mimale yilau.
14 “Ṣùgbọ́n àwọn ará ìlù rẹ̀ kórìíra rẹ̀, wọ́n sì rán ikọ̀ tẹ̀lé e, wí pé, ‘Àwa kò fẹ́ kí ọkùnrin yìí jẹ ọba lórí wa.’
La nobo loce ko co, cin twom nob bwiko cek ki manya ciya ti niwo a ca ciyar dor nyer.
15 “Nígbà tí ó gba ìjọba tan, tí ó padà dé, ó pàṣẹ pé, kí a pe àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ wọ̀nyí tí òun ti fi owó fún wá sọ́dọ̀ rẹ̀, nítorí kí ó le mọ iye èrè tí olúkúlùkù ti jẹ nínú iṣẹ́ òwò wọn.
La ci ne nii wo liyoro, kambo co bou lo weri co tomi ki ciya cucine ne congetini na co nyomom kiyemero co ne ciyeu ki ciya yila kalakangtiyeu.
16 “Èyí èkínní sì wá, ó wí pé, ‘Olúwa, owó mina rẹ jèrè owó mina mẹ́wàá sí i.’
Wi kabako be cinen ki Teluwe fam mwem bo we ma fiya mwen dorcet, fambo kwob.
17 “Olúwa rẹ̀ sì wí fún un pé, ‘O ṣeun, ìwọ ọmọ ọ̀dọ̀ rere! Nítorí tí ìwọ ṣe olóòtítọ́ ní ohun kínkínní, gba àṣẹ lórí ìlú mẹ́wàá.’
Liya yi co ki dong dong canga ken, wuri mo, maken dor dike bi dure, man nenen tako cunnucut do kwob.
18 “Èyí èkejì sì wá, ó wí pé, ‘Olúwa, owó mina rẹ jèrè owó mina márùn.’
Na yobe ce bo yitiki fam mwembo Teluwe ma fiya mwembo fam bo nung.
19 “Olúwa rẹ sì wí fún un pẹ̀lú pé, ‘Ìwọ pẹ̀lú joyè ìlú márùn-ún!’
Liya yicoki tom cunnukirning mwo tamciko.
20 “Òmíràn sì wá, ó wí pé, ‘Olúwa, wò ó owó mina rẹ tí ń bẹ lọ́wọ́ mi ni mo dì sínú aṣọ pélébé kan;
Na taarece bo yitiki, fam mwembo wo man yo ken co yora mor kulene,
21 nítorí mo bẹ̀rù rẹ, àti nítorí tí ìwọ ṣe òǹrorò ènìyàn, ìwọ a máa mú èyí tí ìwọ kò fi lélẹ̀, ìwọ a sì máa ká èyí tí ìwọ kò gbìn!’
man nuwa tai mwe to, wori mor ni funere, moki to tike mo yobe, mo biye dige mo fii be.
22 “Olúwa rẹ sì wí fún un pé, ‘Ní ẹnu ara rẹ náà ni èmi ó ṣe ìdájọ́ rẹ, ìwọ ọmọ ọ̀dọ̀ búburú, ìwọ mọ̀ pé òǹrorò ènìyàn ni mí, pé, èmi a máa mú èyí tí èmi kò fi lélẹ̀ èmi a sì máa ká èyí tí èmi kò gbìn.
Liya yi co ki ki ker mwer ma mamwer bo langtiye, mwo cange bwit mo nyomon moki mo man nii maki to re dike ma yobe,
23 Èéha sì ti ṣe tí ìwọ kò fi owó mi pamọ́ sí ilé ìfowópamọ́, pé nígbà tí mo bá dé, èmi ìbá ti béèrè rẹ̀ pẹ̀lú èlé?’
ye bwi mo yobo ki kye miro fiye bini kiyeme no bwiko ma bori na yo co ki mwen.
24 “Ó sì wí fún àwọn tí ó dúró létí ibẹ̀ pé, ‘Ẹ gba owó mina náà lọ́wọ́ rẹ̀, kí ẹ sì fi í fún ẹni tí ó ní owó mina mẹ́wàá.’
Liya yi nobo tin wiye, kom yom fam bo co tan cike, kom niken niwo ki fam bo kwobbe.
25 “Wọ́n sì wí fún un pé, ‘Olúwa, ó ní owó mina mẹ́wàá.’
Ciki Teluwe, wii ki fam bo kwob.
26 “Mo wí fún yín pé, ‘Ẹnikẹ́ni tí ó ní, ni a ó fi fún, àti lọ́dọ̀ ẹni tí kò ní èyí tí ó ní pàápàá a ó gbà á lọ́wọ́ rẹ̀.
Miki niwo ki dikereri, cin yok cinen ten, niwo man cikeri an yom tangnin bo cine nen.
27 Ṣùgbọ́n àwọn ọ̀tá mi wọ̀nyí, tí kò fẹ́ kí èmi jẹ ọba lórí wọn ẹ mú wọn wá ìhín yìí, kí ẹ sì pa wọ́n níwájú mi!’”
Ki nobo biro koki yilare liya ciye kom bo ki ci fiyemi wii na twallangum ci fo kami.
28 Nígbà tí ó sì ti wí nǹkan wọ̀nyí tan, ó lọ síwájú, ó ń gòkè lọ sí Jerusalẹmu.
La kambo co to kan nyeri cui ken Urcelima.
29 Ó sì ṣe, nígbà tí ó súnmọ́ Betfage àti Betani ní òkè tí a ń pè ní òkè olifi, ó rán àwọn méjì nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.
Kambo cibo bidom kange Betafaji kange Betani dor bange ci coti ki zaitun, co tom nob bwangka coko nyo yob.
30 Wí pé, “Ẹ lọ sí ìletò tí ó kọjú sí yín; nígbà tí ẹ̀yin bá wọ̀ ọ́ lọ, ẹ̀yin ó rí ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan tí a so, tí ẹnikẹ́ni kò gùn rí, ẹ tú u, kí ẹ sì fà á wá.
Yi ciki, kom ya cuinukur do wureno ka kome. No com yari kanto be gelba kange tekum we kom kwiu. Kom bou men ciko.
31 Bí ẹnikẹ́ni bá sì bi yín pé, ‘Èéṣe tí ẹ̀yin fi ń tú u?’ Kí ẹ̀yin wí báyìí pé, ‘Olúwa ń fẹ́ lò ó.’”
No nii kange me kom ki, 'Ye bwiyi kom kwi tiyeri? kom yi co ki teruwe cuitiye.
32 Àwọn tí a rán sì mú ọ̀nà wọn pọ̀n, wọ́n sì bá a gẹ́gẹ́ bí ó ti wí fún wọn.
Nobo biro cu tom ciyeu yaci, fiya be gelba na wo Yeecu yiciyeu.
33 Bí wọ́n sì ti ń tú ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà, àwọn Olúwa rẹ̀ bi wọ́n pé, “Èéṣe tí ẹ̀yin fi ń tu kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà?”
Kambo ci kwi be gelba tiyeri, nob gelba me ciki, ye bwi ci kwi gelba tiye?
34 Wọ́n sì wí pé, “Olúwa fẹ́ lò ó.”
Ciki teluwe cuii tiye.
35 Wọ́n sì fà á tọ Jesu wá, wọ́n sì tẹ́ aṣọ sí ẹ̀yìn ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà, wọ́n sì gbé Jesu kà á.
Ci bo Yeecu nin ciko, cin miti kuleu ciye ro dor be gelba, co ci kun Yeecu ci yoti dorcere.
36 Bí ó sì ti ń lọ wọ́n tẹ́ aṣọ wọn sí ọ̀nà.
Kambo yaken tiyeri cimiten kulen ciyero ti dor nure
37 Bí ó sì ti súnmọ́ etí ibẹ̀ ní gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè olifi, gbogbo àwọn ọmọ-ẹ̀yìn bẹ̀rẹ̀ sí í yọ̀, wọ́n sì fi ohùn rara yin Ọlọ́run, nítorí iṣẹ́ ńlá gbogbo tí wọ́n ti rí,
Di con dedom yirakako kong zaitun, la nob tomange ceu cin ter bilantumbo ci wab kwamati ki diro dur wori nangeu nyo mamka ci to we.
38 wí pé, “Olùbùkún ni ọba tí ó ń bọ̀ wá ní orúkọ Olúwa!” “Àlàáfíà ní ọ̀run, àti ògo ni òkè ọ̀run!”
Bibwiyer lamiyo fiye liya wiyewo boti den Tere fuwor neret firen dii kwama kange yorkako wo na duk kakoce.
39 Àwọn kan nínú àwọn Farisi nínú àwùjọ náà sì wí fún un pé, “Olùkọ́ bá àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ wí.”
Kangum Fariciyawa mor nob mwe kanka nyico ki ni murangka kwanan nob bwingka mweko.
40 Ó sì dá wọn lóhùn, ó wí fún wọn pé, “Mo wí fún yín, bí àwọn wọ̀nyí bá pa ẹnu wọn mọ́, àwọn òkúta yóò kígbe sókè.”
Yeecu yilci miyikum bi rin keti bwenteno nobo biro kumom di terentiyo ki bwiyici ciya bi lange
41 Nígbà tí ó sì súnmọ́ etílé, ó síjú wo ìlú náà, ó sọkún sí i lórí,
Fiya Yeecu bou bidomri la ci lam bero cori la com ciwiyeu dor cer
42 Ó ń wí pé, “Ìbá ṣe pé ìwọ mọ̀, lónìí yìí, àní ìwọ, ohun tí í ṣe tí àlàáfíà rẹ! Ṣùgbọ́n nísinsin yìí wọ́n pamọ́ kúrò lójú rẹ.
tok ki, waki kom nyomom dike abou ti ki furnare di dila cumom nuwi kime mani ka to ti.
43 Nítorí ọjọ́ ń bọ̀ fún ọ, tí àwọn ọ̀tá rẹ yóò mọ odi bèbè yí ọ ká, àní tí wọn yóò sì yí ọ ká, wọn ó sì ká ọ mọ́ níhà gbogbo.
Dila diye boli mwinen, wo nob ki Yeecu mwe, ciyan mu ki yalange kentangum nen, ciyan kwenang mwenten culang ko gwam.
44 Wọn ó sì wó ọ palẹ̀ ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ pẹ̀lú rẹ; wọn kì yóò sì fi òkúta kan sílẹ̀ lórí ara wọn; nítorí ìwọ kò mọ ọjọ́ ìbẹ̀wò rẹ.”
Ciyan kun kom bitine wari kange bi beiyo lomwe. Mani ciya dob kange terti dor kecer wori mo kabo bati fiya kwama cwinco tiken nenen.
45 Ó sì wọ inú tẹmpili lọ, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí lé àwọn tí ń tà nínú rẹ̀ sóde;
Yeecu do bicor wabe co la tir yuwanob miyankake,
46 Ó sì wí fún wọn pé, “A ti kọ̀wé rẹ̀ pé, ‘Ilé mi yóò jẹ́ ilé àdúrà?’ Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ti sọ ọ́ di ihò àwọn ọlọ́ṣà.”
yi ci ti ki mulangum mulange lomi a yila lo diko, kom yilam bwak nob kwiyeb.
47 Ó sì ń kọ́ni lójoojúmọ́ ní tẹmpili, ṣùgbọ́n àwọn olórí àlùfáà, àti àwọn akọ̀wé, àti àwọn olórí àwọn ènìyàn ń wá ọ̀nà láti pa á.
Yeecu wi merang kang kang mor bikur waber. Dila dur wabero kange nob mulanka kange nobo dor noberoci cwiti na ci twallumco.
48 Wọn kò sì rí nǹkan kan tí wọn ìbá ṣe; nítorí gbogbo ènìyàn ṣù mọ́ ọn láti gbọ́rọ̀ rẹ̀.
Di la ci fiya bo nor maka, wori nobo cuwati ti cinen kambo ken.

< Luke 19 >