< Luke 10 >
1 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí, Olúwa sì yan méjìléláàádọ́rin ọmọ-ẹ̀yìn mìíràn pẹ̀lú, ó sì rán wọn ní méjì méjì lọ ṣáájú rẹ̀, sí gbogbo ìlú àti ibi tí òun tìkára rẹ̀ yóò sì dé.
Li puoli po, ke O Diedo go lugdi o ŋɔdkaaba piilele, ki sɔni ba bilie lie ke ban liidi o u dogu po leni ya dongbana ke wani o bá bi ba gedi.
2 Ó sì wí fún wọn pé, “Ìkórè pọ̀, ṣùgbọ́n àwọn alágbàṣe kò tó nǹkan, nítorí náà ẹ bẹ Olúwa ìkórè, kí ó lè rán àwọn alágbàṣe sínú ìkórè rẹ̀.
Ki maadi ba, “u bontaadu yogu pundi. ku kpaangu yabi ama a tuonsɔnla ki yabi. Tin mia O Diedo yua n die u kuanu, wan sɔni a tuonsɔnla o kuanu nni.
3 Ẹ mú ọ̀nà yín pọ̀n: sá wò ó, èmi rán yín lọ bí ọ̀dọ́-àgùntàn sáàrín ìkookò.
Ya caa mani. N suani yi nani mu pabimu yeni i yangbanli siiga.
4 Ẹ má ṣe mú àpò, ẹ má ṣe mú àpamọ́wọ́, tàbí bàtà: ẹ má sì ṣe kí ẹnikẹ́ni lọ́nà.
yin da taa ligbɔgli, ki da kubi sancenbɔgli ki buali taacaadi, ki go da biandi yaama i fuondi po u sanu nni.
5 “Ní ilékílé tí ẹ̀yin bá wọ̀, kí ẹ kọ́ wí pé, ‘Àlàáfíà fún ilé yìí!’
Ke yin ba kua ya diegu nni kuli, yin cindi ki yedi, “Mi yanduanma ń ya ye ku diegu ne nni”.
6 Bí ọmọ àlàáfíà bá sì wà níbẹ̀, àlàáfíà yín yóò bà lé e: ṣùgbọ́n bí kò bá sí, yóò tún padà sọ́dọ̀ yín.
Mi yanduanma nilo ya ye li diegu nni, i yanduanma baa ye leni o, li ya ki tie yeni, mi ba guani i po.
7 Ẹ dúró sínú ilé náà, kí ẹ máa jẹ, kí ẹ sì máa mu ohunkóhun tí wọ́n bá fi fún yín, nítorí ọ̀yà alágbàṣe tọ́ sí i. Ẹ má ṣe lọ láti ilé dé ilé.
Yin ya ye lan ya diegu nni, ki di ki go ñu ban puni yaala, kelima o tuonsɔnlo dagdini o ŋmapani. Yin da ña diegu ki tuadi diegu.
8 “Ìlúkílùú tí ẹ̀yin bá wọ̀, tí wọ́n bá sì gbà yín, ẹ jẹ ohunkóhun tí a bá gbé ka iwájú yín.
Yin kua ya dogu nni kuli, ke bi ga i cangu, yin di ban candi yi yaala,
9 Ẹ sì mú àwọn aláìsàn tí ń bẹ nínú rẹ̀ láradá, kí ẹ sì wí fún wọn pé, ‘Ìjọba Ọlọ́run kù sí dẹ̀dẹ̀ sí yín!’
ki paagdi yaaba n tie bi yiama. Yin yedi ba, “U Tienu diema nagi i kani”.
10 Ṣùgbọ́n ní ìlúkílùú tí ẹ̀yin bá sì wọ̀, tí wọn kò bá sì gbà yín, nígbà tí ẹ̀yin bá sì jáde ní ìgboro ìlú náà, kí ẹ̀yin sì wí pé,
Ama, yin ba kua ya dogu nni ke baa ga i cangu, yin ña ki cendi bi sanjala po, ki yedi,
11 ‘Eruku ìlú yín tí ó kù sí wa lẹ́sẹ̀, a gbọ̀n ọ́n sílẹ̀ fún yín! Ṣùgbọ́n ẹ mọ èyí pé, ìjọba Ọlọ́run kù sí dẹ̀dẹ̀.’
“Ti pidi i dogu ne ya taatama n tabi ti taana, ki guani ki yadi i po, ke lan tua tiadma i po! Ama yin ya bani yaali ne, “U Tienu diema nagini.
12 Ṣùgbọ́n mo wí fún yín, yóò sàn fún Sodomu ní ọjọ́ náà, ju fún ìlú náà lọ.
N maadi yi ke ti buudi daali, Sodoma buudi baa pia sugli ki cie lan ya dogu.
13 “Ègbé ni fún ìwọ, Korasini! Ègbé ni fún ìwọ Betisaida! Nítorí ìbá ṣe pé a ti ṣe iṣẹ́ agbára tí a ṣe nínú yín, ní Tire àti Sidoni, wọn ìbá ti ronúpìwàdà lọ́jọ́ pípẹ́ sẹ́yìn, wọn ìbá sì jókòó nínú aṣọ ọ̀fọ̀ àti nínú eérú.
korasen, sola! Betsahida, sola! Ya yenmaaltuona n tieni i siiga ne ya bo tieni Tiiri leni Sidoni dogi nni, li dogi niba bo ba tuo ki lebdi bi pala hali ke li dá fagi, ki la ti yubɔntiadi, ki pugi bi bá mi fatanpienma.
14 Ṣùgbọ́n yóò sàn fún Tire àti Sidoni nígbà ìdájọ́ jù fún yín lọ.
Ama, ti buudi yogu, Tiiri leni Sidoni yaala baa pia sugli ki cie yinba.
15 Àti ìwọ, Kapernaumu, a ó ha gbé ọ ga dé òkè ọ̀run? A ó rẹ̀ ọ́ sílẹ̀ dé isà òkú. (Hadēs )
Ke fini, Kapenawuma, a maali ke a ba duoni a yuli ŋaljanli nni bii? N n bi ba jiini a hali ku tinkpibuogu nni. (Hadēs )
16 “Ẹni tí ó bá gbọ́ tiyín, ó gbọ́ tèmi. Ẹni tí ó bá sì kọ̀ yín, ó kọ̀ mi. Ẹni tí ó bá sì kọ̀ mi, ó kọ ẹni tí ó rán mi.”
Yua n cengi yi, o cengi mini i, yua n ki ga i maama ki ga mini ya maama i, yua n yie n maama yie yua n sɔni nni maama i.
17 Àwọn àádọ́rin náà sì fi ayọ̀ padà, wí pé, “Olúwa, àwọn ẹ̀mí èṣù tilẹ̀ foríbalẹ̀ fún wa ní orúkọ rẹ.”
Li tondba piilele den guani leni li pamanli, ki maadi O Diedo, “Ti Diedo, ba ́ mu cicibidmu mɔno cɔlni ti maama a yeli po.”
18 Ó sì wí fún wọn pé, “Èmí rí Satani ṣubú bí mọ̀nàmọ́ná láti ọ̀run wá.
K Jesu maadi ba, “N den nua Setaani ke o ñani ŋaljanli nni ki baa.
19 Kíyèsi i, èmí fún yín ní àṣẹ láti tẹ ejò àti àkéekèe mọ́lẹ̀, àti lórí gbogbo agbára ọ̀tá, kò sì ṣí ohun kan bí ó ti wù tí ó ṣe, tí yóò pa yín lára.
Cengi mani, N puni yi ti yikodi, ke yin ya ŋmaadi i wee leni i nami leni yibali paaciamu po kuli. lan ba baa maama kuli, liba kuli kan fidi ki tieni yi yaala n bia.
20 Ṣùgbọ́n kí ẹ má ṣe yọ̀ nítorí èyí pé, àwọn ẹ̀mí ń foríbalẹ̀ fún yín; ṣùgbọ́n ẹ kúkú yọ̀, pé; a kọ̀wé orúkọ yín ní ọ̀run!”
Ama, yeni lankuli, yin da mangdi i pala ke mu cicibiadmu cɔlni i maama baba po ka, ama yi pala ń́ ŋanbi ki ya mani kelime i yela diani ŋaljanli nni”
21 Ní wákàtí kan náà Jesu yọ̀ nínú Ẹ̀mí mímọ́ ó sì wí pé, “Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ, Baba, Olúwa ọ̀run àti ayé, pé, ìwọ pa nǹkan wọ̀nyí mọ́ kúrò lọ́dọ̀ àwọn ọlọ́gbọ́n àti amòye, ìwọ sì fi wọ́n hàn fún àwọn ọmọ ọwọ́. Bẹ́ẹ̀ ni, Baba, bẹ́ẹ̀ ni ó sá à yẹ ní ojú rẹ.
Lanyognu liga, ke o pali mangi boncianli U Tienu foŋanma po, ke o yedi, “N dondi a, Báa, Tanpoli yini ki tinga Diedo, kelima a dɔgni lanya bona bi yanfodanba leni bi nunfandanba po, ki nan dɔgdi a yaaba n ki pia yama nani mu biñidmu yeni po. Nn, Báa, kelima, li den ŋɔdi a yanjagŋanli bonŋanla.”
22 “Ohun gbogbo ni a ti fi fún mi láti ọ̀dọ̀ Baba mi; kò sì ṣí ẹni tí ó mọ ẹni tí ọmọ jẹ́, bí kò ṣe Baba, àti ẹnikẹ́ni tí ó bá sì wu ọmọ láti fi í hàn fún.”
N Báa duu n po ki, kubni nni a bona kuli, ke obá kuli ki ban Bijua ń tie yua, lan ñani Báa baba, obá mo ki bani báa ń tie yua li nan ya ki tie Bijua yaa ka, yeni Bijua ń bua yua ki ba dɔgdi o po.
23 Ó sì yípadà sí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ní apá kan. Ó ní, “Ìbùkún ni fún ojú tí ń rí ohun tí ẹ̀yin ń rí.
Ki guani ki gbagi o ŋɔdkaaba po, ki maadi ba ŋasiili nni. “Mi yedŋanma yaaba n laadi yin laadi yaala.
24 Nítorí mo wí fún yín, ọ̀pọ̀ àwọn wòlíì àti àwọn ọba ni ó ń fẹ́ láti rí ohun tí ẹ̀yin ń rí, wọn kò sì rí wọn, àti láti gbọ́ ohun tí ẹ̀yin ń gbọ́, wọn kò sì gbọ́ wọn.”
N maadi yi, sawalpuaba bonianla yeni bi badcianba den suni ke ban la yin laadi yaala, ki nan ki la ŋa, ke ban gbadi yin gbia yaala, ki nan ki gbadi ŋa.
25 Sì kíyèsi i amòfin kan dìde, ó ń dán an wò, ó ní, “Olùkọ́, kín ni èmi ó ṣe kí èmi lè jogún ìyè àìnípẹ̀kun?” (aiōnios )
Diidi mani, jufinba yoko tundkaaba yendo ń fii, ki bua bigni Jesu, ki maadi, “Canbáa, N ba tieni ledi i, ki baa ya miali n ki pia gbenma? (aiōnios )
26 Ó sì bi í pé, “Kí ni a kọ sínú ìwé òfin? Báwo ni ìwọ sì ti kà á?”
Jesu ń buali o, “Be diani yiko tili nni? A cogi be li tili nni?”
27 Ó sì dáhùn wí pé, “‘Kí ìwọ fi gbogbo àyà rẹ, àti gbogbo ọkàn rẹ, àti gbogbo agbára rẹ, àti gbogbo inú rẹ fẹ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ’; àti, ‘Ẹnìkejì rẹ bí ara rẹ.’”
Wan jiini ki maadi, “A baa bua O Diedo, a Tienu leni a pali kuli, leni a naano kuli, leni a paalu kuli, leni a yantiali kuli, ki go ya bua a nisaalilielo nani abá yeni.”
28 Ó sì wí fún un pé, “Ìwọ́ dáhùn rere. Ṣe èyí, ìwọ ó sì yè.”
Jesu ń maadi o, “A jiini bonŋanla. Ya tie yeni, a baa ye ki fo.
29 Ṣùgbọ́n ó ń fẹ́ láti da ara rẹ̀ láre, ó wí fún Jesu wí pé, “Ta ha sì ni ẹnìkejì mi?”
Ama o tundka yeni den bua wan kuni obá i mɔni, ki buali Jesu, “ŋma n tie lielo?”
30 Jesu sì dáhùn ó wí pé, “Ọkùnrin kan ń ti Jerusalẹmu sọ̀kalẹ̀ lọ sí Jeriko, ó sì bọ́ sí ọwọ́ àwọn ọlọ́ṣà; wọ́n gbà á ní aṣọ, wọ́n sá a lọ́gbẹ́, wọ́n sì fi sílẹ̀ lọ ní àìpatán.
Ke Jesu jiini, “Nilo den ñani Jerusalema ki caa Jeriko, ki cendi bi sanjiaba, ke bi fie o tiadi kuli, ki pua ki janbi o, ke o nagni mi kuuma
31 Ní kòńgẹ́ àkókò yìí ni àlùfáà kan sì ń sọ̀kalẹ̀ lọ lọ́nà náà. Nígbà tí ó sì rí i ó kọjá lọ níhà kejì.
Li sua ke salga yidka kubi li sanu, ki ji, wan la o ja yeni, ke o jadi ki lɔgdi o, ki ban caa.
32 Bẹ́ẹ̀ náà sì ni ọmọ Lefi kan pẹ̀lú, nígbà tí ó dé ibẹ̀, tí ó sì rí i, ó kọjá lọ níhà kejì.
Lan go tieni yeni, Levi yua mo ń ya pendi, o mo ń la o, wan jadi, ki balni, ki pendi.
33 Ṣùgbọ́n ará Samaria kan, bí ó ti ń re àjò, ó dé ibi tí ó gbé wà; nígbà tí ó sì rí i, àánú ṣe é.
Ama, Samari yua n den caa u sanu, ki pudi o kani, Wan la o, o pali ń sia yeni ti niñinpadi.
34 Ó sì tọ̀ ọ́ lọ, ó sì di ọgbẹ́ rẹ̀, ó da òróró àti ọtí wáìnì sí i, ó sì gbé e lé orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ti òun tìkára rẹ̀, ó sì mú un wá sí ilé èrò, a sì ń ṣe ìtọ́jú rẹ̀.
Wan nagni, ki fiadi fiadi o nala, ki tieni mi kpama leni ku daamɔngu. Ki jagni o o ya ŋunbo po, ki ciani o ban gaani bi canba naani, ke bi kubi o lan buali maama.
35 Nígbà tí ó sì lọ ní ọjọ́ kejì, ó fi owó idẹ méjì fún olórí ilé èrò ó sì wí fún un pé, ‘Máa tọ́jú rẹ̀; ohunkóhun tí ìwọ bá sì ná kún un, nígbà tí mo bá padà dé, èmi ó san án fún ọ.’
Lan fandi, ke o ñani ligi lie ki teni o canguulo, ki maadi, “ŋan ŋanbi ki kubi lan buali maama. ligi ya pɔdi, ke a pugni yii kuli, N ya guani, N ba pa ŋa.
36 “Nínú àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta wọ̀nyí, ta ni ìwọ rò pé ó jẹ́ ẹnìkejì ẹni tí ó bọ́ sí ọwọ́ àwọn ọlọ́ṣà?”
Bani bonbtaa siiga yeni, a maali ke ole n tie o ja yua baa bi sanjiaba sanu nni yeni nisaalilielo?
37 Ó sì dáhùn wí pé, “Ẹni tí ó ṣàánú fún un ni.” Jesu sì wí fún un pé, “Lọ, kí o ṣe bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́!”
O tundka ń maadi, “Yua n gbadi o niñima yeni n tie o nisaalilielo.” Jesu ń maadi o, “Ya caa ki mo n ya tiendi yeni”
38 Ó sì ṣe, bí wọ́n ti ń lọ, o wọ ìletò kan, obìnrin kan tí a ń pè ní Marta sì gbà á sí ilé rẹ̀.
Ban paani u sanu ki caa, ke bi kua dogbiga bá ke li kani pua, ke bi yi o Marita biali o, ki mia ke wan tuo ki cani o deni.
39 Ó sì ní arábìnrin kan tí a ń pè ní Maria tí ó sì jókòó lẹ́bàá ẹsẹ̀ Olúwa, tí ó ń gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀.
O den pia o ninsalo ke o yi Maari. Ke o kali Jesu taana kani, ki cengi o maama.
40 Ṣùgbọ́n Marta ń ṣe ìyọnu ohun púpọ̀, ó sì tọ̀ ọ́ wá, ó wí pé, “Olúwa, ìwọ kò sì bìkítà sí ti arábìnrin mi pé ó fi mí sílẹ̀ láti máa nìkan ṣe ìránṣẹ́? Wí fún un kí ó ràn mí lọ́wọ́.”
Ama ke Marita gbaa leni a tuona, ki bua tieni mi bonjiema, wan nagni ki maadi Jesu, “O Diedo, ŋaa la ke n waalo ñɔli mini baba yeni a tuona aa? Lanwani, maadi o wan todi nni.”
41 Ṣùgbọ́n Olúwa sì dáhùn, ó sì wí fún un pé, “Marta, Marta, ìwọ ń ṣe àníyàn àti làálàá nítorí ohun púpọ̀.
Ama ke O Diedo jiini, ki maadi o “Marita, Marita a yagni a yama bona boncianli po,
42 Ṣùgbọ́n ohun kan ni a kò lè ṣe aláìní, Maria sì ti yan ipa rere náà tí a kò lè gbà lọ́wọ́ rẹ̀.”
Ama bonyenli baba n tie bonmɔnli, Mari lugdi yaali n ŋani ki cie, bi kan fidi ki fie la.”