< Luke 17 >

1 Ó sì wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Kò le ṣe kí ohun ìkọ̀sẹ̀ máa wa, ṣùgbọ́n ègbé ni fún ẹni tí ó ti ipasẹ̀ rẹ̀ dé.
ⲁ̅ⲡⲉϫⲁϥ ⲇⲉ ⳿ⲛⲛⲉϥⲙⲁⲑⲏⲧⲏⲥ ϫⲉ ϩⲱϯ ⳿ⲛⲧⲟⲩ⳿ⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲓ⳿ⲥⲕⲁⲛⲇⲁⲗⲟⲛ ⳿ⲡⲗⲏⲛ ⲟⲩⲟⲓ ⳿ⲙⲫⲏⲉⲧⲉ ⲡⲓ⳿ⲥⲕⲁⲛⲇⲁⲗⲟⲛ ⲛⲏⲟⲩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϩⲓⲧⲟⲧϥ.
2 Ìbá sàn fún un kí a so ọlọ mọ́ ọn ní ọrùn, kí a sì gbé e jù sínú Òkun, ju kí ó mú ọ̀kan nínú àwọn kékeré wọ̀nyí kọsẹ̀.
ⲃ̅ⲛⲁⲛⲉⲥ ⲛⲁϥ ⳿ⲛⲧⲟⲩⲉϣ ⲟⲩⲱⲛⲓ ⳿ⲙⲙⲟⲩⲗⲟⲛ ⳿ⲉϧⲏⲧϥ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲧⲟⲩϩⲓⲧϥ ⳿ⲉ⳿ϧⲣⲏⲓ ⳿ⲉ⳿ⲫⲓⲟⲙ ⳿ⲉϩⲟⲧⲉ ⳿ⲛⲧⲉϥⲉⲣ⳿ⲥⲕⲁⲛⲇⲁⲗⲓⲍⲉⲥⲑⲉ ⳿ⲛⲟⲩⲁⲓ ⳿ⲛⲛⲁⲓⲕⲟⲩϫⲓ.
3 Ẹ máa kíyèsára yín. “Bí arákùnrin rẹ bá ṣẹ̀, bá a wí; bí ó bá sì ronúpìwàdà, dáríjì ín.
ⲅ̅ⲙⲁϩⲑⲏⲧⲉⲛ ⳿ⲉⲣⲱⲧⲉⲛ ⲁⲣⲉϣⲁⲛ ⲉⲕⲥⲟⲛ ⲉⲣⲛⲟⲃⲓ ⲁⲣⲓ⳿ⲉⲡⲓⲧⲓⲙⲁⲛ ⲛⲁϥ ⲟⲩⲟϩ ⲉϣⲱⲡ ⲁϥϣⲁⲛⲉⲣⲙⲉⲧⲁⲛⲟⲓⲛ ⲭⲱ ⲛⲁϥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ.
4 Bí ó bá sì ṣẹ̀ ọ́ ní igba méje ní òòjọ́, tí ó padà tọ̀ ọ́ wá ní ìgbà méje ní òòjọ́ pé, ‘Mo ronúpìwàdà,’ dáríjì ín.”
ⲇ̅ⲉϣⲱⲡ ⲇⲉ ⲁϥϣⲁⲛⲉⲣⲛⲟⲃⲓ ⳿ⲉⲣⲟⲕ ⳿ⲛⲍ̅ ⳿ⲛⲥⲟⲡ ⲉⲛ ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⳿ⲛⲧⲉϥⲕⲟⲧϥ ⳿ⲉⲣⲟⲕ ⳿ⲛⲍ̅ ⳿ⲛⲥⲟⲡ ⲉϥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ϯⲉⲣⲙⲉⲧⲁⲛⲟⲓⲛ ⲭⲱ ⲛⲁϥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ.
5 Àwọn aposteli sì wí fún Olúwa pé, “Bù sí ìgbàgbọ́ wa.”
ⲉ̅ⲟⲩⲟϩ ⲡⲉϫⲉ ⲛⲓⲁⲡⲟⲥⲧⲟⲗⲟⲥ ⳿ⲙⲠ⳪ ϫⲉ ⲟⲩⲁϩⲛⲁϩϯ ⳿ⲉⲣⲟⲛ.
6 Olúwa sì wí pé, “Bí ẹ̀yin bá ní ìgbàgbọ́ bí hóró irúgbìn musitadi, ẹ̀yin yóò lè wí fún igi sikamine yìí pé, ‘Di fi fà á tu, kí a sì gbìn ọ́ sínú Òkun,’ yóò sì gbọ́ tiyín.
ⲋ̅ⲡⲉϫⲉ Ⲡ⳪ ⲇⲉ ϫⲉ ⲉⲛⲉ ⲟⲩⲟⲛⲧⲉⲧⲉⲛ ⲛⲁϩϯ ⳿ⲙⲙⲁⲩ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲛⲟⲩⲛⲁⲫⲣⲓ ⳿ⲛϣⲉⲗⲧⲁⲙ ⲛⲁⲣⲉⲧⲉⲛⲛⲁϫⲟⲥ ⳿ⲛϯⲛⲟⲩϩⲓ ϫⲉ ϥⲱϫⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲣⲱⲧ ϧⲉⲛ ⳿ⲫⲓⲟⲙ ⲟⲩⲟϩ ⲛⲁⲥⲛⲁⲥⲱⲧⲉⲙ ⳿ⲛⲥⲁ ⲑⲏⲛⲟⲩ ⲡⲉ.
7 “Ṣùgbọ́n ta ni nínú yín, tí ó ní ọmọ ọ̀dọ̀, tí ó ń tulẹ̀, tàbí tí ó ń bọ́ ẹran, tí yóò wí fún un lójúkan náà tí ó bá ti oko dé pé, ‘Lọ í jókòó láti jẹun’?
ⲍ̅ⲛⲓⲙ ⲇⲉ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲑⲏⲛⲟⲩ ⲉⲧⲉ ⲟⲩⲟⲛⲧⲉϥ ⲟⲩⲃⲱⲕ ⳿ⲙⲙⲁⲩ ⲉϥ⳿ⲥⲭⲁⲓ ⲓⲉ ⲉϥⲙⲟⲛⲓ ⲫⲏⲉⲧⲉ ⲁϥϣⲁⲛ⳿ⲓ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲕⲟⲓ ⲙⲏ ⳿ϥⲛⲁϫⲟⲥ ⲛⲁϥ ⲥⲁⲧⲟⲧϥ ϫⲉ ⲁⲙⲟⲩ ⳿ⲉ⳿ⲡϣⲱⲓ ⲣⲱⲧⲉⲃ.
8 Tí kì yóò kúkú wí fún un pé, ‘Pèsè ohun tí èmi yóò jẹ, sì di àmùrè, kí ìwọ kí ó máa ṣe ìránṣẹ́ fún mi, títí èmi ó fi jẹ kí èmi ó sì mu tán; lẹ́yìn náà ni ìwọ ó sì jẹ, tí ìwọ ó sì mu’?
ⲏ̅ⲙⲏ ⳿ϥⲛⲁϫⲟⲥ ⲛⲁϥ ⲁⲛ ϫⲉ ⲥⲟⲃϯ ⳿ⲙⲫⲏ ⳿ⲉϯⲛⲁⲟⲩⲟⲙϥ ⲟⲩⲟϩ ⲙⲟⲣⲕ ϣⲉⲙϣⲓ ⳿ⲙⲙⲟⲓ ϣⲁϯⲟⲩⲱⲙ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲧⲁⲥⲱ ⲟⲩⲟϩ ⲙⲉⲛⲉⲛⲥⲁ ⲁⲓ ϩⲱⲕ ⳿ⲛⲧⲉⲕⲟⲩⲱⲙ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲧⲉⲕⲥⲱ.
9 Òun ó ha máa dá ọpẹ́ lọ́wọ́ ọmọ ọ̀dọ̀ náà, nítorí ó ṣe ohun tí a pàṣẹ fún un bí? Èmi kò rò bẹ́ẹ̀.
ⲑ̅ⲙⲏ ⲟⲩⲟⲛ ⳿ϩⲙⲟⲧ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲓⲃⲱⲕ ϫⲉ ⲁϥ⳿ⲓⲣⲓ ⳿ⲛⲛⲏⲉⲧⲁϥⲟⲩⲁϩⲥⲁϩⲛⲓ ⳿ⲙⲙⲱⲟⲩ ⲛⲁϥ.
10 Gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin pẹ̀lú, nígbà tí ẹ bá ti ṣe ohun gbogbo tí a pàṣẹ fún yín tán, ẹ wí pé, ‘Aláìlérè ọmọ ọ̀dọ̀ ni wá: èyí tí í ṣe iṣẹ́ wa láti ṣe, ní àwa ti ṣe.’”
ⲓ̅ⲁⲓⲣⲏϯ ⳿ⲛⲑⲱⲧⲉⲛ ϩⲱⲧⲉⲛ ⲁⲣⲉⲧⲉⲛϣⲁⲛ⳿ⲓⲣⲓ ⳿ⲛϩⲱⲃ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲉⲧⲁⲩⲟⲩⲁϩⲥⲁϩⲛⲓ ⳿ⲙⲙⲱⲟⲩ ⲛⲱⲧⲉⲛ ⳿ⲁϫⲟⲥ ϫⲉ ⳿ⲁⲛⲟⲛ ϩⲁⲛⲃⲱⲕ ⳿ⲛⲁⲧϣⲁⲩ ⲡⲉⲧⲉⲣⲟⲛ ⲉⲁⲓϥ ⲁⲛⲁⲓϥ.
11 Ó sì ṣe, bí ó ti ń lọ sí Jerusalẹmu, ó kọjá láàrín Samaria Galili.
ⲓ̅ⲁ̅ⲁⲥϣⲱⲡⲓ ⲉϥϣⲉ ⲛⲁϥ ⳿ⲉ⳿ϩⲣⲏⲓ ⳿ⲉ⳿ⲓⲗ̅ⲏ̅ⲙ̅ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲑⲟϥ ⲛⲁϥⲥⲓⲛⲓⲱⲟⲩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲟⲩⲧⲉ ⳿ⲑⲙⲏϯ ⳿ⲛ⳿ⲧⲁⲥⲁⲙⲁⲣⲓ⳿ⲁ ⲛⲉⲙ ϯⲅⲁⲗⲓⲗⲉ⳿ⲁ.
12 Bí ó sì ti ń wọ inú ìletò kan lọ, àwọn ọkùnrin adẹ́tẹ̀ mẹ́wàá pàdé rẹ̀, wọ́n dúró ní òkèrè,
ⲓ̅ⲃ̅ⲟⲩⲟϩ ⲉϥⲛⲁϣⲉ ⲛⲁϥ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉⲟⲩϯⲙⲓ ⲁⲩ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲉ⳿ϩⲣⲁϥ ⳿ⲛϫⲉ ⲓ̅ ⳿ⲛⲣⲱⲙⲓ ⳿ⲛⲕⲁⲕⲥⲉϩⲧ ⲟⲩⲟϩ ⲛⲁⲩⲟϩⲓ ⳿ⲉⲣⲁⲧⲟⲩ ϩⲓⲫⲟⲩⲉⲓ.
13 wọ́n sì kígbe sókè wí pé, “Jesu, Olùkọ́, ṣàánú fún wa.”
ⲓ̅ⲅ̅ⲩⲟϩ ⳿ⲛⲑⲱⲟⲩ ⲛⲁⲩϭⲓⲥⲓ ⳿ⲛⲧⲟⲩ⳿ⲥⲙⲏ ⲉⲩϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ Ⲓⲏ̅ⲥ̅ ⲡⲓⲣⲉϥϯ⳿ⲥⲃⲱ ⲛⲁⲓ ⲛⲁⲛ.
14 Nígbà tí ó rí wọn, ó wí fún wọn pé, “Ẹ lọ í fi ara yín hàn fún àwọn àlùfáà.” Ó sì ṣe, bí wọ́n ti ń lọ, wọ́n sì di mímọ́.
ⲓ̅ⲇ̅ⲟⲩⲟϩ ⲉⲧⲁϥⲛⲁⲩ ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲱⲟⲩ ϫⲉ ⲙⲁϣⲉ ⲛⲱⲧⲉⲛ ⲁⲧⲁⲙⲉ ⲡⲓⲟⲩⲏⲃ ⳿ⲉⲣⲱⲧⲉⲛ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲥϣⲱⲡⲓ ⲉⲩϣⲉ ⲛⲱⲟⲩ ⲁⲩⲧⲟⲩⲃⲟ.
15 Nígbà tí ọ̀kan nínú wọn rí i pé a mú òun láradá ó padà, ó sì fi ohùn rara yin Ọlọ́run lógo.
ⲓ̅ⲉ̅ⲟⲩⲁⲓ ⲇⲉ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲛϧⲏⲧⲟⲩ ⲉⲧⲁϥⲛⲁⲩ ϫⲉ ⲁϥⲗⲟϫϥ ⲁϥⲧⲁⲥⲑⲟ ⲉⲙ ⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲛ⳿ⲥⲙⲏ ⲉϥϯⲱⲟⲩ ⳿ⲙⲫϯ.
16 Ó sì wólẹ̀ lẹ́bàá ẹsẹ̀ rẹ̀, ó ń dúpẹ́ ní ọwọ́ rẹ̀: ará Samaria ni òun í ṣe.
ⲓ̅ⲋ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁϥϩⲓⲧϥ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⲡⲉϥϩⲟ ϧⲁⲧⲉⲛ ⲛⲉϥϭⲁⲗⲁⲩϫ ⲉϥϣⲉⲡ⳿ϩⲙⲟⲧ ⳿ⲛⲧⲟⲧϥ ⲟⲩⲟϩ ⲫⲁⲓ ⲛⲉ ⲩⲥⲁⲙⲁⲣⲓⲧⲏⲥ ⲡⲉ.
17 Jesu sì dáhùn wí pé, “Àwọn mẹ́wàá kí a sọ di mímọ́? Àwọn mẹ́sàn-án ìyókù ha dà?
ⲓ̅ⲍ̅ⲁϥⲉⲣⲟⲩⲱ ⲇⲉ ⳿ⲛϫⲉ Ⲓⲏ̅ⲥ̅ ⲡⲉϫⲁϥ ϫⲉ ⲙⲏ ⳿ⲙⲡⲉ ⲡⲓⲓ̅ ⲧⲟⲩⲃⲟ ⲡⲓⲕⲉⲑ̅ ⲁⲩⲑⲱⲛ.
18 A kò rí ẹnìkan tí ó padà wá fi ògo fún Ọlọ́run, bí kò ṣe àlejò yìí?”
ⲓ̅ⲏ̅ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲙⲡⲟⲩϫⲉⲙⲟⲩ ⲉⲁⲩⲕⲟⲧⲟⲩ ⳿ⲉϯ ⲱⲟⲩ ⳿ⲙⲫϯ ⳿ⲉⲃⲏⲗ ⳿ⲉⲫⲁⲓ ⲁⲗⲗⲟⲅⲉⲛⲏⲥ.
19 Ó sì wí fún un pé, “Dìde, kí o sì máa lọ, ìgbàgbọ́ rẹ mú ọ láradá.”
ⲓ̅ⲑ̅ⲟⲩⲟϩ ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲁϥ ϫⲉ ⲧⲱⲛⲕ ⲙⲁϣⲉ ⲛⲁⲕ ⲡⲉⲕⲛⲁϩϯ ⲡⲉⲧⲁϥⲛⲁϩⲙⲉⲕ.
20 Nígbà tí àwọn Farisi bi í pé, nígbà wo ni ìjọba Ọlọ́run yóò dé, ó dá wọn lóhùn pé, “Ìjọba Ọlọ́run kì í wá pẹ̀lú àmì.
ⲕ̅ⲉⲧⲁⲩϣⲉⲛϥ ⲇⲉ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲓⲫⲁⲣⲓⲥⲉⲟⲥ ϫⲉ ⲁⲥⲛⲁ⳿ⲓ ⳿ⲛ⳿ⲑⲛⲁⲩ ⳿ⲛϫⲉ ϯⲙⲉⲧⲟⲩⲣⲟ ⳿ⲛⲧⲉ ⲫϯ ⲁϥⲉⲣⲟⲩⲱ ⲛⲱⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲡⲉϫⲁϥ ϫⲉ ⲛⲁⲣⲉ ϯ ⲙⲉⲧⲟⲩⲣⲟ ⳿ⲛⲧⲉ ⲫϯ ⲛⲁ⳿ⲓ ⲁⲛ ϧⲉⲛ ⲟⲩⲙⲉⲧⲣⲉϥϯ ⳿ϩⲑⲏϥ.
21 Bẹ́ẹ̀ ni wọn kì yóò wí pé, ‘Kíyèsi i níhìn-ín!’ tàbí ‘Kíyèsi i lọ́hùn ún ni!’ sá à wò ó, ìjọba Ọlọ́run ń bẹ nínú yín.”
ⲕ̅ⲁ̅ⲟⲩⲇⲉ ⲥⲉⲛⲁϫⲟⲥ ⲁⲛ ϫⲉ ⳿ⲥⲧⲁⲓ ⲓⲉ ⳿ⲥⲧⲏ ϩⲏⲡⲡⲉ ⲅⲁⲣ ⲓⲥ ϯⲙⲉⲧⲟⲩⲣⲟ ⳿ⲛⲧⲉ ⲫϯ ⲥⲁϧⲟⲩⲛ ⳿ⲙⲙⲱⲧⲉⲛ.
22 Ó sì wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Ọjọ́ ń bọ̀, nígbà tí ẹ̀yin yóò fẹ́ láti rí ọ̀kan nínú ọjọ́ Ọmọ Ènìyàn, ẹ̀yin kì yóò sì rí i.
ⲕ̅ⲃ̅ⲡⲉϫⲁϥ ⲇⲉ ⳿ⲛⲛⲉϥⲙⲁⲑⲏⲧⲏⲥ ϫⲉ ⲥⲉⲛⲏ ⲟⲩ ⳿ⲛϫⲉ ϩⲁⲛ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ϩⲟⲧⲉ ⲉⲣⲉⲧⲉⲛⲛⲁⲉⲣⲉⲡⲓⲑⲩⲙⲓⲛ ⳿ⲉⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲟⲩⲁⲓ ⲛⲓ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⳿ⲛⲧⲉ ⳿ⲡϣⲏ ⲣⲓ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲱⲙⲓ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲛⲉⲧⲉⲛⲛⲁⲩ.
23 Wọ́n sì wí fún yín pé, ‘Wò ó níhìn-ín!’ tàbí ‘Wò ó lọ́hùn ún!’ Ẹ máa lọ, ẹ má ṣe tẹ̀lé wọn.
ⲕ̅ⲅ̅ⲟⲩⲟϩ ⲉⲩ⳿ⲉϫⲟⲥ ⲛⲱⲧⲉⲛ ϫⲉ ϩⲏⲡⲡⲉ ⳿ϥⲧⲏ ⲓⲉ ⳿ϥⲧⲁⲓ ⳿ⲙⲡⲉⲣϣⲉ ⲛⲱⲧⲉⲛ ⲟⲩⲇⲉ ⳿ⲙⲡⲉⲣϭⲟϫⲓ.
24 Nítorí gẹ́gẹ́ bí mọ̀nàmọ́ná ti í kọ ní apá kan lábẹ́ ọ̀run, tí sì í mọ́lẹ̀ ní apá kejì lábẹ́ ọ̀run, bẹ́ẹ̀ ni Ọmọ Ènìyàn yóò sì rí ní ọjọ́ rẹ̀.
ⲕ̅ⲇ̅⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲙⲡⲓⲥⲉⲧⲉⲃⲣⲏϫ ⳿ⲉϣⲁϥⲟⲩⲟⲛϩϥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲫⲉ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲧⲉϥⲉⲣⲟⲩⲱⲓⲛⲓ ⲥⲁⲡⲉⲥⲏⲧ ⳿ⲛ⳿ⲧⲫⲉ ⲫⲁⲓ ⲡⲉ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⲉⲧⲉ ⲡϣⲏ ⲣⲓ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲱⲙⲓ ⲛⲁϣⲱⲡⲓ ⳿ⲙⲙⲟϥ ⳿ⲛ⳿ϩⲣⲏⲓ ϧⲉⲛ ⲡⲉϥ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ.
25 Ṣùgbọ́n kò lè ṣàìmá kọ́ jìyà ohun púpọ̀, kí a sì kọ̀ ọ́ lọ́dọ̀ ìran yìí.
ⲕ̅ⲉ̅ϣⲟⲣⲡ ⲇⲉ ϩⲱϯ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⳿ⲛⲧⲉϥϭⲓ ⲟⲩⲙⲏϣ ⳿ⲛϧⲓⲥⲓ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲥⲉϣⲟϣϥ ⳿ⲛϫⲉ ⲁⲓⲅⲉⲛⲉ⳿ⲁ.
26 “Bí ó ti rí ní ọjọ́ Noa, bẹ́ẹ̀ ni yóò rí ní ọjọ́ Ọmọ Ènìyàn.
ⲕ̅ⲋ̅ⲟⲩⲟϩ ⲕⲁⲧⲁ⳿ⲫⲣⲏϯ ⲉⲧⲁⲥϣⲱⲡⲓ ϧⲉⲛ ⲛⲓ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⳿ⲛⲧⲉ ⲛⲱ⳿ⲉ ⲡⲁⲓⲣⲏϯ ⲡⲉⲑⲛⲁϣⲱⲡⲓ ϧⲉⲛ ⲛⲓ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⳿ⲛⲧⲉ ⳿ⲡϣⲏⲣⲓ ⳿ⲙⲫϯ.
27 Wọ́n ń jẹ, wọ́n ń mu, wọ́n ń gbéyàwó, wọ́n sì ń fa ìyàwó fún ni, títí ó fi di ọjọ́ ti Noa wọ inú ọkọ̀ lọ, kíkún omi sì dé, ó sì run gbogbo wọn.
ⲕ̅ⲍ̅ⲛⲁⲩⲟⲩⲱⲙ ⲟⲩⲟϩ ⲛⲁⲩⲥⲱ ⲛⲁⲩϭⲓ ⳿ⲥϩⲓⲙⲓ ⲛⲁⲩϭⲓ ϩⲁⲓ ϣⲁ ⲡⲓ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⲉⲧⲁ ⲛⲱ⳿ⲉ ϣⲉ ⲛⲁϥ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉϯⲕⲓⲃⲱⲧⲟⲥ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥ⳿ⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲡⲓⲕⲁⲧⲁ⳿ⲕⲗⲩⲥⲙⲟⲥ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥⲧⲁⲕⲉ ⲟⲩⲟⲛ ⲛⲓⲃⲉⲛ.
28 “Bí ó sì ti rí ní ọjọ́ Lọti; wọ́n ń jẹ, wọ́n ń mu, wọ́n ń rà, wọ́n ń tà, wọ́n ń gbìn, wọ́n ń kọ́lé,
ⲕ̅ⲏ̅⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⲟⲛ ⲉⲧⲁⲥϣⲱⲡⲓ ϧⲉⲛ ⲛⲓ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⳿ⲛⲧⲉ ⲗⲱⲧ ⲛⲁⲩⲟⲩⲱⲙ ⲛⲁⲩⲥⲱ ⲛⲁⲩϣⲱⲡ ⲁⲩϯ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲛⲁⲩϭⲟ ⲛⲁⲩⲕⲱⲧ.
29 ṣùgbọ́n ní ọjọ́ náà tí Lọti jáde kúrò ní Sodomu, òjò iná àti sulfuru rọ̀ láti ọ̀run wá, ó sì run gbogbo wọn.
ⲕ̅ⲑ̅ϧⲉⲛ ⲡⲓ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⲇⲉ ⲉⲧⲁ ⲗⲱⲧ ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲥⲟⲇⲟⲙⲁ ⲁϥϩⲱⲟⲩ ⳿ⲛⲟⲩ⳿ⲭⲣⲱⲙ ⲛⲉⲙ ⲟⲩⲑⲏⲛ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲧⲫⲉ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥⲧⲁⲕⲉ ⲟⲩⲟⲛ ⲛⲓⲃⲉⲛ.
30 “Gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni yóò rí ní ọjọ́ náà tí Ọmọ Ènìyàn yóò farahàn.
ⲗ̅ⲕⲁⲧⲁ ⲛⲁⲓ ⲣⲱ ⲟⲛ ⲁⲥⲛⲁϣⲱⲡⲓ ϧⲉⲛ ⲡⲓ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⲉⲧⲉ ⳿ⲡϣⲏⲣⲓ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲱⲙⲓ ⲛⲁϭⲱⲣⲡ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲛϧⲏⲧϥ.
31 Ní ọjọ́ náà, ẹni tí ó bá wà lórí ilé, tí ẹrù rẹ̀ sì ń bẹ ní ilẹ̀, kí ó má ṣe sọ̀kalẹ̀ láti wá kó o; ẹni tí ó bá sì wà ní oko, kí ó má ṣe padà sẹ́yìn.
ⲗ̅ⲁ̅ϧⲉⲛ ⲡⲓ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⲇⲉ ⳿ⲉⲧⲉ⳿ⲙⲙⲁⲩ ⲫⲏⲉⲧⲭⲏ ϩⲓϫⲉⲛ ⳿ⲡϫⲉⲛⲉⲫⲱⲣ ⲟⲩⲟϩ ⲉⲣⲉ ⲛⲉϥ⳿ⲥⲕⲉⲩⲟⲥ ϧⲉⲛ ⲡⲓⲏⲓ ⳿ⲙⲡⲉⲛ⳿ⲑⲣⲉϥ⳿ⲓ ⳿ⲉⲡⲉⲥⲏⲧ ⳿ⲉⲟⲗⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲏ ⲉⲧⲭⲏ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲕⲟⲓ ⲡⲁⲓⲣⲏϯ ⲟⲛ ⳿ⲙⲡⲉⲛ⳿ⲑⲣⲉϥⲕⲟⲧϥ ⳿ⲉⲫⲁϩⲟⲩ.
32 Ẹ rántí aya Lọti.
ⲗ̅ⲃ̅ⲁⲣⲓ⳿ⲫⲙⲉⲩⲓ ⳿ⲛ⳿ⲧ⳿ⲥϩⲓⲙⲓ ⳿ⲛⲗⲱⲧ.
33 Ẹnikẹ́ni tí ó bá ń wá àti gba ẹ̀mí rẹ̀ là yóò sọ ọ́ nù; ẹnikẹ́ni tí ó bá sì sọ ọ́ nù yóò gbà á là.
ⲗ̅ⲅ̅ⲫⲏⲉⲑⲛⲁⲕⲱϯ ⳿ⲛⲥⲁ ⲛⲟϩⲉⲙ ⲛⲧⲉϥ ⲯⲩⲭⲏ ⳿ϥⲛⲁⲧⲁⲕⲟⲥ ⲫⲏⲉⲑⲛⲁⲧⲁⲕⲟⲥ ⲉϥ⳿ⲉⲧⲁⲛϧⲟⲥ.
34 Mo wí fún yín, ní òru ọjọ́ náà, ènìyàn méjì yóò wà lórí àkéte kan; a ó mú ọ̀kan, a ó sì fi èkejì sílẹ̀.
ⲗ̅ⲇ̅ϯϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⲛⲱⲧⲉⲛ ϫⲉ ⳿ⲛ⳿ϧⲣⲏⲓ ϧⲉⲛ ⲡⲁⲓ⳿ⲉϫⲱⲣϩ ⲉⲩ⳿ⲉϣⲱⲡⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲃ̅ ⲓϫⲉⲛ ⲟⲩϭⲗⲟϫ ⳿ⲛⲟⲩⲱⲧ ⲡⲓⲟⲩⲁⲓ ⲉⲩ⳿ⲉⲟⲗϥ ⲟⲩⲟϩ ⲡⲓⲕⲉⲟⲩⲁⲓ ⲉⲩ⳿ⲉⲭⲁϥ.
35 Ènìyàn méjì yóò sì máa lọ ọlọ pọ̀; a ó mú ọ̀kan, a ó sì fi èkejì sílẹ̀.”
ⲗ̅ⲉ̅ⲉⲩ⳿ⲉϣⲱⲡⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⳿ⲥⲛⲟⲩϯ ⲉⲩⲛⲟⲩⲧ ϧⲉⲛ ⲟⲩⲙⲁ ⲟⲩ⳿ⲓ ⲉⲩ⳿ⲉⲟⲗⲥ ⲟⲩⲟϩ ϯⲕⲉⲟⲩ⳿ⲓ ⲉⲩ⳿ⲉⲭⲁⲥ.
ⲗ̅ⲋ̅ⲟⲩⲟϩ ⲉⲩⲉⲣⲟⲩ⳿ⲱ ⲡⲉϫⲱⲟⲩ ⲛⲁϥ ϫⲉ ϧⲉⲛ ⲁϣ ⳿ⲙⲙⲁ Ⲡ⳪ ⳿ⲛⲑⲟϥ ⲇⲉ ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲱⲟⲩ ϫⲉ ⲡⲓⲙⲁ ⳿ⲉⲧⲉ ⲡⲓⲥⲱⲙⲁ ⳿ⲙⲙⲟϥ ⲥⲉⲛⲁⲑⲱⲟⲩϯ ⳿ⲉⲙⲁⲩ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲓⲕⲉ⳿ⲁϧⲱⲙ.
37 Wọ́n sì dá a lóhùn, wọ́n bi í pé, “Níbo, Olúwa?” Ó sì wí fún wọn pé, “Níbi tí òkú bá gbé wà, níbẹ̀ pẹ̀lú ni igún ìkójọpọ̀ sí.”
ⲗ̅ⲍ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩⲉⲣⲟⲩⲱ ⲡⲉϫⲱⲟⲩ ⲛⲁϥ ϫⲉ ϧⲉⲛ ⲁϣ ⳿ⲙⲙⲁ Ⲡ⳪ ⳿ⲛⲑⲟϥ ⲇⲉ ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲱⲟⲩ ϫⲉ ⲡⲓⲙⲁ ⲉⲧⲉ ⳿ⲡⲥⲱⲙⲁ ⲙⲟϥ ⲥⲉⲛⲁⲑⲱⲟⲩϯ ⳿ⲉⲙⲁⲩ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲓⲕⲉⲁϧⲱⲙ

< Luke 17 >