< Luke 18 >

1 Ó sì pa òwe kan fún wọn láti fi yé wọn pe, ó yẹ kí a máa gbàdúrà nígbà gbogbo, kí a má sì ṣàárẹ̀.
Nau haeanadetha hauthaunauhānee nuu heee, hena henane hāvachudajauaunevevetha, nau hājethauujesevenauau;
2 Wí pé, “Onídàájọ́ kan wà ní ìlú kan, tí kò bẹ̀rù Ọlọ́run, tí kò sì ṣe ojúsàájú ènìyàn.
Hahagu haeanedau hedan hauchuwunane, haeejesa Hejavaneauthu, daudause hathauwunanenau:
3 Opó kan sì wà ní ìlú náà, ó sì ń tọ̀ ọ́ wá, wí pé, ‘Gbẹ̀san mi lára ọ̀tá mi!’
Nau haeanedau henevesā hena hedan; nau haejeedasa, Jeaugaunayewhu naujauthavaa, hathauhuk.
4 “Lákọ̀ọ́kọ́ kò dá a lóhùn, ṣùgbọ́n níkẹyìn ó wí nínú ara rẹ̀ pé, ‘Bí èmi kò tilẹ̀ bẹ̀rù Ọlọ́run, tí èmi kò sì ṣe ojúsàájú ènìyàn,
Nau haejevadaunaasedau: hau waunee hasethajauhuk, hewauāthe nejechauau Hejavaneauthau, nau hathauwunanenau;
5 Ṣùgbọ́n nítorí tí opó yìí ń yọ mí lẹ́nu, èmi ó gbẹ̀san rẹ̀, kí ó má ba à fi wíwá rẹ̀ nígbàkígbà dá mi lágara.’”
Hau nausunee hanau naa henevesā hajanauchuhānau, hadenayauhauau havaedajauaunejau navanadauchuhaa.
6 Olúwa sì wí pé, “Ẹ gbọ́ bí aláìṣòótọ́ onídàájọ́ ti wí!
Nau Vahadāde hasenehehuk, Jaathehaa hasenehede janechuvāhede hauchuwunane.
7 Ọlọ́run kì yóò ha sì gbẹ̀san àwọn àyànfẹ́ rẹ̀, tí ń fi ọ̀sán àti òru kígbe pè é, tí ó sì mú sùúrù fún wọn?
Nau gauhujavaneauthau gauhadnenayauha nehayau hanayāsanaunau, hauwauaudaunādaunau hesee nau dajāee, hau negudauchuhaude?
8 Mo wí fún yín, yóò gbẹ̀san wọn kánkán! Ṣùgbọ́n nígbà tí Ọmọ Ènìyàn bá dé yóò ha rí ìgbàgbọ́ ní ayé bí?”
Nananenau nananena nāedauwunathana henee hadnauchuhanenayauhaude, Hau hāejauthe Heau henane, gauhadveede hethauwaudaude nuu hathāauauvaa.
9 Ó sì pa òwe yìí fún àwọn kan tí wọ́n gbẹ́kẹ̀lé ara wọn pé, àwọn ni olódodo, tí wọ́n sì ń gan àwọn ẹlòmíràn,
Nau haeauthaunanadetha jachau nethauwaudaunadenethe nehayau henee dauchuvahethee, nau newauchānauwauthee hauthauau:
10 pé, “Àwọn ọkùnrin méjì gòkè lọ sí tẹmpili láti gbàdúrà, ọ̀kan jẹ́ Farisi, èkejì sì jẹ́ agbowó òde.
Hanesethee henanenauau haeyehaunauau vevethahenauauwuu hadvevethahethee; hanesāde Nesethajuhu, nau jasaa hauāyāhe.
11 Èyí Farisi dìde, ó sì ń gbàdúrà nínú ara rẹ̀ báyìí pé, ‘Ọlọ́run mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ, nítorí tí èmi kò rí bí àwọn ará ìyókù, àwọn alọ́nilọ́wọ́gbà, aláìṣòótọ́, panṣágà, tàbí bí agbowó òde yìí.
Nesethajuhu haetheaugu nau haevevetha waude heee nehayau, Hejavaneauthau, nananenau vaveenethedaunathane, henee nāhauwunaathā hauthauau henanenauau hathahethee, hedanauwuyāhehauau, janechuvahethee, jatheaudauwuyāhehauau, daudause naa hathāde hauāyāhe.
12 Èmi ń gbààwẹ̀ lẹ́ẹ̀méjì ní ọ̀sẹ̀, mo ń san ìdámẹ́wàá ohun gbogbo tí mo ní.’
Nananenau nenaugauyānau nese hanesadee hauchauvadede, Nevānau vadadauchu vahee henee nāthāenetheyaunau.
13 “Ṣùgbọ́n agbowó òde dúró lókèèrè, kò tilẹ̀ jẹ́ gbé ojú rẹ̀ sókè ọ̀run, ṣùgbọ́n ó lu ara rẹ̀ ní oókan àyà, ó wí pé, ‘Ọlọ́run ṣàánú fún mi, èmi ẹlẹ́ṣẹ̀!’
Nau hauāyāhe haetheaugu vavāaune, daudause haejejenāauguau hejavaa, hau haeanadesejāhede, Hejavaneauthau jeauwunaune wauchudaunau, hathauhuk.
14 “Mo wí fún yín, ọkùnrin yìí sọ̀kalẹ̀ lọ sí ilé rẹ̀ ní ìdáláre ju èkejì lọ: nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá gbé ara rẹ̀ ga, òun ni a ó rẹ̀ sílẹ̀; ẹni tí ó bá sì rẹ̀ ara rẹ̀ sílẹ̀ òun ni a ó gbéga.”
Nananenau nāedauwunathana, naa henane haejaeyehau hedauauwuu haeauwunaunau haejavaāhe jachau: hanau dathājee hanesāde henee nevadaujavaānajanethee nehayau hadnauwujenanade; nau henee nenehanethaunadede hadnejanade.
15 Wọ́n sì gbé àwọn ọmọ ọwọ́ tọ̀ ọ́ wá pẹ̀lú, kí ó lè gbé ọwọ́ lé wọn; ṣùgbọ́n nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ rí i, wọ́n ń bá wọn wí.
Nau haejādaunanauau jea hajasedāeyaunauau, hadnevasanaude; hau hāenauhaudauwunethe hethauguhādaunau, haeneneuvanauau.
16 Ṣùgbọ́n Jesu pè wọ́n sọ́dọ̀ rẹ̀, ó sì wí pé, “Ẹ jẹ́ kí àwọn ọmọ kékeré wá sọ́dọ̀ mi, ẹ má sì ṣe dá wọn lẹ́kun, nítorí tí irú wọn ni ìjọba Ọlọ́run.
Hau Hejavaneauthusau haeadetha, nau hahagu, Nanehajauthee hajasedāeyaunauauau, nau jevadauduvaa: naathāhenethe henehanahedaunau henajanede Hejavaneauthau.
17 Lóòótọ́ ni mo wí fún yín, ẹnikẹ́ni tí kò bá gbà ìjọba Ọlọ́run bí ọmọ kékeré, kì yóò wọ inú rẹ̀ bí ó ti wù kí ó rí.”
Hethauwuu nāedauwunathana, Daun hadjesedanauau henajanedaunene Hejavaneauthu hasenaedenethe hajasedāeyaunauau hadnehauwuneejedā.
18 Ìjòyè kan sì béèrè lọ́wọ́ rẹ̀, wí pé, “Olùkọ́ rere, kín ni èmi ó ṣe tí èmi ó fi jogún ìyè àìnípẹ̀kun?” (aiōnios g166)
Nau jachau hauchuwunanene haenaudedaunaa, Hethāhene Hechauhauthethāhe, nauddusedau hadnedanauwau jethauujenenaedede? hathauhuk. (aiōnios g166)
19 Jesu wí fún un pé, “Èéṣe tí ìwọ fi ń pè mí ní ẹni rere? Ẹni rere kan kò sí bí kò ṣe ẹnìkan, èyí sì ni Ọlọ́run.
Nau Hejavaneauthsaun haeāedauwunaa, Naudu hethāde haesene? henaneda hehauwuthā, vavade hanesāde, nananede, Hejavaneauthau.
20 Ìwọ mọ̀ àwọn òfin: ‘Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe panṣágà, ìwọ kò gbọdọ̀ pànìyàn, ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe jalè, ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe jẹ́rìí èké, bọ̀wọ̀ fún baba àti ìyá rẹ.’”
Nananene haenauwu nanavaavedaunau, Jevawauchudauau heee haugauthenenede, Jevanaa, Jevaaveda, Jevajayaudauwāedauwauthadee, Vechauchune nananene hāsaunau nau hānau.
21 Ó sì wí pé, “Gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni èmi ti pamọ́ láti ìgbà èwe mi wá.”
Nau hanaāenehede, Vahee nuu haunaunedenau heee daujeeseaunau.
22 Nígbà tí Jesu sì gbọ́ èyí, ó wí fún un pé, “Ohun kan ni ó kù fún ọ síbẹ̀: lọ ta ohun gbogbo tí o ní, kí o sì pín in fún àwọn tálákà, ìwọ ó sì ní ìṣúra ní ọ̀run: sì wá, kí o máa tọ̀ mí lẹ́yìn.”
Wauhā Hejavaneauthusau hāenedauwaudauau nuu, Hanaāāedauwunaude, Hanesadee hāhauwusenethene: Vaheaudauna henee hāthāenetheyaunau, nau hadjaanauwunaunauau hadavenuhuhauau, nau nananene hadnethenauwu haenathau hejavaa, nau hadejau hadjethaugu.
23 Nígbà tí ó sì gbọ́ èyí, inú rẹ̀ bàjẹ́ gidigidi, nítorí tí ó ní ọrọ̀ púpọ̀.
Nau hāenedauwaudauau nuu, haeaudauwuthajau: hanau deethauwunethauyā dāde.
24 Nígbà tí Jesu rí i pé inú rẹ̀ bàjẹ́ gidigidi, ó wí pé, “Yóò ti ṣòro tó fún àwọn tí ó ní ọrọ̀ láti wọ ìjọba Ọlọ́run!
Nau Hejavaneauthausaun hāenauhaudauwunith henee dauaudauwuthajaude, Duthāenanauthaune henee nanethenuu veaunauaude hadnesejedāthee henajanedaunene Hejavaneauthu, hathauhuk.
25 Nítorí ó rọrùn fún ìbákasẹ láti gba ojú abẹ́rẹ́ wọlé jù fún ọlọ́rọ̀ láti wọ ìjọba Ọlọ́run lọ.”
Hanau hehauwujajathaune heee camel hehedesahagaunee hajasevāhau nedaudaunaudenee, javaāneenauthaunee nethauyāsenane hadnesejedāde henajanedaunene Hejavaneauthu.
26 Àwọn tí ó sì gbọ́ wí pé, “Ǹjẹ́ ta ni ó ha lè là?”
Nau hathāenedauwauduu, Hanaa hadnenanedanede? hahagaunee.
27 Ó sì wí pé, “Ohun tí ó ṣòro lọ́dọ̀ ènìyàn kò ṣòro lọ́dọ̀ Ọlọ́run.”
Nau hanaāenehenith, hayauhuhau hejethauuneethaunenau henanenauau neneedede Hejavaneauthau.
28 Peteru sì wí pé, “Sá wò ó, àwa ti fi ilé wa sílẹ̀, a sì tọ̀ ọ́ lẹ́yìn!”
Hanaāenehede Peda, Naune, naunaudauwunauau vahee, nau thaunauguhane.
29 Ó sì wí fún wọn pé, “Lóòótọ́ ni mo wí fún yín, kò sí ẹni tí ó fi ilé, tàbí aya, tàbí ará, tàbí òbí, tàbí ọmọ sílẹ̀, nítorí ìjọba Ọlọ́run,
Nau haeāedauwuna, Hethauwuu nāedauwunathana, hena haunauude henane henee hehauwunaude hedauauwuu, wauāthe henehā, wauāthe henauhauwauau, wauāthe henene wauāthe henesaunau, heee henajanedaunene Hejavaneauthu hedenaededaunene,
30 tí kì yóò gba ìlọ́po púpọ̀ sí i ní ayé yìí, àti ní ayé tí ń bọ̀ ìyè àìnípẹ̀kun.” (aiōn g165, aiōnios g166)
Nananede hadjavaānesedanauau nuu hewaunehaa, nau hathāauauvaa hadnauusanauau henaedede hadnejethauuvadauauau. (aiōn g165, aiōnios g166)
31 Nígbà náà ni ó pe àwọn méjìlá sọ́dọ̀ rẹ̀, ó sì wí fún wọn pé, “Sá wò ó, àwa ń gòkè lọ sí Jerusalẹmu, a ó sì mú ohun gbogbo ṣẹ, tí a ti kọ láti ọwọ́ àwọn wòlíì, nítorí Ọmọ Ènìyàn.
Hanaāedanaude nesenee, nau hanaāāedauwunaude, Naune, hadneyehaunauau Dādaunedan, nau vahee hayauhuhau hathāewauthaunauhuu haeyāhehauau heee Heau henane hethauwunauauchauau.
32 Nítorí tí a ó fi lé àwọn aláìkọlà lọ́wọ́, a ó fi ṣe ẹlẹ́yà, a ó sì fi ṣe ẹ̀sín, a ó sì tutọ́ sí i lára.
Hanau hadvenavathe Neauthu, nau hadvavavanauchuhāde, nau hadnaunaunauchaudauchuhāde, nau hadneguthahayauthāde.
33 Wọn ó sì nà án, wọn ó sì pa á, ní ọjọ́ kẹta yóò sì jíǹde.”
Nau hadnenesegauhude, nau hadnaāde: nau nasese hadnaāejaegauhāde.
34 Ọ̀kan nínú nǹkan wọ̀nyí kò sì yé wọn, ọ̀rọ̀ yìí sì pamọ́ fún wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò sì mọ ohun tí a wí.
Nau haejaenauwu nuu: nau nuu hauthedau haeyaudaunaunauau, daudause haejaenauwu hathauthedaunāthee.
35 Bí ó ti súnmọ́ Jeriko, afọ́jú kan jókòó lẹ́bàá ọ̀nà ó ń ṣagbe.
Nau hethauwuu, hāayāedadauau Jericho, jasaa haenanenaugu henane haetheaugu nedechaudenenee dauhunedauwaude:
36 Nígbà tí ó gbọ́ tí ọ̀pọ̀ ń kọjá lọ, ó béèrè pé, kín ni ìtumọ̀ èyí.
Nau haenedauwaude henanedanede dadavechaudenenee, haenaudedauva haesedaudenenee.
37 Wọ́n sì wí fún un pé, “Jesu ti Nasareti ni ó ń kọjá lọ.”
Nau haeaāedauwunau, henee Jesus Nazareth hanehedesade.
38 Ó sì kígbe pé, “Jesu, ìwọ ọmọ Dafidi, ṣàánú fún mi!”
Nau hanaāevasanadede, Hejavaneauthusau, nananene Heau David, jeauwunaune, hathauhuk.
39 Àwọn tí ń lọ níwájú bá a wí, pé, kí ó pa ẹnu rẹ̀ mọ́, ṣùgbọ́n òun sì kígbe sókè sí í pé, “Ìwọ Ọmọ Dafidi, ṣàánú fún mi!”
Nau henee nanedauvathee haeneneuvanauau haddādaunaugunith: hau haevasanade haugauthe, Nananene Heau David, jeauwunaune.
40 Jesu sì dúró, ó ní, kí á mú un tọ òun wá nígbà tí ó sì súnmọ́ ọn, ó bi í
Nau Hejavaneauthusau haedauusa, nau haeautheave hadjādaunade: nau hāayājenauusanith, haenaudedauna,
41 wí pé, “Kí ni ìwọ ń fẹ́ kí èmi ṣe fún ọ?” Ó sì wí pé, “Olúwa jẹ́ kí èmi ríran.”
Hauddusehathe henee hadenaasehathane? hathauhuk. Nau hanaāāedauwunaude, Vahadāhene, nanaa hadeesedanauwau nauhaudauwaude.
42 Jesu sì wí fún un pé, “Ríran; ìgbàgbọ́ rẹ mú ọ láradá.”
Nau Hejavaneauthusau haenehetha, hanesedanauwu nananene nauhaudauwaude: hadethauwaudaude henayauhāne.
43 Lójúkan náà ó sì ríran, ó sì ń tọ̀ ọ́ lẹ́yìn, ó sì ń yin Ọlọ́run lógo àti gbogbo ènìyàn nígbà tí wọ́n rí i, wọ́n fi ìyìn fún Ọlọ́run.
Nau chauchaunu haeesedane henauhaudauwaude, nau haethauguha, haevaveenethedauna Hejavaneauthu: nau vahee henanedanede, hāenauhauduu, haevaveenethedaunanauau Hejavaneauthu.

< Luke 18 >