< Luke 18 >

1 Ó sì pa òwe kan fún wọn láti fi yé wọn pe, ó yẹ kí a máa gbàdúrà nígbà gbogbo, kí a má sì ṣàárẹ̀.
Ea fa: no bobogesu dunu da mae helele, mae da: i dione sia: ne gadoma: ne, Yesu da fedege sia: ilima olelei.
2 Wí pé, “Onídàájọ́ kan wà ní ìlú kan, tí kò bẹ̀rù Ọlọ́run, tí kò sì ṣe ojúsàájú ènìyàn.
E amane sia: i, “Moilai afae ganodini fofada: su dunu esalebe ba: i. E da Godema hame beda: i, amola eno dunuma hame asigisu.
3 Opó kan sì wà ní ìlú náà, ó sì ń tọ̀ ọ́ wá, wí pé, ‘Gbẹ̀san mi lára ọ̀tá mi!’
Amo moilai ganodini, didalo afae da mae yolele ema fofada: la misini, amane sia: nanu, ‘Na fidima: ne, nama ha lai dunuma fofada: ma!’
4 “Lákọ̀ọ́kọ́ kò dá a lóhùn, ṣùgbọ́n níkẹyìn ó wí nínú ara rẹ̀ pé, ‘Bí èmi kò tilẹ̀ bẹ̀rù Ọlọ́run, tí èmi kò sì ṣe ojúsàájú ènìyàn,
Fofada: su dunu da ea sia: hidadea hame nabi. Be fa: no, helebeba: le, e da ea dogo ganodini amane sia: i, ‘Na da Godema hame beda: i, amola eno dunuma hame asigisa.
5 Ṣùgbọ́n nítorí tí opó yìí ń yọ mí lẹ́nu, èmi ó gbẹ̀san rẹ̀, kí ó má ba à fi wíwá rẹ̀ nígbàkígbà dá mi lágara.’”
Be amo didalo da mae helele nama mabeba: le, na da se naba. Amaiba: le na da bagadewane helesa: besa: le, na da e fidima: ne, ema ha lai dunu ilima fofada: mu.’
6 Olúwa sì wí pé, “Ẹ gbọ́ bí aláìṣòótọ́ onídàájọ́ ti wí!
Amalalu, Yesu da bu amane sia: i, “Dilia da wadela: i fofada: su dunu ea sia: i nabimu da defea.
7 Ọlọ́run kì yóò ha sì gbẹ̀san àwọn àyànfẹ́ rẹ̀, tí ń fi ọ̀sán àti òru kígbe pè é, tí ó sì mú sùúrù fún wọn?
Dilia adi dawa: bela: ? Gode Ea ilegei fi dunu da Ema gasia amola yoga Ema digini wele sia: beba: le, E da ili fidima: ne fofada: ma: bela: ? E da ili fidima: ne, eso bagohame ouesaloma: bela: ?
8 Mo wí fún yín, yóò gbẹ̀san wọn kánkán! Ṣùgbọ́n nígbà tí Ọmọ Ènìyàn bá dé yóò ha rí ìgbàgbọ́ ní ayé bí?”
Hame mabu! E da hedolowane fidima: ne, fofada: musa: misunu. Be Dunu Egefe da bu misini, doaga: sea, e da osobo bagadega, Gode Ea hou dafawaneyale dawa: su hou ba: ma: bela?”
9 Ó sì pa òwe yìí fún àwọn kan tí wọ́n gbẹ́kẹ̀lé ara wọn pé, àwọn ni olódodo, tí wọ́n sì ń gan àwọn ẹlòmíràn,
Dunu ilila: hou ilisu ida: iwane dawa: i, amola eno dunu ilia hou da wadela: i ilia dawa: i, amo dunu da noga: le dawa: ma: ne, Yesu da fedege sia: olelei,
10 pé, “Àwọn ọkùnrin méjì gòkè lọ sí tẹmpili láti gbàdúrà, ọ̀kan jẹ́ Farisi, èkejì sì jẹ́ agbowó òde.
“Dunu aduna da sia: ne gadomusa: Debolo Diasuga golili sa: i. Afadafa da Fa: lisi dunu, eno da su lidisu dunu.
11 Èyí Farisi dìde, ó sì ń gbàdúrà nínú ara rẹ̀ báyìí pé, ‘Ọlọ́run mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ, nítorí tí èmi kò rí bí àwọn ará ìyókù, àwọn alọ́nilọ́wọ́gbà, aláìṣòótọ́, panṣágà, tàbí bí agbowó òde yìí.
Fa: lisi dunu e da wa: legadole, hina: hou olelema: ne amane sia: ne gadoi, ‘Gode! Na da eno dunu agoane hame. Amaiba: le, na Dima nodone sia: sa. Eno dunu huluane da wamolasu amola wadela: i hou hamosu amola inia uda adole lasu hamosa. Be na hame. Na da amo su lidisu dunu agoane hameba: le, na dima nodone sia: sa.
12 Èmi ń gbààwẹ̀ lẹ́ẹ̀méjì ní ọ̀sẹ̀, mo ń san ìdámẹ́wàá ohun gbogbo tí mo ní.’
Na da hi ganodini eso aduna ha: i hame naha. Na labe huluane nabuane mogili, afadafa Dima iaha.’
13 “Ṣùgbọ́n agbowó òde dúró lókèèrè, kò tilẹ̀ jẹ́ gbé ojú rẹ̀ sókè ọ̀run, ṣùgbọ́n ó lu ara rẹ̀ ní oókan àyà, ó wí pé, ‘Ọlọ́run ṣàánú fún mi, èmi ẹlẹ́ṣẹ̀!’
Be su lidisu dunu, e sedagawane lelu, gogosiabeba: le, ea si da hamedafa ba: le gadole, ea bida: gi hi loboga fane, amane sia: ne gadoi, ‘Gode! Na da wadela: i bagade dunu! Dia nama asigiba: le, na wadela: i hou gogolema: ne olofoma!’
14 “Mo wí fún yín, ọkùnrin yìí sọ̀kalẹ̀ lọ sí ilé rẹ̀ ní ìdáláre ju èkejì lọ: nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá gbé ara rẹ̀ ga, òun ni a ó rẹ̀ sílẹ̀; ẹni tí ó bá sì rẹ̀ ara rẹ̀ sílẹ̀ òun ni a ó gbéga.”
Na dilima sia: sa. Amo dunu da ea diasuga bu asili, ea wadela: i hou gogolema: ne olofoi dagoi ba: i. Be Fa: lisi dunu da agoane hame hamoi. Nowa dunu da hi hou gaguia gadoma: ne, gasa fi hou hamosea, Gode da amo dunu ea hou fonobomu. Be nowa dunu ea hou hi fonobosea, Gode da amo dunu ea hou bu bagade hahamomu.”
15 Wọ́n sì gbé àwọn ọmọ ọwọ́ tọ̀ ọ́ wá pẹ̀lú, kí ó lè gbé ọwọ́ lé wọn; ṣùgbọ́n nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ rí i, wọ́n ń bá wọn wí.
Dunu eno da mano dudubu Yesuma oule misi. Ilia da Yesu amo mano ilia dialuma da: iya Ea lobo ligisima: ne, oule misi. Amo hou ba: beba: le, Yesu Ea ado ba: su dunu da ilima ougili gagabole sia: i.
16 Ṣùgbọ́n Jesu pè wọ́n sọ́dọ̀ rẹ̀, ó sì wí pé, “Ẹ jẹ́ kí àwọn ọmọ kékeré wá sọ́dọ̀ mi, ẹ má sì ṣe dá wọn lẹ́kun, nítorí tí irú wọn ni ìjọba Ọlọ́run.
Be Yesu da amo mano misa: ne sia: nu, amane sia: i, “Mano ilia nama misunu logo mae hedofama. Gode Ea Hinadafa Hou da mano wewai ilia:
17 Lóòótọ́ ni mo wí fún yín, ẹnikẹ́ni tí kò bá gbà ìjọba Ọlọ́run bí ọmọ kékeré, kì yóò wọ inú rẹ̀ bí ó ti wù kí ó rí.”
Dawa: ma! Nowa dunu da mano ilia hou defelewane Gode Ea Hinadafa Hou hame lalegagusia, e da amo ganodini hamedafa masunu.”
18 Ìjòyè kan sì béèrè lọ́wọ́ rẹ̀, wí pé, “Olùkọ́ rere, kín ni èmi ó ṣe tí èmi ó fi jogún ìyè àìnípẹ̀kun?” (aiōnios g166)
Isala: ili ouligisu dunu afae da Yesuma amane adole ba: i, “Olelesu ida: iwane gala! Na da eso huluane mae bogole Fifi Ahoanusu lama: ne, adi hamoma: bela: ?” (aiōnios g166)
19 Jesu wí fún un pé, “Èéṣe tí ìwọ fi ń pè mí ní ẹni rere? Ẹni rere kan kò sí bí kò ṣe ẹnìkan, èyí sì ni Ọlọ́run.
Yesu E bu adole i, “Di da abuliba: le Nama ida: iwane dio asulila: ? Dunu huluanedafa da ida: iwane hame. Gode E fawane da ida: iwane gala.
20 Ìwọ mọ̀ àwọn òfin: ‘Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe panṣágà, ìwọ kò gbọdọ̀ pànìyàn, ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe jalè, ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe jẹ́rìí èké, bọ̀wọ̀ fún baba àti ìyá rẹ.’”
Gode Ea sema di dawa: ‘Inia uda mae adole lama. Mae medole legema. Mae wamolama. Mae ogogole sia: ma. Dia ada amola dia ame elama nodone asigima.”
21 Ó sì wí pé, “Gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni èmi ti pamọ́ láti ìgbà èwe mi wá.”
Amo dunu da Yesuma bu adole i, “Na da goihadini eso amogainini amo sema huluane mae giadofale hamoi dagoi.”
22 Nígbà tí Jesu sì gbọ́ èyí, ó wí fún un pé, “Ohun kan ni ó kù fún ọ síbẹ̀: lọ ta ohun gbogbo tí o ní, kí o sì pín in fún àwọn tálákà, ìwọ ó sì ní ìṣúra ní ọ̀run: sì wá, kí o máa tọ̀ mí lẹ́yìn.”
Amo sia: nababeba: le, Yesu da ema amane sia: i, “Afadafa fawane di da hamomu gala. Dia liligi huluane bidi lale, liligi hame gagui dunuma ima. Amasea, di da gobolo ida: iwane liligi Hebene ganodini ba: mu. Amasea, misini, Nama fa: no bobogema!”
23 Nígbà tí ó sì gbọ́ èyí, inú rẹ̀ bàjẹ́ gidigidi, nítorí tí ó ní ọrọ̀ púpọ̀.
Be amo sia: nababeba: le, amo dunu da ea liligi bagade gagui amo dawa: beba: le, da: i dioi nabi.
24 Nígbà tí Jesu rí i pé inú rẹ̀ bàjẹ́ gidigidi, ó wí pé, “Yóò ti ṣòro tó fún àwọn tí ó ní ọrọ̀ láti wọ ìjọba Ọlọ́run!
Ea da: i dioi ba: loba, Yesu da amane sia: i, “Bagade gagui dunu, ilia Gode Ea Hinadafa Hou amoga heda: su logo da ga: nasidafa.
25 Nítorí ó rọrùn fún ìbákasẹ láti gba ojú abẹ́rẹ́ wọlé jù fún ọlọ́rọ̀ láti wọ ìjọba Ọlọ́run lọ.”
Ga: mele da nusi ea gelaboga golili masunu da liligisimu. Be bagade gagui dunu ea Gode Ea Hinadafa Hou amo ganodini golili masunu logo da ga: mele ea nusi gelaboga golili ahoasu logo amo ea liligisisu bagadewane baligisa!”
26 Àwọn tí ó sì gbọ́ wí pé, “Ǹjẹ́ ta ni ó ha lè là?”
Amo sia: nabi dunu ilia amane sia: i. “Amaiba: le, nowa da Gode Ea gaga: su hou ba: ma: bela: ?”
27 Ó sì wí pé, “Ohun tí ó ṣòro lọ́dọ̀ ènìyàn kò ṣòro lọ́dọ̀ Ọlọ́run.”
Be Yesu da bu adole i, “Osobo bagade dunu ilia hamomu hamedei liligi, Gode da hamomusa: dawa: !”
28 Peteru sì wí pé, “Sá wò ó, àwa ti fi ilé wa sílẹ̀, a sì tọ̀ ọ́ lẹ́yìn!”
Amalalu, Bida e amane sia: i “Be Hina! Ninia da ninia diasu amola liligi fisili, Dima fa: no bobogei dagoi.”
29 Ó sì wí fún wọn pé, “Lóòótọ́ ni mo wí fún yín, kò sí ẹni tí ó fi ilé, tàbí aya, tàbí ará, tàbí òbí, tàbí ọmọ sílẹ̀, nítorí ìjọba Ọlọ́run,
Yesu E bu adole i, “Na da dilima dafawane sia: sa. Nowa dunu da Gode Ea Hinadafa Hou fidimusa: hanaiba: le, ea diasu amola uda, yolalali, eda, ame, amola mano huluane fisisia,
30 tí kì yóò gba ìlọ́po púpọ̀ sí i ní ayé yìí, àti ní ayé tí ń bọ̀ ìyè àìnípẹ̀kun.” (aiōn g165, aiōnios g166)
e da osobo bagadega esalea, amo liligi fisi baligiliwane bu lamu, amola fa: no fifi misunu amo esoga, e da mae bogole, Eso Huluane Fifi Ahoanusu lamu.” (aiōn g165, aiōnios g166)
31 Nígbà náà ni ó pe àwọn méjìlá sọ́dọ̀ rẹ̀, ó sì wí fún wọn pé, “Sá wò ó, àwa ń gòkè lọ sí Jerusalẹmu, a ó sì mú ohun gbogbo ṣẹ, tí a ti kọ láti ọwọ́ àwọn wòlíì, nítorí Ọmọ Ènìyàn.
Yesu da Ea ado ba: su dunu fagoyale gala amo la: ididili oule asili, ilima amane sia: i, “Nabima! Ninia Yelusaleme moilai bai bagadega masunu. Balofede dunu da musa: Dunu Egefe Ea hou olelemusa: sia dedei. Amo dedei hou huluane da doaga: i dagoi ba: mu.
32 Nítorí tí a ó fi lé àwọn aláìkọlà lọ́wọ́, a ó fi ṣe ẹlẹ́yà, a ó sì fi ṣe ẹ̀sín, a ó sì tutọ́ sí i lára.
Amasea, ilia da Dunu Egefe amo Dienadaile dunu (Gode Ea hou hame dawa: su dunu) ilima imunu. Ilia da Ema oufesega: ne, gadele, defo adugagala: mu.
33 Wọn ó sì nà án, wọn ó sì pa á, ní ọjọ́ kẹta yóò sì jíǹde.”
Ilia da Ea da: i fegasuga fane, medole legemu. Be E da bogole, eso udiana aligili wa: legadomu.”
34 Ọ̀kan nínú nǹkan wọ̀nyí kò sì yé wọn, ọ̀rọ̀ yìí sì pamọ́ fún wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò sì mọ ohun tí a wí.
Be amo sia: ea bai da wamolegeiba: le, ilia da noga: le hame dawa: i. Ilia da Yesu Ea sia: be bai hamedafa dawa: i.
35 Bí ó ti súnmọ́ Jeriko, afọ́jú kan jókòó lẹ́bàá ọ̀nà ó ń ṣagbe.
Yesu da Yeligou moilai gadenenewane laloba, si dofoi dunu da logo bega: fili, muni udigili edegelalebe ba: i.
36 Nígbà tí ó gbọ́ tí ọ̀pọ̀ ń kọjá lọ, ó béèrè pé, kín ni ìtumọ̀ èyí.
Amo dunu da Yesu amola dunu huluane ilia mabe nababeba: le, amane adole ba: i, “Amo da adi hamosala: ?”
37 Wọ́n sì wí fún un pé, “Jesu ti Nasareti ni ó ń kọjá lọ.”
Eno dunu ilia amane sia: i, “Yesu, Na: salede dunu, da baligili ahoanebe.”
38 Ó sì kígbe pé, “Jesu, ìwọ ọmọ Dafidi, ṣàánú fún mi!”
Amalalu, e ha: giwane wele sia: i, “Yesu! Da: ibidi Egefe! Nama asigima!”
39 Àwọn tí ń lọ níwájú bá a wí, pé, kí ó pa ẹnu rẹ̀ mọ́, ṣùgbọ́n òun sì kígbe sókè sí í pé, “Ìwọ Ọmọ Dafidi, ṣàánú fún mi!”
Be bisili ahoasu dunu da ema gagabole sia: i, “Ouiya: ma!” Be amo sia: nabasea, e da bu baligiliwane wele sia: i, “Da: ibidi Egefe! Nama asigima!”
40 Jesu sì dúró, ó ní, kí á mú un tọ òun wá nígbà tí ó sì súnmọ́ ọn, ó bi í
Amasea, Yesu da oulelu, eno dunu ilia da si dofoi dunu ema oule misa: ne sia: i. E da doaga: loba, Yesu da ema amane adole ba: i,
41 wí pé, “Kí ni ìwọ ń fẹ́ kí èmi ṣe fún ọ?” Ó sì wí pé, “Olúwa jẹ́ kí èmi ríran.”
“Na di fidima: ne, adi hamoma: bela: ?” Si dofoi dunu da bu adole i, “Hina! Na da bu ba: mu hanai gala!”
42 Jesu sì wí fún un pé, “Ríran; ìgbàgbọ́ rẹ mú ọ láradá.”
Yesu E amane sia: i, “Dia si fadegama! Di da dafawaneyale dawa: beba: le, uhi dagoi.”
43 Lójúkan náà ó sì ríran, ó sì ń tọ̀ ọ́ lẹ́yìn, ó sì ń yin Ọlọ́run lógo àti gbogbo ènìyàn nígbà tí wọ́n rí i, wọ́n fi ìyìn fún Ọlọ́run.
Amasea, mae aligili, ea si da fadegale, e Godema nodone sia: nanuwane Yesuma fa: no bobogei. Dunu huluane amo gasa bagade hou ba: beba: le, Godema nodosu.

< Luke 18 >