< Luke 10 >

1 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí, Olúwa sì yan méjìléláàádọ́rin ọmọ-ẹ̀yìn mìíràn pẹ̀lú, ó sì rán wọn ní méjì méjì lọ ṣáájú rẹ̀, sí gbogbo ìlú àti ibi tí òun tìkára rẹ̀ yóò sì dé.
Boeipa loh a tloe sawmrhih panit a tuek tih, amih te amah hmai kah pha hamla a cai thil kho neh a hmuen takuem la panit panit ah a tueih.
2 Ó sì wí fún wọn pé, “Ìkórè pọ̀, ṣùgbọ́n àwọn alágbàṣe kò tó nǹkan, nítorí náà ẹ bẹ Olúwa ìkórè, kí ó lè rán àwọn alágbàṣe sínú ìkórè rẹ̀.
Te vaengah amih taengah, “Cangah hamla yet dae bibikung yool, te dongah cangah Boeipa taengah bih uh lamtah amah kah cangah hmuen ah bibikung han hlah saeh.
3 Ẹ mú ọ̀nà yín pọ̀n: sá wò ó, èmi rán yín lọ bí ọ̀dọ́-àgùntàn sáàrín ìkookò.
Cet uh, uithang lakli ah tuca bangla nangmih kan tueih coeng he.
4 Ẹ má ṣe mú àpò, ẹ má ṣe mú àpamọ́wọ́, tàbí bàtà: ẹ má sì ṣe kí ẹnikẹ́ni lọ́nà.
Sungkoi, sungsa neh khokhom khaw khuen uh boeh, longpueng ah hlang kuttu uh boeh.
5 “Ní ilékílé tí ẹ̀yin bá wọ̀, kí ẹ kọ́ wí pé, ‘Àlàáfíà fún ilé yìí!’
Im te na kun thil uh coeng atah lamhma la, 'He im khuiah ngaimongnah om saeh, 'ti na uh.
6 Bí ọmọ àlàáfíà bá sì wà níbẹ̀, àlàáfíà yín yóò bà lé e: ṣùgbọ́n bí kò bá sí, yóò tún padà sọ́dọ̀ yín.
Te ah te ngaimongnah kah a capa a om van atah nangmih kah ngaimongnah loh anih soah om ni. Te pawt koinih nangmih taengla koep ha bal bitni.
7 Ẹ dúró sínú ilé náà, kí ẹ máa jẹ, kí ẹ sì máa mu ohunkóhun tí wọ́n bá fi fún yín, nítorí ọ̀yà alágbàṣe tọ́ sí i. Ẹ má ṣe lọ láti ilé dé ilé.
Te dongah amah tekah im ah naeh uh, amih taengkah te ca uh lamtah ouh. Bibikung tah a thapang a dang hamla tueng pai. Im pakhat lamloh im pakhat la thoeih uh boeh.
8 “Ìlúkílùú tí ẹ̀yin bá wọ̀, tí wọ́n bá sì gbà yín, ẹ jẹ ohunkóhun tí a bá gbé ka iwájú yín.
Khopuei te na kun uh thil tih nangmih te n'doe uh atah na taengah han tawn te ca uh.
9 Ẹ sì mú àwọn aláìsàn tí ń bẹ nínú rẹ̀ láradá, kí ẹ sì wí fún wọn pé, ‘Ìjọba Ọlọ́run kù sí dẹ̀dẹ̀ sí yín!’
A khuikah tattloel te hoeih sak uh lamtah amih te, 'Pathen kah ram tah nangmih taengah yoei coeng,’ ti nah.
10 Ṣùgbọ́n ní ìlúkílùú tí ẹ̀yin bá sì wọ̀, tí wọn kò bá sì gbà yín, nígbà tí ẹ̀yin bá sì jáde ní ìgboro ìlú náà, kí ẹ̀yin sì wí pé,
Tedae khopuei te na kun thil uh vaengah nangmih te n'doe uh pawt atah toltung ah cet uh.
11 ‘Eruku ìlú yín tí ó kù sí wa lẹ́sẹ̀, a gbọ̀n ọ́n sílẹ̀ fún yín! Ṣùgbọ́n ẹ mọ èyí pé, ìjọba Ọlọ́run kù sí dẹ̀dẹ̀.’
Na khopuei lamkah loh kaimih kho dongah tangdik aka kap te nangmih kan khoek uh thil coeng, 'ti nauh. Tedae te nen te Pathen kah ram tah yoei coeng tila ming uh.
12 Ṣùgbọ́n mo wí fún yín, yóò sàn fún Sodomu ní ọjọ́ náà, ju fún ìlú náà lọ.
Nangmih taengah ka thui, tekah khohnin ah Sodom te tekah khopuei lakah a phoeng la om ni.
13 “Ègbé ni fún ìwọ, Korasini! Ègbé ni fún ìwọ Betisaida! Nítorí ìbá ṣe pé a ti ṣe iṣẹ́ agbára tí a ṣe nínú yín, ní Tire àti Sidoni, wọn ìbá ti ronúpìwàdà lọ́jọ́ pípẹ́ sẹ́yìn, wọn ìbá sì jókòó nínú aṣọ ọ̀fọ̀ àti nínú eérú.
Anunae nang Khorazim, anunae nang Bethsaida, nangmih ah thaomnah aka om te Tyre neh Sidon ah om koinih, tlamhni neh hmaiphu dongah ngol uh vetih yut uh dingrhae pawn ni.
14 Ṣùgbọ́n yóò sàn fún Tire àti Sidoni nígbà ìdájọ́ jù fún yín lọ.
Tedae laitloeknah khuiah Tyre neh Sidon te nangmih lakah a phoeng la om ni.
15 Àti ìwọ, Kapernaumu, a ó ha gbé ọ ga dé òkè ọ̀run? A ó rẹ̀ ọ́ sílẹ̀ dé isà òkú. (Hadēs g86)
Kapernaum nang te, vaan la na pomsang pawt nim? Tedae Hell la na cungpung bitni. (Hadēs g86)
16 “Ẹni tí ó bá gbọ́ tiyín, ó gbọ́ tèmi. Ẹni tí ó bá sì kọ̀ yín, ó kọ̀ mi. Ẹni tí ó bá sì kọ̀ mi, ó kọ ẹni tí ó rán mi.”
Nangmih taengah aka hnatun long tah kai ol a hnatun tih, nangmih aka hnawt long tah kai ni n'hnawt. Tedae kai aka hnawt long tah ka tueih hlang te khaw a hnawt,” a ti nah.
17 Àwọn àádọ́rin náà sì fi ayọ̀ padà, wí pé, “Olúwa, àwọn ẹ̀mí èṣù tilẹ̀ foríbalẹ̀ fún wa ní orúkọ rẹ.”
Sawmrhih panit tah omngaihnah neh mael uh tih, “Boeipa, nang ming nen tah rhaithae pataeng kaimih taengah boe a ngai uh coeng,” a ti uh.
18 Ó sì wí fún wọn pé, “Èmí rí Satani ṣubú bí mọ̀nàmọ́ná láti ọ̀run wá.
Te vaengah amih te, “Satan he vaan lamkah khophaa a tlak banglam ni ka hmuh.
19 Kíyèsi i, èmí fún yín ní àṣẹ láti tẹ ejò àti àkéekèe mọ́lẹ̀, àti lórí gbogbo agbára ọ̀tá, kò sì ṣí ohun kan bí ó ti wù tí ó ṣe, tí yóò pa yín lára.
Rhul neh saelkhui-ta-ai khaw, rhal kah thaomnah boeih khaw cawt thil hamla nangmih taengah saithainah kam paek he. Te dongah pakhat nen pataeng nangmih te n'thae sak loengloeng boel saeh.
20 Ṣùgbọ́n kí ẹ má ṣe yọ̀ nítorí èyí pé, àwọn ẹ̀mí ń foríbalẹ̀ fún yín; ṣùgbọ́n ẹ kúkú yọ̀, pé; a kọ̀wé orúkọ yín ní ọ̀run!”
Tedae mueihla loh nangmih taengah boe a ngai dongah he omngaih uh boeh, vaan ah na ming a tarhit dongah mah omngaih uh,” a ti nah.
21 Ní wákàtí kan náà Jesu yọ̀ nínú Ẹ̀mí mímọ́ ó sì wí pé, “Mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ, Baba, Olúwa ọ̀run àti ayé, pé, ìwọ pa nǹkan wọ̀nyí mọ́ kúrò lọ́dọ̀ àwọn ọlọ́gbọ́n àti amòye, ìwọ sì fi wọ́n hàn fún àwọn ọmọ ọwọ́. Bẹ́ẹ̀ ni, Baba, bẹ́ẹ̀ ni ó sá à yẹ ní ojú rẹ.
Amah te vaeng tue ah Mueihla Cim loh a hlampan sak tih, “A Pa, vaan neh diklai kah Boeipa namah te kan uem, lungming hlangcueih taengkah na phah tangtae te cahmang rhoek taengah a pumphoe pah. Te pai saeh, a pa, te ni na hmaiah kolonah la aka om.
22 “Ohun gbogbo ni a ti fi fún mi láti ọ̀dọ̀ Baba mi; kò sì ṣí ẹni tí ó mọ ẹni tí ọmọ jẹ́, bí kò ṣe Baba, àti ẹnikẹ́ni tí ó bá sì wu ọmọ láti fi í hàn fún.”
A cungkuem he a Pa loh kai taengah a tloeng. Pa mueh atah capa te unim ti khaw a ming moenih. Capa mueh atah pa te unim ti khaw a ming moenih. Amih taengah khaw capa loh pumphoe hamla a ngaih,” a ti nah.
23 Ó sì yípadà sí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ní apá kan. Ó ní, “Ìbùkún ni fún ojú tí ń rí ohun tí ẹ̀yin ń rí.
Te phoeiah amah te hnukbang rhoek taengla mael tih, “Na hmuh uh he na mik loh a hmuh dongah he a yoethen.
24 Nítorí mo wí fún yín, ọ̀pọ̀ àwọn wòlíì àti àwọn ọba ni ó ń fẹ́ láti rí ohun tí ẹ̀yin ń rí, wọn kò sì rí wọn, àti láti gbọ́ ohun tí ẹ̀yin ń gbọ́, wọn kò sì gbọ́ wọn.”
Nangmih ham ni ka thui, nangmih loh na hmuh uh he tonghma rhoek neh manghai rhoek loh hmuh ham muep a ngaih uh dae ana hmu uh pawh, na yaak uh he ana yaak lam khaw ana yaak uh moenih,” a ti nah.
25 Sì kíyèsi i amòfin kan dìde, ó ń dán an wò, ó ní, “Olùkọ́, kín ni èmi ó ṣe kí èmi lè jogún ìyè àìnípẹ̀kun?” (aiōnios g166)
Te vaengah olming pakhat tah Jesuh te noemcai ham tarha thoo tih, “Saya, balae ka saii vetih dungyan hingnah ka pang eh?,” a ti nah. (aiōnios g166)
26 Ó sì bi í pé, “Kí ni a kọ sínú ìwé òfin? Báwo ni ìwọ sì ti kà á?”
Te dongah Jesuh loh anih te, “Olkhueng dongah a daek te metlam na tae te?” a ti nah.
27 Ó sì dáhùn wí pé, “‘Kí ìwọ fi gbogbo àyà rẹ, àti gbogbo ọkàn rẹ, àti gbogbo agbára rẹ, àti gbogbo inú rẹ fẹ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ’; àti, ‘Ẹnìkejì rẹ bí ara rẹ.’”
Anih long khaw a doo tih, “Boeipa na Pathen te na thinko boeih, na hinglu boeih, na thadueng boeih, na kopoek boeih neh, na imben te khaw namah pum bangla na lungnah ni,” a ti nah.
28 Ó sì wí fún un pé, “Ìwọ́ dáhùn rere. Ṣe èyí, ìwọ ó sì yè.”
Te dongah anih te, “Buelh nan doo coeng, te te saii lamtah na hing bitni,” a ti nah.
29 Ṣùgbọ́n ó ń fẹ́ láti da ara rẹ̀ láre, ó wí fún Jesu wí pé, “Ta ha sì ni ẹnìkejì mi?”
Tedae anih long te amah a tang a ngaih dongah, Jesuh te, “Ka imben te unim,” a ti nah.
30 Jesu sì dáhùn ó wí pé, “Ọkùnrin kan ń ti Jerusalẹmu sọ̀kalẹ̀ lọ sí Jeriko, ó sì bọ́ sí ọwọ́ àwọn ọlọ́ṣà; wọ́n gbà á ní aṣọ, wọ́n sá a lọ́gbẹ́, wọ́n sì fi sílẹ̀ lọ ní àìpatán.
Jesuh loh a doo tih, “Hlang pakhat tah Jerusalem lamkah loh Jerikho la suntla dae dingca rhoek neh tonguh. Anih te a pit uh phoeiah lucik la a khuehuh. Te daengah a toeng uh tih duekhlong la a caeh tak uh.
31 Ní kòńgẹ́ àkókò yìí ni àlùfáà kan sì ń sọ̀kalẹ̀ lọ lọ́nà náà. Nígbà tí ó sì rí i ó kọjá lọ níhà kejì.
Tapkhoeh taploeng la khosoih pakhat tah tekah longpuei ah suntla tih anih te a hmuh dae a rhael.
32 Bẹ́ẹ̀ náà sì ni ọmọ Lefi kan pẹ̀lú, nígbà tí ó dé ibẹ̀, tí ó sì rí i, ó kọjá lọ níhà kejì.
Te vanbangla Levi khaw te hmuen kah aka om te a thoeng thil tih a hmuh dae a rhael bal.
33 Ṣùgbọ́n ará Samaria kan, bí ó ti ń re àjò, ó dé ibi tí ó gbé wà; nígbà tí ó sì rí i, àánú ṣe é.
Tedae Samaria yin pakhat loh anih te a thoeng thil tih a hmuh vaengah a thinphat.
34 Ó sì tọ̀ ọ́ lọ, ó sì di ọgbẹ́ rẹ̀, ó da òróró àti ọtí wáìnì sí i, ó sì gbé e lé orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ti òun tìkára rẹ̀, ó sì mú un wá sí ilé èrò, a sì ń ṣe ìtọ́jú rẹ̀.
Te dongah a paan tih a hma te a ben pah, situi, misurtui neh a toi pah. Te phoeiah anih te amah kah boiva dongah a ngol sak, rhaehim la a khuen tih, a cuncah.
35 Nígbà tí ó sì lọ ní ọjọ́ kejì, ó fi owó idẹ méjì fún olórí ilé èrò ó sì wí fún un pé, ‘Máa tọ́jú rẹ̀; ohunkóhun tí ìwọ bá sì ná kún un, nígbà tí mo bá padà dé, èmi ó san án fún ọ.’
A vuen ah tah denari panit te a loh tih imtawt te a paek. Te phoeiah, 'Anih he cuncah lamtah pakhat khaw na vak yet te tah ka mael vaengah nang te kan thuung bitni,” a ti nah.
36 “Nínú àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta wọ̀nyí, ta ni ìwọ rò pé ó jẹ́ ẹnìkejì ẹni tí ó bọ́ sí ọwọ́ àwọn ọlọ́ṣà?”
Te rhoek pathum khuiah dingca kut ah aka cungku kah imben la ulae aka om ni tila na poek?” a ti nah.
37 Ó sì dáhùn wí pé, “Ẹni tí ó ṣàánú fún un ni.” Jesu sì wí fún un pé, “Lọ, kí o ṣe bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́!”
Te vaengah anih long te, “A soah rhennah aka tueng sak te,” a ti nah. Te phoeiah amah te Jesuh loh, “Cet lamtah namah loh saii van,” a ti nah.
38 Ó sì ṣe, bí wọ́n ti ń lọ, o wọ ìletò kan, obìnrin kan tí a ń pè ní Marta sì gbà á sí ilé rẹ̀.
A caeh uh vaengah kho pakhat ah pah. Te vaengah huta pakhat, a ming ah Martha loh Jesuh te a doe.
39 Ó sì ní arábìnrin kan tí a ń pè ní Maria tí ó sì jókòó lẹ́bàá ẹsẹ̀ Olúwa, tí ó ń gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀.
Te vaengah a mana Mary la a khue te khaw om. Anih tah Boeipa kah kho taengah ngol van tih a ol te a hnatun.
40 Ṣùgbọ́n Marta ń ṣe ìyọnu ohun púpọ̀, ó sì tọ̀ ọ́ wá, ó wí pé, “Olúwa, ìwọ kò sì bìkítà sí ti arábìnrin mi pé ó fi mí sílẹ̀ láti máa nìkan ṣe ìránṣẹ́? Wí fún un kí ó ràn mí lọ́wọ́.”
Tedae Martha tah bibi dongah mat tok. Te dongah koe pai tih, “Boeipa, kai mana tah nang hamla a ngaihuet voel pawt tih kamah bueng he thohtat ham n'hnoo coeng. Te dongah anih te thui pah lamtah kai n'bom mai saeh,” a ti nah.
41 Ṣùgbọ́n Olúwa sì dáhùn, ó sì wí fún un pé, “Marta, Marta, ìwọ ń ṣe àníyàn àti làálàá nítorí ohun púpọ̀.
Tedae anih te Boeipa loh a doo tih, “Martha, Martha, muep na mawn tih na tom na ta mai.
42 Ṣùgbọ́n ohun kan ni a kò lè ṣe aláìní, Maria sì ti yan ipa rere náà tí a kò lè gbà lọ́wọ́ rẹ̀.”
Tedae pakhat a ngoe om, Mary loh buham then te a tuek coeng dongah anih kah he rhawt pa uh mahpawh,” a ti nah.

< Luke 10 >