< Luke 1 >

1 Ọ̀pọ̀ ènìyàn ni ó ti dáwọ́lé títo àwọn nǹkan wọ̀n-ọn-nì jọ lẹ́sẹẹsẹ, èyí tí ó ti múlẹ̀ ṣinṣin láàrín wa,
پْرَتھَمَتو یے ساکْشِنو واکْیَپْرَچارَکاشْچاسَنْ تےسْماکَں مَدھْیے یَدْیَتْ سَپْرَمانَں واکْیَمَرْپَیَنْتِ سْمَ
2 àní gẹ́gẹ́ bí àwọn ìránṣẹ́ ọ̀rọ̀ náà, tí ó ṣe ojú wọn láti ìbẹ̀rẹ̀ ti fi lé wa lọ́wọ́.
تَدَنُسارَتونْییپِ بَہَوَسْتَدْورِتّانْتَں رَچَیِتُں پْرَورِتّاح۔
3 Nítorí náà, ó sì yẹ fún èmi pẹ̀lú, láti kọ̀wé sí ọ lẹ́sẹẹsẹ bí mo ti wádìí ohun gbogbo fínní fínní sí láti ìpilẹ̀ṣẹ̀, Teofilu ọlọ́lá jùlọ,
اَتَایوَ ہے مَہامَہِمَتھِیَپھِلْ تْوَں یا یاح کَتھا اَشِکْشْیَتھاسْتاساں درِڈھَپْرَمانانِ یَتھا پْراپْنوشِ
4 kí ìwọ kí ó le mọ òtítọ́ ohun wọ̀n-ọn-nì, tí a ti kọ́ ọ.
تَدَرْتھَں پْرَتھَمَمارَبھْیَ تانِ سَرْوّانِ جْناتْواہَمَپِ اَنُکْرَماتْ سَرْوَّورِتّانْتانْ تُبھْیَں لیکھِتُں مَتِمَکارْشَمْ۔
5 Nígbà ọjọ́ Herodu ọba Judea, àlùfáà kan wà, láti ìran Abijah, orúkọ rẹ̀ a máa jẹ́ Sekariah: aya rẹ̀ sì ṣe ọ̀kan nínú àwọn ọmọbìnrin Aaroni, orúkọ rẹ̀ a sì máa jẹ́ Elisabeti.
یِہُودادیشِییَہیرودْنامَکے راجَتْوَں کُرْوَّتِ اَبِییَیاجَکَسْیَ پَرْیّایادھِکارِی سِکھَرِیَنامَکَ ایکو یاجَکو ہارونَوَںشودْبھَوا اِلِیشیواکھْیا
6 Àwọn méjèèjì sì ṣe olódodo níwájú Ọlọ́run, wọ́n ń rìn ní gbogbo òfin àti ìlànà Olúwa ní àìlẹ́gàn.
تَسْیَ جایا دْواوِمَو نِرْدوشَو پْرَبھوح سَرْوّاجْنا وْیَوَسْتھاشْچَ سَںمَنْیَ اِیشْوَرَدرِشْٹَو دھارْمِّکاواسْتامْ۔
7 Ṣùgbọ́n wọn kò ní ọmọ, nítorí tí Elisabeti yàgàn; àwọn méjèèjì sì di arúgbó.
تَیوح سَنْتانَ ایکوپِ ناسِیتْ، یَتَ اِلِیشیوا بَنْدھْیا تَو دْواویوَ ورِدّھاوَبھَوَتامْ۔
8 Ó sì ṣe, nígbà tí ó ń ṣe iṣẹ́ àlùfáà níwájú Ọlọ́run ni àkókò tirẹ̀.
یَدا سْوَپَرْیّانُکْرَمینَ سِکھَرِیَ اِیشْواسْیَ سَمَکْشَں یاجَکِییَں کَرْمَّ کَروتِ
9 Bí ìṣe àwọn àlùfáà, ipa tirẹ̀ ni láti máa fi tùràrí jóná, nígbà tí ó bá wọ inú tẹmpili Olúwa lọ.
تَدا یَجْنَسْیَ دِنَپَرِپایّا پَرَمیشْوَرَسْیَ مَنْدِرے پْرَویشَکالے دھُوپَجْوالَنَں کَرْمَّ تَسْیَ کَرَنِییَماسِیتْ۔
10 Gbogbo ìjọ àwọn ènìyàn sì ń gbàdúrà lóde ní àkókò sísun tùràrí.
تَدّھُوپَجْوالَنَکالے لوکَنِوَہے پْرارْتھَناں کَرْتُں بَہِسْتِشْٹھَتِ
11 Angẹli Olúwa kan sì fi ara hàn án, ó dúró ní apá ọ̀tún pẹpẹ tùràrí.
سَتِ سِکھَرِیو یَسْیاں ویدْیاں دھُوپَں جْوالَیَتِ تَدَّکْشِنَپارْشْوے پَرَمیشْوَرَسْیَ دُوتَ ایکَ اُپَسْتھِتو دَرْشَنَں دَدَو۔
12 Nígbà tí Sekariah sì rí i, orí rẹ̀ wú, ẹ̀rù sì bà á.
تَں درِشْٹْوا سِکھَرِیَ اُدْوِوِجے شَشَنْکے چَ۔
13 Ṣùgbọ́n angẹli náà wí fún un pé, “Má bẹ̀rù, Sekariah: nítorí tí àdúrà rẹ gbà; Elisabeti aya rẹ yóò sì bí ọmọkùnrin kan fún ọ, ìwọ ó sì sọ orúkọ rẹ̀ ní Johanu.
تَدا سَ دُوتَسْتَں بَبھاشے ہے سِکھَرِیَ ما بھَیسْتَوَ پْرارْتھَنا گْراہْیا جاتا تَوَ بھارْیّا اِلِیشیوا پُتْرَں پْرَسوشْیَتے تَسْیَ نامَ یوہَنْ اِتِ کَرِشْیَسِ۔
14 Òun yóò sì jẹ́ ayọ̀ àti ìdùnnú fún ọ, ènìyàn púpọ̀ yóò sì yọ̀ sí ìbí rẹ.
کِنْچَ تْوَں سانَنْدَح سَہَرْشَشْچَ بھَوِشْیَسِ تَسْیَ جَنْمَنِ بَہَوَ آنَنْدِشْیَنْتِ چَ۔
15 Nítorí òun ó pọ̀ níwájú Olúwa, kì yóò sì mu ọtí wáìnì, bẹ́ẹ̀ ni kì yóò sì mu ọtí líle; yóò sì kún fún Ẹ̀mí Mímọ́ àní láti inú ìyá rẹ̀ wá.
یَتو ہیتوح سَ پَرَمیشْوَرَسْیَ گوچَرے مَہانْ بھَوِشْیَتِ تَتھا دْراکْشارَسَں سُراں وا کِمَپِ نَ پاسْیَتِ، اَپَرَں جَنْمارَبھْیَ پَوِتْریناتْمَنا پَرِپُورْنَح
16 Òun ó sì yí ènìyàn púpọ̀ padà nínú àwọn ọmọ Israẹli sí Olúwa Ọlọ́run wọn.
سَنْ اِسْراییلْوَںشِییانْ اَنیکانْ پْرَبھوح پَرَمیشْوَرَسْیَ مارْگَمانیشْیَتِ۔
17 Ẹ̀mí àti agbára Elijah ni Olúwa yóò sì fi ṣáájú rẹ̀ lọ, láti pa ọkàn àwọn baba dà sí ti àwọn ọmọ, àti ti àwọn aláìgbọ́ràn sí ọgbọ́n àwọn olóòtítọ́; kí ó le pèsè àwọn ènìyàn tí a múra sílẹ̀ de Olúwa.”
سَنْتانانْ پْرَتِ پِترِناں مَناںسِ دھَرْمَّجْنانَں پْرَتْیَناجْناگْراہِنَشْچَ پَراوَرْتَّیِتُں، پْرَبھوح پَرَمیشْوَرَسْیَ سیوارْتھَمْ ایکاں سَجِّتَجاتِں وِدھاتُنْچَ سَ ایلِیَرُوپاتْمَشَکْتِپْراپْتَسْتَسْیاگْرے گَمِشْیَتِ۔
18 Sekariah sì wí fún angẹli náà pé, “Àmì wo ni èmi ó fi mọ èyí? Èmi sá ti di àgbà, àti Elisabeti aya mi sì di arúgbó.”
تَدا سِکھَرِیو دُوتَمَوادِیتْ کَتھَمیتَدْ ویتْسْیامِ؟ یَتوہَں ورِدّھو مَمَ بھارْیّا چَ ورِدّھا۔
19 Angẹli náà sì dáhùn ó wí fún un pé, “Èmi ni Gabrieli, tí máa ń dúró níwájú Ọlọ́run; èmi ni a rán wá láti sọ fún ọ, àti láti mú ìròyìn ayọ̀ wọ̀nyí fún ọ wá.
تَتو دُوتَح پْرَتْیُواچَ پَشْییشْوَرَسْیَ ساکْشادْوَرْتِّی جِبْراییلْناما دُوتوہَں تْوَیا سَہَ کَتھاں گَدِتُں تُبھْیَمِماں شُبھَوارْتّاں داتُنْچَ پْریشِتَح۔
20 Sì kíyèsi i, ìwọ ó yadi, ìwọ kì yóò sì le fọhùn, títí ọjọ́ náà tí nǹkan wọ̀nyí yóò fi ṣẹ, nítorí ìwọ kò gba ọ̀rọ̀ mi gbọ́ tí yóò ṣẹ ní àkókò wọn.”
کِنْتُ مَدِییَں واکْیَں کالے پھَلِشْیَتِ تَتْ تْوَیا نَ پْرَتِیتَمْ اَتَح کارَنادْ یاوَدیوَ تانِ نَ سیتْسْیَنْتِ تاوَتْ تْوَں وَکْتُںمَشَکْتو مُوکو بھَوَ۔
21 Àwọn ènìyàn sì ń dúró de Sekariah, ẹnu sì yà wọ́n nítorí tí ó pẹ́ nínú tẹmpili.
تَدانِیں یے یے لوکاح سِکھَرِیَمَپَیکْشَنْتَ تے مَدھْییمَنْدِرَں تَسْیَ بَہُوِلَمْبادْ آشْچَرْیَّں مینِرے۔
22 Nígbà tí ó sì jáde wá, òun kò le bá wọn sọ̀rọ̀. Wọn sì kíyèsi wí pé ó ti rí ìran nínú tẹmpili, ó sì ń ṣe àpẹẹrẹ sí wọn, nítorí tí ó yadi.
سَ بَہِراگَتو یَدا کِمَپِ واکْیَں وَکْتُمَشَکْتَح سَنْکیتَں کرِتْوا نِحشَبْدَسْتَسْیَو تَدا مَدھْییمَنْدِرَں کَسْیَچِدْ دَرْشَنَں تینَ پْراپْتَمْ اِتِ سَرْوّے بُبُدھِرے۔
23 Ó sì ṣe, nígbà tí ọjọ́ iṣẹ́ ìsìn rẹ̀ pé, ó lọ sí ilé rẹ̀.
اَنَنْتَرَں تَسْیَ سیوَنَپَرْیّایے سَمْپُورْنے سَتِ سَ نِجَگیہَں جَگامَ۔
24 Lẹ́yìn èyí ni Elisabeti aya rẹ̀ lóyún, ó sì fi ara rẹ̀ pamọ́ ní oṣù márùn-ún,
کَتِپَیَدِنیشُ گَتیشُ تَسْیَ بھارْیّا اِلِیشیوا گَرْبّھَوَتِی بَبھُووَ
25 Ó sì wí pé, “Báyìí ni Olúwa ṣe fún mi ní ọjọ́ tí ó síjú wò mí, láti mú ẹ̀gàn mi kúrò láàrín àwọn ènìyàn.”
پَشْچاتْ سا پَنْچَماسانْ سَںگوپْیاکَتھَیَتْ لوکاناں سَمَکْشَں مَماپَمانَں کھَنْڈَیِتُں پَرَمیشْوَرو مَیِ درِشْٹِں پاتَیِتْوا کَرْمّیدرِشَں کرِتَوانْ۔
26 Ní oṣù kẹfà Ọlọ́run sì rán angẹli Gabrieli sí ìlú kan ní Galili, tí à ń pè ní Nasareti,
اَپَرَنْچَ تَسْیا گَرْبّھَسْیَ شَشْٹھے ماسے جاتے گالِیلْپْرَدیشِییَناسَرَتْپُری
27 sí wúńdíá kan tí a ṣèlérí láti fẹ́ fún ọkùnrin kan, tí a ń pè ní Josẹfu, ti ìdílé Dafidi; orúkọ wúńdíá náà a sì máa jẹ́ Maria.
دایُودو وَںشِییایَ یُوشَپھْنامْنے پُرُشایَ یا مَرِیَمْنامَکُمارِی واگْدَتّاسِیتْ تَسْیاح سَمِیپَں جِبْراییلْ دُوتَ اِیشْوَرینَ پْرَہِتَح۔
28 Angẹli náà sì tọ̀ ọ́ wá, ó ní, “Àlàáfíà fun ọ, ìwọ ẹni tí a kọjú sí ṣe ní oore, Olúwa ń bẹ pẹ̀lú rẹ.”
سَ گَتْوا جَگادَ ہے اِیشْوَرانُگرِہِیتَکَنْیے تَوَ شُبھَں بھُویاتْ پْرَبھُح پَرَمیشْوَرَسْتَوَ سَہایوسْتِ نارِیناں مَدھْیے تْوَمیوَ دھَنْیا۔
29 Ṣùgbọ́n ọkàn Maria kò lélẹ̀ nítorí ọ̀rọ̀ náà, ó sì rò nínú ara rẹ̀ pé, irú kíkí kín ni èyí.
تَدانِیں سا تَں درِشْٹْوا تَسْیَ واکْیَتَ اُدْوِجْیَ کِیدرِشَں بھاشَنَمِدَمْ اِتِ مَنَسا چِنْتَیاماسَ۔
30 Ṣùgbọ́n angẹli náà wí fún un pé, “Má bẹ̀rù, Maria, nítorí ìwọ ti rí ojúrere lọ́dọ̀ Ọlọ́run.
تَتو دُوتووَدَتْ ہے مَرِیَمْ بھَیَں ماکارْشِیح، تْوَیِ پَرَمیشْوَرَسْیانُگْرَہوسْتِ۔
31 Ìwọ yóò lóyún nínú rẹ, ìwọ ó sì bí ọmọkùnrin kan, ìwọ ó sì pe orúkọ rẹ̀ ní Jesu.
پَشْیَ تْوَں گَرْبّھَں دھرِتْوا پُتْرَں پْرَسوشْیَسے تَسْیَ نامَ یِیشُرِتِ کَرِشْیَسِ۔
32 Òun ó pọ̀, ọmọ Ọ̀gá-ògo jùlọ ni a ó sì máa pè é, Olúwa Ọlọ́run yóò sì fi ìtẹ́ Dafidi baba rẹ̀ fún.
سَ مَہانْ بھَوِشْیَتِ تَتھا سَرْوّیبھْیَح شْریشْٹھَسْیَ پُتْرَ اِتِ کھْیاسْیَتِ؛ اَپَرَں پْرَبھُح پَرَمیشْوَرَسْتَسْیَ پِتُرْدایُودَح سِںہاسَنَں تَسْمَے داسْیَتِ؛
33 Yóò sì jẹ ọba lórí ilé Jakọbu títí láé; ìjọba rẹ̀ kì yóò sì ní ìpẹ̀kun.” (aiōn g165)
تَتھا سَ یاکُوبو وَںشوپَرِ سَرْوَّدا راجَتْوَں کَرِشْیَتِ، تَسْیَ راجَتْوَسْیانْتو نَ بھَوِشْیَتِ۔ (aiōn g165)
34 Nígbà náà ni Maria béèrè lọ́wọ́ angẹli náà pé, “Èyí yóò ha ti ṣe rí bẹ́ẹ̀, nígbà tí èmi kò tí ì mọ ọkùnrin.”
تَدا مَرِیَمْ تَں دُوتَں بَبھاشے ناہَں پُرُشَسَنْگَں کَرومِ تَرْہِ کَتھَمیتَتْ سَمْبھَوِشْیَتِ؟
35 Angẹli náà sì dáhùn ó sì wí fún un pé, “Ẹ̀mí Mímọ́ yóò tọ̀ ọ́ wá, agbára Ọ̀gá-ògo jùlọ yóò síji bò ọ́. Nítorí náà ohun mímọ́ tí a ó ti inú rẹ bí, Ọmọ Ọlọ́run ni a ó máa pè é.
تَتو دُوتوکَتھَیَتْ پَوِتْرَ آتْما تْواماشْرایِشْیَتِ تَتھا سَرْوَّشْریشْٹھَسْیَ شَکْتِسْتَووپَرِ چھایاں کَرِشْیَتِ تَتو ہیتوسْتَوَ گَرْبّھادْ یَح پَوِتْرَبالَکو جَنِشْیَتے سَ اِیشْوَرَپُتْرَ اِتِ کھْیاتِں پْراپْسْیَتِ۔
36 Sì kíyèsi i, Elisabeti ìbátan rẹ náà yóò sì ní ọmọkùnrin kan ní ògbólógbòó rẹ̀, èyí sì ni oṣù kẹfà fún ẹni tí à ń pè ní àgàn.
اَپَرَنْچَ پَشْیَ تَوَ جْناتِرِلِیشیوا یاں سَرْوّے بَنْدھْیامَوَدَنْ اِدانِیں سا وارْدّھَکْیے سَنْتانَمیکَں گَرْبّھےدھارَیَتْ تَسْیَ شَشْٹھَماسوبھُوتْ۔
37 Nítorí kò sí ohun tí Ọlọ́run kò le ṣe.”
کِمَپِ کَرْمَّ ناسادھْیَمْ اِیشْوَرَسْیَ۔
38 Maria sì dáhùn wí pé, “Wò ó ọmọ ọ̀dọ̀ Olúwa; kí ó rí fún mi gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ rẹ.” Angẹli náà sì fi í sílẹ̀ lọ.
تَدا مَرِیَمْ جَگادَ، پَشْیَ پْرَبھیرَہَں داسِی مَہْیَں تَوَ واکْیانُسارینَ سَرْوَّمیتَدْ گھَٹَتامْ؛ اَنَنَتَرَں دُوتَسْتَسْیاح سَمِیپاتْ پْرَتَسْتھے۔
39 Ní àkókò náà ni Maria sì dìde, ó lọ kánkán sí ilẹ̀ òkè, sí ìlú kan ní Judea;
اَتھَ کَتِپَیَدِناتْ پَرَں مَرِیَمْ تَسْماتْ پَرْوَّتَمَیَپْرَدیشِییَیِہُودایا نَگَرَمیکَں شِیگھْرَں گَتْوا
40 Ó sì wọ ilé Sekariah lọ ó sì kí Elisabeti.
سِکھَرِیَیاجَکَسْیَ گرِہَں پْرَوِشْیَ تَسْیَ جایامْ اِلِیشیواں سَمْبودھْیاوَدَتْ۔
41 Ó sì ṣe, nígbà tí Elisabeti gbọ́ kíkí Maria, ọlẹ̀ sọ nínú rẹ̀; Elisabeti sì kún fún Ẹ̀mí Mímọ́,
تَتو مَرِیَمَح سَمْبودھَنَواکْیے اِلِیشیوایاح کَرْنَیوح پْرَوِشْٹَماتْرے سَتِ تَسْیا گَرْبّھَسْتھَبالَکو نَنَرْتَّ۔ تَتَ اِلِیشیوا پَوِتْریناتْمَنا پَرِپُورْنا سَتِی
42 Ó sì ké ní ohùn rara, ó sì wí pé, “Alábùkún fún ni ìwọ nínú àwọn obìnrin, alábùkún fún sì ni ọmọ tí ìwọ yóò bí.
پْروچَّیرْگَدِتُماریبھے، یوشِتاں مَدھْیے تْوَمیوَ دھَنْیا، تَوَ گَرْبّھَسْتھَح شِشُشْچَ دھَنْیَح۔
43 Èéṣe tí èmi fi rí irú ojúrere yìí, tí ìyá Olúwa mi ìbá fi tọ̀ mí wá?
تْوَں پْرَبھورْماتا، مَمَ نِویشَنے تْوَیا چَرَناوَرْپِتَو، مَمادْیَ سَوبھاگْیَمیتَتْ۔
44 Sá wò ó, bí ohùn kíkí rẹ ti bọ́ sí mi ní etí, ọlẹ̀ sọ nínú mi fún ayọ̀.
پَشْیَ تَوَ واکْیے مَمَ کَرْنَیوح پْرَوِشْٹَماتْرے سَتِ مَمودَرَسْتھَح شِشُرانَنْدانْ نَنَرْتَّ۔
45 Alábùkún fún sì ni ẹni tí ó gbàgbọ́, nítorí nǹkan wọ̀nyí tí a ti sọ fún un láti ọ̀dọ̀ Olúwa wá yóò ṣẹ.”
یا سْتْرِی وْیَشْوَسِیتْ سا دھَنْیا، یَتو ہیتوسْتاں پْرَتِ پَرَمیشْوَروکْتَں واکْیَں سَرْوَّں سِدّھَں بھَوِشْیَتِ۔
46 Maria sì dáhùn, ó ní: “Ọkàn mi yin Olúwa lógo.
تَدانِیں مَرِیَمْ جَگادَ۔ دھَنْیَوادَں پَریشَسْیَ کَروتِ مامَکَں مَنَح۔
47 Ẹ̀mí mi sì yọ̀ sí Ọlọ́run Olùgbàlà mi.
مَماتْما تارَکیشے چَ سَمُلّاسَں پْرَگَچّھَتِ۔
48 Nítorí tí ó síjú wo ìwà ìrẹ̀lẹ̀ ọmọbìnrin ọ̀dọ̀ rẹ̀. Sá wò ó, láti ìsinsin yìí lọ gbogbo ìran ènìyàn ni yóò máa pè mí ní alábùkún fún.
اَکَروتْ سَ پْرَبھُ رْدُشْٹِں سْوَداسْیا دُرْگَتِں پْرَتِ۔ پَشْیادْیارَبھْیَ ماں دھَنْیاں وَکْشْیَنْتِ پُرُشاح سَدا۔
49 Nítorí ẹni tí ó ní agbára ti ṣe ohun tí ó tóbi fún mi; Mímọ́ sì ni orúkọ rẹ̀.
یَح سَرْوَّشَکْتِمانْ یَسْیَ ناماپِ چَ پَوِتْرَکَں۔ سَ ایوَ سُمَہَتْکَرْمَّ کرِتَوانْ مَنِّمِتَّکَں۔
50 Àánú rẹ̀ sì ń bẹ fún àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀, láti ìrandíran.
یے بِبھْیَتِ جَناسْتَسْماتْ تیشاں سَنْتانَپَںکْتِشُ۔ اَنُکَمْپا تَدِییا چَ سَرْوَّدَیوَ سُتِشْٹھَتِ۔
51 Ó ti fi agbára hàn ní apá rẹ̀; o ti tú àwọn onígbèéraga ká ní ìrònú ọkàn wọn.
سْوَباہُبَلَتَسْتینَ پْراکاشْیَتَ پَراکْرَمَح۔ مَنَحکُمَنْتْرَناسارْدّھَں وِکِیرْیَّنْتےبھِمانِنَح۔
52 Ó ti mú àwọn alágbára kúrò lórí ìtẹ́ wọn, o sì gbé àwọn onírẹ̀lẹ̀ lékè.
سِںہاسَنَگَتالّوکانْ بَلِنَشْچاوَروہْیَ سَح۔ پَدیشُوچّیشُ لوکاںسْتُ کْشُدْرانْ سَںسْتھاپَیَتْیَپِ۔
53 Ó ti fi ohun tí ó dára kún àwọn tí ebi ń pa ó sì rán àwọn ọlọ́rọ̀ padà ní òfo.
کْشُدھِتانْ مانَوانْ دْرَوْیَیرُتَّمَیح پَرِتَرْپْیَ سَح۔ سَکَلانْ دھَنِنو لوکانْ وِسرِجیدْ رِکْتَہَسْتَکانْ۔
54 Ó ti ran Israẹli ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ lọ́wọ́, ní ìrántí àánú rẹ̀;
اِبْراہِیمِ چَ تَدْوَںشے یا دَیاسْتِ سَدَیوَ تاں۔ سْمرِتْوا پُرا پِترِناں نو یَتھا ساکْشاتْ پْرَتِشْرُتَں۔ (aiōn g165)
55 sí Abrahamu àti àwọn ìran rẹ̀ láéláé, baba wa, àti bí ó ti sọ fún àwọn baba wa.” (aiōn g165)
اِسْراییلْسیوَکَسْتینَ تَتھوپَکْرِیَتے سْوَیَں۔۔
56 Maria sì jókòó tì Elisabeti níwọ̀n oṣù mẹ́ta, ó sì padà lọ sí ilé rẹ̀.
اَنَنْتَرَں مَرِیَمْ پْرایینَ ماسَتْرَیَمْ اِلِیشیوَیا سَہوشِتْوا وْیاگھُیَّ نِجَنِویشَنَں یَیَو۔
57 Nígbà tí ọjọ́ Elisabeti pé tí yóò bí; ó sì bí ọmọkùnrin kan.
تَدَنَنْتَرَمْ اِلِیشیوایاح پْرَسَوَکالَ اُپَسْتھِتے سَتِ سا پُتْرَں پْراسوشْٹَ۔
58 Àwọn aládùúgbò, àti àwọn ìbátan rẹ̀ gbọ́ bí Olúwa ti fi àánú ńlá hàn fún un, wọ́n sì bá a yọ̀.
تَتَح پَرَمیشْوَرَسْتَسْیاں مَہانُگْرَہَں کرِتَوانْ ایتَتْ شْرُتْوا سَمِیپَواسِنَح کُٹُمْباشْچاگَتْیَ تَیا سَہَ مُمُدِرے۔
59 Ó sì ṣe, ní ọjọ́ kẹjọ wọ́n wá láti kọ ọmọ náà nílà; wọ́n sì fẹ́ sọ orúkọ rẹ̀ ní Sekariah, gẹ́gẹ́ bí orúkọ baba rẹ̀.
تَتھاشْٹَمے دِنے تے بالَکَسْیَ تْوَچَں چھیتُّمْ ایتْیَ تَسْیَ پِترِنامانُرُوپَں تَنّامَ سِکھَرِیَ اِتِ کَرْتُّمِیشُح۔
60 Ìyá rẹ̀ sì dáhùn, ó ní, “Bẹ́ẹ̀ kọ́! Johanu ni a ó pè é.”
کِنْتُ تَسْیَ ماتاکَتھَیَتْ تَنَّ، ناماسْیَ یوہَنْ اِتِ کَرْتَّوْیَمْ۔
61 Wọ́n sì wí fún un pé, “Kò sí ọ̀kan nínú àwọn ará rẹ̀ tí à ń pè ní orúkọ yìí.”
تَدا تے وْیاہَرَنْ تَوَ وَںشَمَدھْیے نامیدرِشَں کَسْیاپِ ناسْتِ۔
62 Wọ́n sì ṣe àpẹẹrẹ sí baba rẹ̀, bí ó ti ń fẹ́ kí a pè é.
تَتَح پَرَں تَسْیَ پِتَرَں سِکھَرِیَں پْرَتِ سَنْکیتْیَ پَپْرَچّھُح شِشوح کِں نامَ کارِشْیَتے؟
63 Ó sì béèrè fún wàláà, ó sì kọ ọ wí pé, “Johanu ni orúkọ rẹ̀.” Ẹnu sì ya gbogbo wọn.
تَتَح سَ پھَلَکَمیکَں یاچِتْوا لِلیکھَ تَسْیَ نامَ یوہَنْ بھَوِشْیَتِ۔ تَسْماتْ سَرْوّے آشْچَرْیَّں مینِرے۔
64 Ẹnu rẹ̀ sì ṣí lọ́gán, okùn ahọ́n rẹ̀ sì tú, ó sì sọ̀rọ̀, ó sì ń yin Ọlọ́run.
تَتْکْشَنَں سِکھَرِیَسْیَ جِہْواجاڈْیےپَگَتے سَ مُکھَں وْیادایَ سْپَشْٹَوَرْنَمُچّارْیَّ اِیشْوَرَسْیَ گُنانُوادَں چَکارَ۔
65 Ẹ̀rù sì ba gbogbo àwọn tí ń bẹ ní agbègbè wọn, a sì ròyìn gbogbo nǹkan wọ̀nyí ká gbogbo ilẹ̀ òkè Judea.
تَسْماچَّتُرْدِکْسْتھاح سَمِیپَواسِلوکا بھِیتا ایوَمیتاح سَرْوّاح کَتھا یِہُودایاح پَرْوَّتَمَیَپْرَدیشَسْیَ سَرْوَّتْرَ پْرَچارِتاح۔
66 Ó sì jẹ́ ohun ìyanu fún gbogbo àwọn tí ó gbọ́ nípa rẹ̀, wọ́n sì tò ó sínú ọkàn wọn, wọ́n ń wí pé, “Irú-ọmọ kín ni èyí yóò jẹ́?” Nítorí tí ọwọ́ Olúwa wà pẹ̀lú rẹ̀.
تَسْماتْ شْروتارو مَنَحسُ سْتھاپَیِتْوا کَتھَیامْبَبھُووُح کِیدرِشویَں بالو بھَوِشْیَتِ؟ اَتھَ پَرَمیشْوَرَسْتَسْیَ سَہایوبھُوتْ۔
67 Sekariah baba rẹ̀ sì kún fún Ẹ̀mí Mímọ́, ó sì sọtẹ́lẹ̀, ó ní:
تَدا یوہَنَح پِتا سِکھَرِیَح پَوِتْریناتْمَنا پَرِپُورْنَح سَنْ ایتادرِشَں بھَوِشْیَدْواکْیَں کَتھَیاماسَ۔
68 “Olùbùkún ni Olúwa Ọlọ́run Israẹli; nítorí tí ó ti bojú wò, tí ó sì ti dá àwọn ènìyàn rẹ̀ nídè,
اِسْراییلَح پْرَبھُ رْیَسْتُ سَ دھَنْیَح پَرَمیشْوَرَح۔ اَنُگرِہْیَ نِجالّوکانْ سَ ایوَ پَرِموچَییتْ۔
69 Ó sì ti gbé ìwo ìgbàlà sókè fún wa ní ilé Dafidi ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀;
وِپَکْشَجَنَہَسْتیبھْیو یَتھا موچْیامَہے وَیَں۔ یاوَجِّیوَنْچَ دھَرْمّینَ سارَلْیینَ چَ نِرْبھَیاح۔
70 (bí ó ti sọtẹ́lẹ̀ láti ẹnu àwọn wòlíì rẹ̀ mímọ́ tipẹ́tipẹ́), (aiōn g165)
سیوامَہَے تَمیوَیکَمْ ایتَتْکارَنَمیوَ چَ۔ سْوَکِییَں سُپَوِتْرَنْچَ سَںسْمرِتْیَ نِیَمَں سَدا۔
71 Pé, a ó gbà wá là lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wa àti lọ́wọ́ àwọn tí ó kórìíra wá.
کرِپَیا پُرُشانْ پُورْوّانْ نِکَشارْتھاتُّ نَح پِتُح۔ اِبْراہِیمَح سَمِیپے یَں شَپَتھَں کرِتَوانْ پُرا۔
72 Láti ṣe àánú tí ó ṣèlérí fún àwọn baba wa, àti láti rántí májẹ̀mú rẹ̀ mímọ́,
تَمیوَ سَپھَلَں کَرْتَّں تَتھا شَتْرُگَنَسْیَ چَ۔ رِتِییاکارِنَشْچَیوَ کَریبھْیو رَکْشَنایَ نَح۔
73 ìbúra tí ó ti bú fún Abrahamu baba wa,
سرِشْٹیح پْرَتھَمَتَح سْوِییَیح پَوِتْرَے رْبھاوِوادِبھِح۔ (aiōn g165)
74 láti gbà wá lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wa, kí àwa kí ó lè máa sìn láìfòyà,
یَتھوکْتَوانْ تَتھا سْوَسْیَ دایُودَح سیوَکَسْیَ تُ۔
75 ni ìwà mímọ́ àti ní òdodo níwájú rẹ̀, ní ọjọ́ ayé wa gbogbo.
وَںشے تْراتارَمیکَں سَ سَمُتْپادِتَوانْ سْوَیَمْ۔
76 “Àti ìwọ, ọmọ mi, wòlíì Ọ̀gá-ògo jùlọ ni a ó máa pè ọ́: nítorí ìwọ ni yóò ṣáájú Olúwa láti tún ọ̀nà rẹ̀ ṣe;
اَتو ہے بالَکَ تْوَنْتُ سَرْوّیبھْیَح شْریشْٹھَ ایوَ یَح۔ تَسْیَیوَ بھاوِوادِیتِ پْرَوِکھْیاتو بھَوِشْیَسِ۔ اَسْماکَں چَرَنانْ کْشیمے مارْگے چالَیِتُں سَدا۔ ایوَں دھْوانْتےرْتھَتو مرِتْیوشْچھایایاں یے تُ مانَواح۔
77 láti fi ìmọ̀ ìgbàlà fún àwọn ènìyàn rẹ̀ fún ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ wọn,
اُپَوِشْٹاسْتُ تانیوَ پْرَکاشَیِتُمیوَ ہِ۔ کرِتْوا مَہانُکَمْپاں ہِ یامیوَ پَرَمیشْوَرَح۔
78 nítorí ìyọ́nú Ọlọ́run wà; nípa èyí tí ìlà-oòrùn láti òkè wá bojú wò wá,
اُورْدْوّاتْ سُورْیَّمُدایَّیواسْمَبھْیَں پْراداتُّ دَرْشَنَں۔ تَیانُکَمْپَیا سْوَسْیَ لوکاناں پاپَموچَنے۔
79 Láti fi ìmọ́lẹ̀ fún àwọn tí ó jókòó ní òkùnkùn àti ní òjìji ikú, àti láti fi ẹsẹ̀ wa lé ọ̀nà àlàáfíà.”
پَرِتْرانَسْیَ تیبھْیو ہِ جْنانَوِشْرانَنایَ چَ۔ پْرَبھو رْمارْگَں پَرِشْکَرْتُّں تَسْیاگْرایِی بھَوِشْیَسِ۔۔
80 Ọmọ náà sì dàgbà, ó sì le ní ọkàn, ó sì ń gbé ní ijù títí ó fi di ọjọ́ ìfihàn rẹ̀ fún Israẹli.
اَتھَ بالَکَح شَرِیرینَ بُدّھیا چَ وَرْدّھِتُماریبھے؛ اَپَرَنْچَ سَ اِسْراییلو وَںشِییَلوکاناں سَمِیپے یاوَنَّ پْرَکَٹِیبھُوتَسْتاسْتاوَتْ پْرانْتَرے نْیَوَسَتْ۔

< Luke 1 >