< Luke 17 >

1 Ó sì wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Kò le ṣe kí ohun ìkọ̀sẹ̀ máa wa, ṣùgbọ́n ègbé ni fún ẹni tí ó ti ipasẹ̀ rẹ̀ dé.
Te phoeiah a hnukbang rhoek te, “Thangkui te a thoeng pawt ham om tloel coeng. Tedae anunae anih lamloh aka thoeng sak aih.
2 Ìbá sàn fún un kí a so ọlọ mọ́ ọn ní ọrùn, kí a sì gbé e jù sínú Òkun, ju kí ó mú ọ̀kan nínú àwọn kékeré wọ̀nyí kọsẹ̀.
He camoe rhoek khuikah pakhat a khah ham lakah tah a rhawn ah lungto phaklung a oi tih tuili la voei koinih anih ham hoeikhang lah.
3 Ẹ máa kíyèsára yín. “Bí arákùnrin rẹ bá ṣẹ̀, bá a wí; bí ó bá sì ronúpìwàdà, dáríjì ín.
Namamih te ngaithuen uh, na manuca loh a tholh atah amah te toel, a yut atah anih te hlah laeh.
4 Bí ó bá sì ṣẹ̀ ọ́ ní igba méje ní òòjọ́, tí ó padà tọ̀ ọ́ wá ní ìgbà méje ní òòjọ́ pé, ‘Mo ronúpìwàdà,’ dáríjì ín.”
Hnin at neh nang soah voei rhih tholh coeng dae namah taengla voei rhih ha bal tih, “Ka yut,” a ti coeng atah anih te hlah laeh,” a ti nah.
5 Àwọn aposteli sì wí fún Olúwa pé, “Bù sí ìgbàgbọ́ wa.”
Caeltueih rhoek loh Boeipa taengah, “Kaimih ham tangnah han thap lah,” a ti uh.
6 Olúwa sì wí pé, “Bí ẹ̀yin bá ní ìgbàgbọ́ bí hóró irúgbìn musitadi, ẹ̀yin yóò lè wí fún igi sikamine yìí pé, ‘Di fi fà á tu, kí a sì gbìn ọ́ sínú Òkun,’ yóò sì gbọ́ tiyín.
Tedae Boeipa loh, “Tangnah he mukang mu tet na khueh uh koinih, hekah thaihae kung he, 'Phong uh lamtah tuili ah phung,’ na ti uh mai cakhaw nangmih kah te a ngai ni.
7 “Ṣùgbọ́n ta ni nínú yín, tí ó ní ọmọ ọ̀dọ̀, tí ó ń tulẹ̀, tàbí tí ó ń bọ́ ẹran, tí yóò wí fún un lójúkan náà tí ó bá ti oko dé pé, ‘Lọ í jókòó láti jẹun’?
Nangmih khuiah sal aka khueh te tah lai a thol pah tih boiva a dawn pah. Lohma lamkah a paipaek vaengah anih te u long, ‘Ha kun lamtah cawt ngol dae,’ a ti na eh?
8 Tí kì yóò kúkú wí fún un pé, ‘Pèsè ohun tí èmi yóò jẹ, sì di àmùrè, kí ìwọ kí ó máa ṣe ìránṣẹ́ fún mi, títí èmi ó fi jẹ kí èmi ó sì mu tán; lẹ́yìn náà ni ìwọ ó sì jẹ, tí ìwọ ó sì mu’?
Anih te, “Mebang khaw tawn lamtah ka ca eh?, te phoeiah cihnin vaep lamtah ka caak ka ok vaengah kai taengah thotat, te phoeiah ni na caak na ok eh?, 'ti na mahpawt nim?
9 Òun ó ha máa dá ọpẹ́ lọ́wọ́ ọmọ ọ̀dọ̀ náà, nítorí ó ṣe ohun tí a pàṣẹ fún un bí? Èmi kò rò bẹ́ẹ̀.
A uen te a saii dongah sal soah lungvatnah khueh mapawt nim?
10 Gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin pẹ̀lú, nígbà tí ẹ bá ti ṣe ohun gbogbo tí a pàṣẹ fún yín tán, ẹ wí pé, ‘Aláìlérè ọmọ ọ̀dọ̀ ni wá: èyí tí í ṣe iṣẹ́ wa láti ṣe, ní àwa ti ṣe.’”
Nangmih khaw, nangmih ng'uen te boeih na saii uh tangloeng dae, ' kaimih tah sal hlangkhue hlangvaih rhoek ni, saii ham a kuek te ni n'saii, 'ti uh mai,” a ti nah.
11 Ó sì ṣe, bí ó ti ń lọ sí Jerusalẹmu, ó kọjá láàrín Samaria Galili.
Jerusalem la a caeh a om vaengah Jesuh tah Samaria neh Galilee laklo longah cet.
12 Bí ó sì ti ń wọ inú ìletò kan lọ, àwọn ọkùnrin adẹ́tẹ̀ mẹ́wàá pàdé rẹ̀, wọ́n dúró ní òkèrè,
Te vaengah vangca pakhat la a kun hatah hmaibae hlang parha loh Jesuh te a doe uh tih amamih tah soei pai uh.
13 wọ́n sì kígbe sókè wí pé, “Jesu, Olùkọ́, ṣàánú fún wa.”
Te phoeiah a ol a huel uh tih, “Boeipa Jesuh kaimih n'rhen lah,” a ti uh.
14 Nígbà tí ó rí wọn, ó wí fún wọn pé, “Ẹ lọ í fi ara yín hàn fún àwọn àlùfáà.” Ó sì ṣe, bí wọ́n ti ń lọ, wọ́n sì di mímọ́.
Amih te a hmuh vaengah, “Cet uh lamtah namamih te khosoih rhoek taengah tueng uh,” a ti nah. Tedae a caeh uh li vaengah mah amih te boeih cim uh.
15 Nígbà tí ọ̀kan nínú wọn rí i pé a mú òun láradá ó padà, ó sì fi ohùn rara yin Ọlọ́run lógo.
Tedae amih khuikah pakhat long tah a hoeih te a hmuh vaengah bal tih ol ue la Pathen te a thangpom.
16 Ó sì wólẹ̀ lẹ́bàá ẹsẹ̀ rẹ̀, ó ń dúpẹ́ ní ọwọ́ rẹ̀: ará Samaria ni òun í ṣe.
Te phoeiah anih tah Samaria dae ni a kho kung ah maelhmai a buluk thil tih Jesuh te a uem.
17 Jesu sì dáhùn wí pé, “Àwọn mẹ́wàá kí a sọ di mímọ́? Àwọn mẹ́sàn-án ìyókù ha dà?
Te dongah Jesuh loh a doo tih, “Parha la a cim uh moenih a? Pako rhoek ta melae?,”
18 A kò rí ẹnìkan tí ó padà wá fi ògo fún Ọlọ́run, bí kò ṣe àlejò yìí?”
Anih kholong hlang pawt atah Pathen te thangpomnah paek ham aka bal hmu uh boel saeh a?” a ti nah.
19 Ó sì wí fún un pé, “Dìde, kí o sì máa lọ, ìgbàgbọ́ rẹ mú ọ láradá.”
Te phoeiah anih te, “Thoo, cet laeh, namah kah tangnah loh namah ng'khang coeng,” a ti nah.
20 Nígbà tí àwọn Farisi bi í pé, nígbà wo ni ìjọba Ọlọ́run yóò dé, ó dá wọn lóhùn pé, “Ìjọba Ọlọ́run kì í wá pẹ̀lú àmì.
Pathen kah ram ha pawk vaengkah te Pharisee rhoek loh a dawt dongah amih te a doo tih, “Pathen kah ram tah hmuhnah neh ha pawk moenih.
21 Bẹ́ẹ̀ ni wọn kì yóò wí pé, ‘Kíyèsi i níhìn-ín!’ tàbí ‘Kíyèsi i lọ́hùn ún ni!’ sá à wò ó, ìjọba Ọlọ́run ń bẹ nínú yín.”
“'He la he, ke la ke, 'ti uh mahpawh. Pathen kah ram tah namamih khuiah ni a om te,” a ti nah.
22 Ó sì wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Ọjọ́ ń bọ̀, nígbà tí ẹ̀yin yóò fẹ́ láti rí ọ̀kan nínú ọjọ́ Ọmọ Ènìyàn, ẹ̀yin kì yóò sì rí i.
Te phoeiah hnukbang rhoek te, “Khohnin ha pawk vaengah hlang capa kah khohnin te hnin at hmuh ham na hue uh suidae na hmuh uh mahpawh.
23 Wọ́n sì wí fún yín pé, ‘Wò ó níhìn-ín!’ tàbí ‘Wò ó lọ́hùn ún!’ Ẹ máa lọ, ẹ má ṣe tẹ̀lé wọn.
Nangmih taengah, 'Ke la ke, he la he,’ a ti uh akhaw cet uh boeh, hnuktlak uh boeh.
24 Nítorí gẹ́gẹ́ bí mọ̀nàmọ́ná ti í kọ ní apá kan lábẹ́ ọ̀run, tí sì í mọ́lẹ̀ ní apá kejì lábẹ́ ọ̀run, bẹ́ẹ̀ ni Ọmọ Ènìyàn yóò sì rí ní ọjọ́ rẹ̀.
Khophaa loh phaa tih vaan hmui pakhat lamkah loh vaan hmui pakhat la sae ni. Hlang capa tah amah tue vaengah ha om tangloeng bitni.
25 Ṣùgbọ́n kò lè ṣàìmá kọ́ jìyà ohun púpọ̀, kí a sì kọ̀ ọ́ lọ́dọ̀ ìran yìí.
Tedae lamhma la muep a patang ham neh tahae cadil loh a hnawt ham khaw a kuek.
26 “Bí ó ti rí ní ọjọ́ Noa, bẹ́ẹ̀ ni yóò rí ní ọjọ́ Ọmọ Ènìyàn.
Noah tue vaengkah a om vanbangla, hlang capa kah a tue vaengah khaw om van ni.
27 Wọ́n ń jẹ, wọ́n ń mu, wọ́n ń gbéyàwó, wọ́n sì ń fa ìyàwó fún ni, títí ó fi di ọjọ́ ti Noa wọ inú ọkọ̀ lọ, kíkún omi sì dé, ó sì run gbogbo wọn.
Noah lawng khuila a kun khohnin duela yuloh rhaihlan neh a caak a okuh. Te dongah tuliii ha pawk vaengah boeih poci.
28 “Bí ó sì ti rí ní ọjọ́ Lọti; wọ́n ń jẹ, wọ́n ń mu, wọ́n ń rà, wọ́n ń tà, wọ́n ń gbìn, wọ́n ń kọ́lé,
Lot kah khohnin vaengah khaw amah boeiloeih la om uh tih a caak uh, a ok uh, a lai uh, a yoih uh, a tawn uh, a sak uh.
29 ṣùgbọ́n ní ọjọ́ náà tí Lọti jáde kúrò ní Sodomu, òjò iná àti sulfuru rọ̀ láti ọ̀run wá, ó sì run gbogbo wọn.
Tedae Sodom lamkah loh Lot a caeh khohnin ah, vaan lamkah hmai neh kat a tlan pah tih boeih poci.
30 “Gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni yóò rí ní ọjọ́ náà tí Ọmọ Ènìyàn yóò farahàn.
Hlang capa a pumphoe tue vaengah amah boeiloeih la om ni.
31 Ní ọjọ́ náà, ẹni tí ó bá wà lórí ilé, tí ẹrù rẹ̀ sì ń bẹ ní ilẹ̀, kí ó má ṣe sọ̀kalẹ̀ láti wá kó o; ẹni tí ó bá sì wà ní oko, kí ó má ṣe padà sẹ́yìn.
Te khohnin vaengah imphu ah aka om tah, im khuikah a hno te loh hamla suntla boel saeh. Lohma kah long khaw a hnuk la mael van boel saeh.
32 Ẹ rántí aya Lọti.
Lot yuu te poek uh.
33 Ẹnikẹ́ni tí ó bá ń wá àti gba ẹ̀mí rẹ̀ là yóò sọ ọ́ nù; ẹnikẹ́ni tí ó bá sì sọ ọ́ nù yóò gbà á là.
A hinglu te kutloh ham aka toem long tah poci ni, tedae aka hlong long tah tekah a hing thil ni.
34 Mo wí fún yín, ní òru ọjọ́ náà, ènìyàn méjì yóò wà lórí àkéte kan; a ó mú ọ̀kan, a ó sì fi èkejì sílẹ̀.
Nangmih taengah ka thui, tekah khoyin ah panit loh thingkong pakhat dongah om rhoi cakhaw, pakhat te a khuen vetih pakhat te a hlun ni.
35 Ènìyàn méjì yóò sì máa lọ ọlọ pọ̀; a ó mú ọ̀kan, a ó sì fi èkejì sílẹ̀.”
Amah nawn ah ah sum aka kuelh panit om ni. Pakhat te a khuen vetih, pakhat a hlun ni,” a ti nah.
Te dongah amah te a doo uh tih, “Melae Boeipa,” a ti nauh.
37 Wọ́n sì dá a lóhùn, wọ́n bi í pé, “Níbo, Olúwa?” Ó sì wí fún wọn pé, “Níbi tí òkú bá gbé wà, níbẹ̀ pẹ̀lú ni igún ìkójọpọ̀ sí.”
Tedae amih te, “Rhok te tah langta loh pahoi a bo van ni,” a ti nah.

< Luke 17 >