< Luke 16 >
1 Ó sì wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pẹ̀lú pé, “Ọkùnrin ọlọ́rọ̀ kan wà, tí ó ní ìríjú kan; òun náà ni wọ́n fi sùn ún pé, ó ti ń fi ohun ìní rẹ̀ ṣòfò.
A OLELO mai la o Iesu i kana mau haumana, O kekahi kanaka waiwai he puuku kana; a ua haiia ia ia na puuku la i kona hokai ana i kana waiwai.
2 Nígbà tí ó sì pè é, ó wí fún un pé, ‘Èéṣe tí èmi fi ń gbọ́ èyí sí ọ? Ṣírò iṣẹ́ ìríjú rẹ; nítorí ìwọ kò lè ṣe ìríjú mi mọ́.’
A kii aku la oia ia ia, i aku la ia ia, Heaha keia a'u i lohe iho nei ia oe? E hoike mai oe i kou malama ana, no ka mea, aole oe e puuku hou aku.
3 “Ìríjú náà sì wí nínú ara rẹ̀ pé, ‘Èwo ni èmi ó ṣe? Nítorí tí olúwa mi gba iṣẹ́ ìríjú lọ́wọ́ mi: èmi kò le ṣiṣẹ́ oko, bẹ́ẹ̀ ni ojú ń tì mí láti ṣagbe.
I iho la ka puuku ia ia iho, Pehea la wau e hana'i? No ka mea, e lawo ana kuu haku i ka puuku mai o'u aku nei; aole hiki ia'u ke mahi, a hilahila no wau i ko noi.
4 Mo mọ èyí tí èmi yóò ṣe, nígbà tí a bá mú mi kúrò níbi iṣẹ́ ìríjú, kí àwọn ènìyàn le gbà mí sínú ilé wọn.’
Ua ike au i ka'u mea e hana aku ai, i hookipa kokahi poe ia'u i ko lakou mau hale, i ka wa e hemo aku ai ko'u puuku.
5 “Ó sì pe àwọn ajigbèsè olúwa rẹ̀ sọ́dọ̀ rẹ̀, ó sì wí fún èkínní pé, ‘Èló ni ìwọ jẹ olúwa mi?’
A kii aku la ia i kela mea aie keia mea aie a kona haku, ninau aku la oia i kekahi, Pehea ka nui o kau aie i kuu haku?
6 “Ó sì wí pé, ‘Ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rún òsùwọ̀n òróró.’ “Ó sì wí fún un pé, ‘Mú ìwé rẹ, sì jókòó nísinsin yìí, kí o sì kọ àádọ́ta lé ní irinwó.’
Hai mai la hoi ia, Hookahi haneri bato aila. A i aku la oia ia ia, E lawe oe i kau palapala, a noho koke iho oe e kakau i kanalima.
7 “Nígbà náà ni ó sì bi ẹnìkejì pé, ‘Èló ni ìwọ jẹ?’ “Òun sì wí pé, ‘Ẹgbẹ̀rún òsùwọ̀n alikama.’ “Ó sì wí fún un pé, ‘Mú ìwé rẹ, kí o sì kọ ẹgbẹ̀rin.’
Alaila ninau aku la oia i kekahi, Pehea la ka nui o kau aie? A hai mai la ia, Hookahi haneri homera hua palaoa. I aku la hoi oia ia ia, E lawe i kau palapala, a e kakau iho i kanawalu.
8 “Olúwa rẹ̀ sì yin aláìṣòótọ́ ìríjú náà, nítorí tí ó fi ọgbọ́n ṣe é, àwọn ọmọ ayé yìí sá à gbọ́n ní ìran wọn ju àwọn ọmọ ìmọ́lẹ̀ lọ. (aiōn )
A mahalo iho la ua haku la i ka puuku pono ole, no kana hana akamai ana. Oia hoi, ua oi aku ke akamai o na keiki o neia ao i ka lakou hanauna mamua o ko na keiki o ka malamalama. (aiōn )
9 Èmi sì wí fún yín, ẹ fi ọrọ̀ ayé yìí yan ọ̀rẹ́ fún ara yín pé, nígbà tí o ba lọ, kí wọn kí ó le gbà yín sí ibùjókòó wọn títí ayé. (aiōnios )
Ke olelo aku nei no hoi au ia oukou, Me ka waiwai oiaio ole, e hoomakamaka ai oukou i mau makamaka no oukou, i hookipa lakou ia oukou iloko o na hale pau ole, i ka wa e haule ai oukou. (aiōnios )
10 “Ẹni tí ó bá ṣe olóòtítọ́ nínú ohun kínkínní, ó ṣe olóòtítọ́ ní púpọ̀ pẹ̀lú: ẹni tí ó bá sì ṣe aláìṣòótọ́ ní ohun kínkínní, ó ṣe aláìṣòótọ́ ní ohun púpọ̀ pẹ̀lú.
O ka mea i malama pono i ka mea uuku, oia ke malama pono i ka mea nui; a o ka mea i hana hewa ma ka mea uuku, oia hoi ke hana hewa ma ka mea nui.
11 Ǹjẹ́ bí ẹ̀yin kò bá ti jẹ́ olóòtítọ́ nínú ọrọ̀ ayé yìí, ta ni yóò fi ọ̀rọ̀ tòótọ́ fún yín?
Nolaila, ina i ole oukou e malama pono i ka waiwai oiaio ole, nawai la e waiho ia oukou i ka waiwai oiaio?
12 Bí ẹ̀yin kò bá sì ti jẹ́ olóòtítọ́ nínú ohun tí í ṣe ti ẹlòmíràn, ta ni yóò fún yín ní ohun tí í ṣe ti ẹ̀yin tìkára yín?
A ina i ole oukou i malama pono i ka hai waiwai, nawai la hoi e haawi i waiwai na oukou ponoi?
13 “Kò sì í ẹnìkan tí ó lè sin ọ̀gá méjì. Òun yóò yà kórìíra ọ̀kan tí yóò fẹ́ràn èkejì, tàbí kí ó fi ara mọ́ ọ̀kan kí ó sì yan èkejì ní ìpọ̀sí. Ẹ̀yin kò lè sin Ọlọ́run àti owó papọ̀.”
Aohe kauwa e hiki ke hookauwa na na haku elua; no ka mea, e hoowahawaha oia i kekahi me ka makemake i kekahi, a i ole ia, e hahai aku ia i kela, me ka haalele i keia. Aole hoi e hiki ia oukou ke hookauwa na ke Akua a me ka mamona.
14 Àwọn Farisi, tí wọ́n ní ojúkòkòrò sì gbọ́ gbogbo nǹkan wọ̀nyí, wọ́n sì yọ ṣùtì sí i.
A lohe ae la na Parisaio ka poe puni waiwai i keia mau mea, henehene iho la lakou ia ia.
15 Ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ni àwọn tí ń dá àre fún ara yín níwájú ènìyàn; ṣùgbọ́n Ọlọ́run mọ ọkàn yín, nítorí ohun ti a gbéga lójú ènìyàn, ìríra ni níwájú Ọlọ́run.
I mai la oia ia lakou, O oukou ka poe e hoopono ia oukou iho imua o na kanaka; aka, ua ike mai ke Akua i ko oukou mau naau, no ka mea, o kahi mea nani i kanaka, he ino ia imua o ke Akua.
16 “Òfin àti àwọn wòlíì ń bẹ títí di ìgbà Johanu, Láti ìgbà náà wá ni a ti ń wàásù ìròyìn ayọ̀ ìjọba Ọlọ́run, olúkúlùkù sì ń fi ipá wọ inú rẹ̀.
E mau mai ana ke kanawai a me ka poe kaula a hiki ia Ioane; a mai ia manawa mai, ua haiia'ku ke aupuni o ke Akua, a ma ka hoikaika loa, e komo ai na mea a pau.
17 Ṣùgbọ́n ó rọrùn fún ọ̀run òun ayé láti kọjá lọ, ju kí èyí tí ó kéré jù nínú òfin kí ó yẹ.
E lilo ka lani a me ka honua mamua o ka haule ana o kekahi huna o ke kanawai.
18 “Ẹnikẹ́ni tí ó bá kọ aya rẹ̀ sílẹ̀, tí ó sì gbé ẹlòmíràn ní ìyàwó, ó ṣe panṣágà: ẹnikẹ́ni tí ó bá sì gbé, ẹni tí ọkọ rẹ̀ kọ̀sílẹ̀ ní ìyàwó náà, ó ṣe panṣágà.
O ka mea i hoohemo i kana wahine, a e mare aku hoi i kekahi, oia ke moe kolohe. A o ka mea i mare i ka wahine i hoohemoia, oia ke moe kolohe.
19 “Ǹjẹ́ ọkùnrin ọlọ́rọ̀ kan wà, tí ó ń wọ aṣọ elése àlùkò àti aṣọ àlà dáradára, a sì máa jẹ dídùndídùn lójoojúmọ́.
O kekahi kanaka waiwai ua aahuia i ka lole makue a me ka ie nani, ua ahaaina olioli ia i kela la i keia la.
20 Alágbe kan sì wà tí à ń pè ní Lasaru, tí wọ́n máa ń gbé wá kalẹ̀ lẹ́bàá ọ̀nà ilé rẹ̀, ó kún fún ooju,
A o kekahi kanaka ilihune, o Lazaro kona inoa, ua waihoia aku la ia ma kona ipuka, ua paapu i na mai hehe;
21 Òun a sì máa fẹ́ kí a fi èérún tí ó ti orí tábìlì ọlọ́rọ̀ bọ́ sílẹ̀ bọ́ òun, àwọn ajá sì wá, wọ́n sì fá a ní ooju lá.
E ake ia e hanaiia mai i na hunahuna i haule mai luna iho o ka papaaina o ua kauaka waiwai la. A hele mai hoi na ilio a palu iho la i kona mau mai.
22 “Ó sì ṣe, alágbe kú, a sì ti ọwọ́ àwọn angẹli gbé e lọ sí oókan àyà Abrahamu: ọlọ́rọ̀ náà sì kú pẹ̀lú, a sì sin ín;
Eia hoi kekahi, make aku la ia kanaka ilihune, a laweia aku la oia e na anela ma ka poli o Aberahama; a make aku la hoi ua kanaka waiwai la, a kanuia iho la.
23 Ní ipò òkú ni ó gbé ojú rẹ̀ sókè, ó ń bẹ nínú ìjìyà oró, ó sì rí Abrahamu ní òkèrè, àti Lasaru ní oókan àyà rẹ̀. (Hadēs )
A maloko o ka no oia i nana aku ai, me ka eha nui, ike aku la ia Aberahama i kahi loihi aku a me Lazaro ma kona poli; (Hadēs )
24 Ó sì ké, ó wí pé, ‘Baba Abrahamu, ṣàánú fún mi, kí o sì rán Lasaru, kí ó tẹ orí ìka rẹ̀ bọ omi, kí ó sì fi tù mí ní ahọ́n; nítorí èmi ń joró nínú ọ̀wọ́n iná yìí.’
A kahea aku la ia, i aku la, E ka makua, e Aberahama, e aloha mai oe ia'u, a e hoouna mai ia Lazaro e o iho ia i ka welau o kona manamana lima iloko o ka wai, a e hoomaalili mai i ko'u alelo; no ka mea, ua eha loa au iloko o keia lapalapa.
25 “Ṣùgbọ́n Abrahamu wí pé, ‘Ọmọ, rántí pé, nígbà ayé rẹ, ìwọ ti gba ohun rere tìrẹ, àti Lasaru ohun búburú, ṣùgbọ́n nísinsin yìí ara rọ̀ ọ́, ìwọ sì ń joró.
Alaila i mai la o Aberahama, E ke keiki, e hoomanao oe, ua loaa ia oe kau mau mea maikai i kou wa e ola ana; a ia Lazaro hoi na mea ino. Ano hoi ua hooluoluia oia nei, a ua hoehaehaia hoi oe.
26 Àti pẹ̀lú gbogbo èyí, a gbé ọ̀gbun ńlá kan sí agbede-méjì àwa àti ẹ̀yin, kí àwọn tí ń fẹ́ má ba á le rékọjá láti ìhín lọ sọ́dọ̀ yín, kí ẹnikẹ́ni má sì le ti ọ̀hún rékọjá tọ̀ wá wá.’
A he mea e ae no hoi, ua waihoia mai he awawa nui iwaena o makou a me oukou, i ole ai e hiki ka poe o manao ana e hele aku mai keia wahi aku io oukou la; ao ko laila poe aole e hiki ke hele mai io makou nei.
27 “Ó sì wí pé, ‘Ǹjẹ́ mo bẹ̀ ọ́, baba, kí ìwọ kí ó rán Lasaru lọ sí ilé baba mi,
I aku la hoi oia, Nolaila ke noi aku nei au ia oe, e ka makua, o hoouna oe ia ia i ka halo o ko'u makuakane;
28 nítorí mo ní arákùnrin márùn-ún; kí ó lè rò fún wọn kí àwọn kí ó má ba á wá sí ibi oró yìí pẹ̀lú.’
No ka mea, ho mau hoahanau kano ko'u elima, e ao aku oia ia lakou, o hiki mai lakou i keia wahi eha.
29 “Abrahamu sì wí fún un pé, ‘Wọ́n ní Mose àti àwọn wòlíì; kí wọn kí ó gbọ́ tiwọn.’
I mai la o Aberahama ia ia. Aia no hoi ia lakou o Moso a me ka poe kaula, i lohe lakou ia mau mea.
30 “Ó sì wí pé, ‘Bẹ́ẹ̀ kọ́, Abrahamu baba; ṣùgbọ́n bí ẹnìkan bá ti inú òkú tọ̀ wọ́n lọ, wọn ó ronúpìwàdà.’
A i aku la oia, Aole, e ka makua, o Aberahama; aka, ina e hele aku kekahi mai waena aku o ka poe make, e mihi no lakou.
31 “Ó sì wí fún un pé, ‘Bí wọn kò bá gbọ́ ti Mose àti ti àwọn wòlíì, a kì yóò yí wọn ní ọkàn padà bí ẹnìkan tilẹ̀ ti inú òkú dìde.’”
I mai la hoi oia ia ia, Ina i lohe ole lakou ia Mose a me ka poe kaula, aole no lakou e hoohuliia ke ala hou kekahi mai waena aku o ka poe make.