< Luke 1 >

1 Ọ̀pọ̀ ènìyàn ni ó ti dáwọ́lé títo àwọn nǹkan wọ̀n-ọn-nì jọ lẹ́sẹẹsẹ, èyí tí ó ti múlẹ̀ ṣinṣin láàrín wa,
Ka kum šćijec mulc su apukat să skriji događajur šje Dimizov u obečalit a su dogodulit ăntri noj.
2 àní gẹ́gẹ́ bí àwọn ìránṣẹ́ ọ̀rọ̀ náà, tí ó ṣe ojú wọn láti ìbẹ̀rẹ̀ ti fi lé wa lọ́wọ́.
Orikic as re svedoci dăm kap dă šje ur skris šje ur văzut šă šje svite Isus, jej ăs slugurlje alu vorba.
3 Nítorí náà, ó sì yẹ fún èmi pẹ̀lú, láti kọ̀wé sí ọ lẹ́sẹẹsẹ bí mo ti wádìí ohun gbogbo fínní fínní sí láti ìpilẹ̀ṣẹ̀, Teofilu ọlọ́lá jùlọ,
Aša šă ju mam ăngănđit dăm elši pă rănd să skruv kutotu păntru činji, glavni Teofile.
4 kí ìwọ kí ó le mọ òtítọ́ ohun wọ̀n-ọn-nì, tí a ti kọ́ ọ.
Aša să fij siguran šă să poc arăta šă să spuj dă ănkriđală dă vorbilje dă šje u fost ănvăcat kă ăj aje anume.
5 Nígbà ọjọ́ Herodu ọba Judea, àlùfáà kan wà, láti ìran Abijah, orúkọ rẹ̀ a máa jẹ́ Sekariah: aya rẹ̀ sì ṣe ọ̀kan nínú àwọn ọmọbìnrin Aaroni, orúkọ rẹ̀ a sì máa jẹ́ Elisabeti.
Ăm zăljiljelje kănd kralj Herod vladale ăm Judeja, are unu popă šje să čima Zaharija dăm svečenički rodu alu Abiji, šă mujere aluj isto are dăm pleme alu Aron. Je să čima Elizabeta.
6 Àwọn méjèèjì sì ṣe olódodo níwájú Ọlọ́run, wọ́n ń rìn ní gbogbo òfin àti ìlànà Olúwa ní àìlẹ́gàn.
Amăndoj ăs re ăm oči alu Dimizov făr dă duvină, pravedni kă jej cănje toći zapovjedurlje šă pravilurlje alu Domnu anostru.
7 Ṣùgbọ́n wọn kò ní ọmọ, nítorí tí Elisabeti yàgàn; àwọn méjèèjì sì di arúgbó.
Jej asre făr dă kupij, daje kă Elizabeta nu puće să ajvi kupij, šă amăndoj asre tari bătărnj.
8 Ó sì ṣe, nígbà tí ó ń ṣe iṣẹ́ àlùfáà níwájú Ọlọ́run ni àkókò tirẹ̀.
Kănd una ză, Zaharija služule ka popa alu Dimizov ăm Hram, u vinjit vreme pă grupa aluj să služulaskă.
9 Bí ìṣe àwọn àlùfáà, ipa tirẹ̀ ni láti máa fi tùràrí jóná, nígbà tí ó bá wọ inú tẹmpili Olúwa lọ.
Dă pă običaju ăntri pop lu izabralit ku kockă să mergă ăm svetište alu Domnu să prinusulaskă miomirosur.
10 Gbogbo ìjọ àwọn ènìyàn sì ń gbàdúrà lóde ní àkókò sísun tùràrí.
Šă ăntreg narodu aščipta afară ăm udvar šă să aruga ăm vreme dă mirosur.
11 Angẹli Olúwa kan sì fi ara hàn án, ó dúró ní apá ọ̀tún pẹpẹ tùràrí.
Atunšje anđalu alu Domnu su năstămit ăm Hram alu Zahariji dădănenći pă desna parći dă žrtvenik hunđi are miomiris.
12 Nígbà tí Sekariah sì rí i, orí rẹ̀ wú, ẹ̀rù sì bà á.
Zaharija kănd u văzut pă anđal tari su ănfrikušatăsă.
13 Ṣùgbọ́n angẹli náà wí fún un pé, “Má bẹ̀rù, Sekariah: nítorí tí àdúrà rẹ gbà; Elisabeti aya rẹ yóò sì bí ọmọkùnrin kan fún ọ, ìwọ ó sì sọ orúkọ rẹ̀ ní Johanu.
Daje anđalu ju zăs: “Nuči sprije, Zaharija! Arugală ata u fost auzătă. Mujere ata Elizabeta u ave fišjor, šă tu vi da numi Ivan.
14 Òun yóò sì jẹ́ ayọ̀ àti ìdùnnú fún ọ, ènìyàn púpọ̀ yóò sì yọ̀ sí ìbí rẹ.
Vi ave fălušăje šă slavlje šă mulc sur ăm făluša la fătala aluj.
15 Nítorí òun ó pọ̀ níwájú Olúwa, kì yóò sì mu ọtí wáìnì, bẹ́ẹ̀ ni kì yóò sì mu ọtí líle; yóò sì kún fún Ẹ̀mí Mímọ́ àní láti inú ìyá rẹ̀ wá.
Kă jăl anume u fi mari ăm oči lu Domnu anostru. Vin šă tari butură no be. Mar ăm injima alu mumăsa jăl u fi umpljet ku Duhu Svănt.
16 Òun ó sì yí ènìyàn púpọ̀ padà nínú àwọn ọmọ Israẹli sí Olúwa Ọlọ́run wọn.
Mulc fišjori kari ăs Izraelci sur ăntoršji dă rănd dă la jăl ăm napoj la Domnu Dimizovu alor.
17 Ẹ̀mí àti agbára Elijah ni Olúwa yóò sì fi ṣáájú rẹ̀ lọ, láti pa ọkàn àwọn baba dà sí ti àwọn ọmọ, àti ti àwọn aláìgbọ́ràn sí ọgbọ́n àwọn olóòtítọ́; kí ó le pèsè àwọn ènìyàn tí a múra sílẹ̀ de Olúwa.”
Jăl u meržji ăm nenće alu Domnu ka vjesniku ăm duhu šă ăm pučere alu Ilija kari are dă kănva prorok să pomirilaskă pă kupiji ku tatusurlje, să ăntorkă pă eje kari ăs nevjerni să apušji mudrost dă la heje kari ăs pravednă, să pripremalaskă narod păntru Domnu.”
18 Sekariah sì wí fún angẹli náà pé, “Àmì wo ni èmi ó fi mọ èyí? Èmi sá ti di àgbà, àti Elisabeti aya mi sì di arúgbó.”
Ali u zăs Zaharija alu anđalu Gabrijel kari stăće ăm nenče alu Dimizov: “Dă pă šje uj šči kă aje ăj anume? Tu vejs kă mes aku om bătărn šă băšăca ame ăj isto ăm aj.”
19 Angẹli náà sì dáhùn ó wí fún un pé, “Èmi ni Gabrieli, tí máa ń dúró níwájú Ọlọ́run; èmi ni a rán wá láti sọ fún ọ, àti láti mú ìròyìn ayọ̀ wọ̀nyí fún ọ wá.
Anđalu ju ăntors vorba: “Numilje amnjov ăj Gabrijel šă ju mes ku Dimizov să askultă šje mu spunji, aša mes mănat să svitesk ku činji šă săc aduk Hir fălos.
20 Sì kíyèsi i, ìwọ ó yadi, ìwọ kì yóò sì le fọhùn, títí ọjọ́ náà tí nǹkan wọ̀nyí yóò fi ṣẹ, nítorí ìwọ kò gba ọ̀rọ̀ mi gbọ́ tí yóò ṣẹ ní àkókò wọn.”
Punji mă ureći, kănd mar nu maj ănkrizut dă vorbasta šje cam spusu, tu njimika nu vi puće sviti păn šje no su dogoduli asta šje cam spus. Vorbilje šje cam spus ur fi ăm pravă vremi.”
21 Àwọn ènìyàn sì ń dúró de Sekariah, ẹnu sì yà wọ́n nítorí tí ó pẹ́ nínú tẹmpili.
Lume aščipta afară pă Zaharija, šă să čudule šje fašji atita dobă ăm svetište.
22 Nígbà tí ó sì jáde wá, òun kò le bá wọn sọ̀rọ̀. Wọn sì kíyèsi wí pé ó ti rí ìran nínú tẹmpili, ó sì ń ṣe àpẹẹrẹ sí wọn, nítorí tí ó yadi.
Kănd u vinjit afară nu puće să svitaskă. Jăl svite ăm znakovur šă nu puće să svitaskă njimika păn šje nu ju su ave kupilu. Šă atunšje ur prišjepi kă u avut vizijă ăm svetište.
23 Ó sì ṣe, nígbà tí ọjọ́ iṣẹ́ ìsìn rẹ̀ pé, ó lọ sí ilé rẹ̀.
Kănd u završălit vreme dă služba aluj ăm Hram, Zaharija u fužjit akasă.
24 Lẹ́yìn èyí ni Elisabeti aya rẹ̀ lóyún, ó sì fi ara rẹ̀ pamọ́ ní oṣù márùn-ún,
Atunšje maj dă pă zăljilje băšăca aluj u rămas gărjonă, šă nu jăšă afară šinšj lunj. Elizabeta u zăs:
25 Ó sì wí pé, “Báyìí ni Olúwa ṣe fún mi ní ọjọ́ tí ó síjú wò mí, láti mú ẹ̀gàn mi kúrò láàrín àwọn ènìyàn.”
“Domnu ăj ala kari u făkut asta aku: Dimizov su ujtat pă minji ku milă šă u lot ăndărăt rušănje dăm oči alu ominj.”
26 Ní oṣù kẹfà Ọlọ́run sì rán angẹli Gabrieli sí ìlú kan ní Galili, tí à ń pè ní Nasareti,
Šasă lunj dă kănd Elizabeta are gărjonă, Dimizov u mănat pă anđalu aluj păšći Gabrijel ăm varuš ăm Galileja kari să čamă Nazaret.
27 sí wúńdíá kan tí a ṣèlérí láti fẹ́ fún ọkùnrin kan, tí a ń pè ní Josẹfu, ti ìdílé Dafidi; orúkọ wúńdíá náà a sì máa jẹ́ Maria.
Jăl u vinjit la fată ăm păr kă su zaručulit ku Josip kari are potomku alu Kralju David. Je să čima Marija.
28 Angẹli náà sì tọ̀ ọ́ wá, ó ní, “Àlàáfíà fun ọ, ìwọ ẹni tí a kọjú sí ṣe ní oore, Olúwa ń bẹ pẹ̀lú rẹ.”
Gabrijel u vinjit šă u zăs: “Ănfălušešćići tu kari ješć izabralită! Domnu ăj ku činji! Blagoslovulită ješć tu ăntri mujer!”
29 Ṣùgbọ́n ọkàn Maria kò lélẹ̀ nítorí ọ̀rọ̀ náà, ó sì rò nínú ara rẹ̀ pé, irú kíkí kín ni èyí.
Marija are uznemirenă dă pozdravu aluj šă je u ănšjirkat să să ăngănđaskă šje značalešći.
30 Ṣùgbọ́n angẹli náà wí fún un pé, “Má bẹ̀rù, Maria, nítorí ìwọ ti rí ojúrere lọ́dọ̀ Ọlọ́run.
Anđalu ju zăs alji: “Nuc fijă frikă, Marija! Tu aj aflat la Dimizov milă.
31 Ìwọ yóò lóyún nínú rẹ, ìwọ ó sì bí ọmọkùnrin kan, ìwọ ó sì pe orúkọ rẹ̀ ní Jesu.
Punji ureći, vi rămănje gărjonă, vi făta fišjoru šă tu ji punji numi Isus!
32 Òun ó pọ̀, ọmọ Ọ̀gá-ògo jùlọ ni a ó sì máa pè é, Olúwa Ọlọ́run yóò sì fi ìtẹ́ Dafidi baba rẹ̀ fún.
Jăl u fi mari, šă u fi čimat Fišjoru lu Hăl Maj Mari! Šă Domnu Dimizov ju da autoritet să vladalaskă ka kralju ka kum ăj predaku aluj David.
33 Yóò sì jẹ ọba lórí ilé Jakọbu títí láé; ìjọba rẹ̀ kì yóò sì ní ìpẹ̀kun.” (aiōn g165)
Šă jăl u vladalit ăm familija lu Jakov dă erikeš, šă kraljevstva aluj nu ave kraj!” (aiōn g165)
34 Nígbà náà ni Maria béèrè lọ́wọ́ angẹli náà pé, “Èyí yóò ha ti ṣe rí bẹ́ẹ̀, nígbà tí èmi kò tí ì mọ ọkùnrin.”
Marija u ăntribat atunšje pă anđal: “Kum poći asta fi kă ju mes fată ăm păr!”
35 Angẹli náà sì dáhùn ó sì wí fún un pé, “Ẹ̀mí Mímọ́ yóò tọ̀ ọ́ wá, agbára Ọ̀gá-ògo jùlọ yóò síji bò ọ́. Nítorí náà ohun mímọ́ tí a ó ti inú rẹ bí, Ọmọ Ọlọ́run ni a ó máa pè é.
Anđalu ju ăntors vorba: “Duhu Svănt u vinji pă činji, šă pučere dă Hăl Maj Mari ću astupa ku umbră. Dăm ala rănd Kupilu Svănt šje u fi fătat dă la činji u fi čimat Fišjoru alu Dimizov.
36 Sì kíyèsi i, Elisabeti ìbátan rẹ náà yóò sì ní ọmọkùnrin kan ní ògbólógbòó rẹ̀, èyí sì ni oṣù kẹfà fún ẹni tí à ń pè ní àgàn.
Punji ureči: Rođakinja asta Elizabeta ăj bătărnă šă isto u ave fišjor, kă je nu puće să ajvi majmult, ali aku ăj mar ăm šasă lunj dă kănd ăj gărjonă.
37 Nítorí kò sí ohun tí Ọlọ́run kò le ṣe.”
Kă njimika nuj nemoguće alu Dimizov!”
38 Maria sì dáhùn wí pé, “Wò ó ọmọ ọ̀dọ̀ Olúwa; kí ó rí fún mi gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ rẹ.” Angẹli náà sì fi í sílẹ̀ lọ.
Atunšje u zăs Marija: “Da ju mă ligizesk ku asta să fjuv ropkinja alu Domnu. Lasă fijă aša kum tu zăšj.” Atunšje anđalu u fužjit dă la je.
39 Ní àkókò náà ni Maria sì dìde, ó lọ kánkán sí ilẹ̀ òkè, sí ìlú kan ní Judea;
Dovă tri zălji dă pă aje Marija su gătat šă u mers pă kalji, je su ăngribit ăm unu sat ăm Judeja pă đal.
40 Ó sì wọ ilé Sekariah lọ ó sì kí Elisabeti.
Akulo are kasa lu Zaharija. Je u tunat ăm nontru šă su pozdravalit ku Elizabeta.
41 Ó sì ṣe, nígbà tí Elisabeti gbọ́ kíkí Maria, ọlẹ̀ sọ nínú rẹ̀; Elisabeti sì kún fún Ẹ̀mí Mímọ́,
Kum u auzăt Elizabeta pozdravu lu Marija u sămcăt pă kupilu alji kum tari su miškat ăm injimă, šă Elizabeta are pljină ku Duhu Svănt.
42 Ó sì ké ní ohùn rara, ó sì wí pé, “Alábùkún fún ni ìwọ nínú àwọn obìnrin, alábùkún fún sì ni ọmọ tí ìwọ yóò bí.
Elizabeta tari u mužjit lu Marija: “Maj tari ješć blagoslovulită tu ăntri mujer, šă blagoslovulită ăj kupilu atov!
43 Èéṣe tí èmi fi rí irú ojúrere yìí, tí ìyá Olúwa mi ìbá fi tọ̀ mí wá?
Adišje mes aša bitnă, kă tu mama lu Domnu amnjov vinji să mă posjetilaskă?
44 Sá wò ó, bí ohùn kíkí rẹ ti bọ́ sí mi ní etí, ọlẹ̀ sọ nínú mi fún ayọ̀.
Kă dăm momentu šje am auzăt pozdravalala ata, kupilu amnjov tari su miškat dă fălušăjă ăm injima ame!
45 Alábùkún fún sì ni ẹni tí ó gbàgbọ́, nítorí nǹkan wọ̀nyí tí a ti sọ fún un láti ọ̀dọ̀ Olúwa wá yóò ṣẹ.”
Blagoslovljenă daje kă tu aj ănkrizut kă šje Domnu cu igirit sigurno u fi!”
46 Maria sì dáhùn, ó ní: “Ọkàn mi yin Olúwa lógo.
Atunšje Marija u zăs: “Duša ame ăl slavalešći pă maj mari Domn,
47 Ẹ̀mí mi sì yọ̀ sí Ọlọ́run Olùgbàlà mi.
šă duhu amnjov să ănfălušešći ăm Dimizov Spasitelju amnjov,
48 Nítorí tí ó síjú wo ìwà ìrẹ̀lẹ̀ ọmọbìnrin ọ̀dọ̀ rẹ̀. Sá wò ó, láti ìsinsin yìí lọ gbogbo ìran ènìyàn ni yóò máa pè mí ní alábùkún fún.
daje kă jăl su ujtat ku milă pă minji pă poniznă ropkinja aluj, aku toći generacijurlje mur čimamă blagoslovljenă,
49 Nítorí ẹni tí ó ní agbára ti ṣe ohun tí ó tóbi fún mi; Mímọ́ sì ni orúkọ rẹ̀.
daje kă svemogući Dimizov u făkut mari djelur ku minji, šă numilje aluj ăj svănt.
50 Àánú rẹ̀ sì ń bẹ fún àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀, láti ìrandíran.
Pălăngă totă sămănca, Dimizov ăj milos pălăngă eje kari ăl poštivalešći.
51 Ó ti fi agbára hàn ní apá rẹ̀; o ti tú àwọn onígbèéraga ká ní ìrònú ọkàn wọn.
Ku mănă aluj jăl u făkut pučernjišji lukrur. Jăl u arunkat afară pă eje kari asre ponosnă ăm sufljičilje alor šă pă eje kari asre umišljeni.
52 Ó ti mú àwọn alágbára kúrò lórí ìtẹ́ wọn, o sì gbé àwọn onírẹ̀lẹ̀ lékè.
Pă heje bălour vladar lju vărlji dă pă prijestolje, a pă heje kari ăs ponizni lju riđikatulji.
53 Ó ti fi ohun tí ó dára kún àwọn tí ebi ń pa ó sì rán àwọn ọlọ́rọ̀ padà ní òfo.
U rănjit pă flămănž ku mănkari bună, a pă găzdašji lju măna ku mănjilje golji.
54 Ó ti ran Israẹli ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ lọ́wọ́, ní ìrántí àánú rẹ̀;
Jăl u ažutat pă Izrael sluga aluj su ăngănđitusă dă milă aluj,
55 sí Abrahamu àti àwọn ìran rẹ̀ láéláé, baba wa, àti bí ó ti sọ fún àwọn baba wa.” (aiōn g165)
ka kum u obečalit alu preci anoštri dă kănva să fijă pljinj dă milă pălăngă Abraham šă pălăngă potomku aluj dă erikeš.” (aiōn g165)
56 Maria sì jókòó tì Elisabeti níwọ̀n oṣù mẹ́ta, ó sì padà lọ sí ilé rẹ̀.
Marija u rămas ku Elizabeta tri lunj atunšje su ăntorsăsă akasă.
57 Nígbà tí ọjọ́ Elisabeti pé tí yóò bí; ó sì bí ọmọkùnrin kan.
Kănd u vinjit vreme alu Elizabeti să ajvi kupil, je u fătat fišjor.
58 Àwọn aládùúgbò, àti àwọn ìbátan rẹ̀ gbọ́ bí Olúwa ti fi àánú ńlá hàn fún un, wọ́n sì bá a yọ̀.
Šă kănd ur auzăt susjedi šă njamu kă Domnu are bun pălăngă je, jej ur vinjit una la je šă să ăm făluše ku je una.
59 Ó sì ṣe, ní ọjọ́ kẹjọ wọ́n wá láti kọ ọmọ náà nílà; wọ́n sì fẹ́ sọ orúkọ rẹ̀ ní Sekariah, gẹ́gẹ́ bí orúkọ baba rẹ̀.
Kupilu trăbuje să fijă obrezalit pă optă (8) zuva, šă kănd or vinjit una să fakă asta, jej gănđe să ăj đe numi Zaharija dă pă tatusu.
60 Ìyá rẹ̀ sì dáhùn, ó ní, “Bẹ́ẹ̀ kọ́! Johanu ni a ó pè é.”
Mumăsa u odbijilit šă u zăs: “Nu, jăl su čima Ivan.”
61 Wọ́n sì wí fún un pé, “Kò sí ọ̀kan nínú àwọn ará rẹ̀ tí à ń pè ní orúkọ yìí.”
Ali jej ur zăs: “Njime dăm njamuc nu u fost čimat dă pă numiljala!”
62 Wọ́n sì ṣe àpẹẹrẹ sí baba rẹ̀, bí ó ti ń fẹ́ kí a pè é.
Šă aša jej ăntriba ku znakur pă tatusu alu kupilula, kum su čima.
63 Ó sì béèrè fún wàláà, ó sì kọ ọ wí pé, “Johanu ni orúkọ rẹ̀.” Ẹnu sì ya gbogbo wọn.
Zaharija u šjirut pločică dă skris šă u skris: “Ivan ăj numilje aluj!” Toc asre ămirac.
64 Ẹnu rẹ̀ sì ṣí lọ́gán, okùn ahọ́n rẹ̀ sì tú, ó sì sọ̀rọ̀, ó sì ń yin Ọlọ́run.
Šă dăm ala šas Dimizov u dăsvăkut gura alu Zaharija šă poći să svitaskă. Šă jăl dăđe slavă alu Dimizov!
65 Ẹ̀rù sì ba gbogbo àwọn tí ń bẹ ní agbègbè wọn, a sì ròyìn gbogbo nǹkan wọ̀nyí ká gbogbo ilẹ̀ òkè Judea.
Atunšje frika u vinjit pă tot susjedu šă ăm totă parće dă Judeja păm đalur šă spunje šje su dogodulit.
66 Ó sì jẹ́ ohun ìyanu fún gbogbo àwọn tí ó gbọ́ nípa rẹ̀, wọ́n sì tò ó sínú ọkàn wọn, wọ́n ń wí pé, “Irú-ọmọ kín ni èyí yóò jẹ́?” Nítorí tí ọwọ́ Olúwa wà pẹ̀lú rẹ̀.
Toc kari ur auzăt dă aje cănje ăm firi šă să ăngănđe: “Šje u fi dăm ala kupil? Anume măna alu Domnuluj are ku kupilula Ivan.”
67 Sekariah baba rẹ̀ sì kún fún Ẹ̀mí Mímọ́, ó sì sọtẹ́lẹ̀, ó ní:
Zaharija, tatusu alu Ivan are pljin dă Duhu Svănt, atunšje prorokovale šă zăšje:
68 “Olùbùkún ni Olúwa Ọlọ́run Israẹli; nítorí tí ó ti bojú wò, tí ó sì ti dá àwọn ènìyàn rẹ̀ nídè,
“Slava alu Domnu Dimizov alu Izrael, Kă jăl u vinjit šă să otkupilaskă pă narodu aluj!
69 Ó sì ti gbé ìwo ìgbàlà sókè fún wa ní ilé Dafidi ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀;
Jăl u răđikat păntru noj pă spasitelju silni! Dăm potomstva lu sluga amnjov la kralj David.
70 (bí ó ti sọtẹ́lẹ̀ láti ẹnu àwọn wòlíì rẹ̀ mímọ́ tipẹ́tipẹ́), (aiōn g165)
Asta nju fost spus dăm gurălje dă proroci aluj svănc dă kănva: (aiōn g165)
71 Pé, a ó gbà wá là lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wa àti lọ́wọ́ àwọn tí ó kórìíra wá.
spasenje dă la dužmanji anoštri šă dăm mănj kari toc nji mărzălešći.
72 Láti ṣe àánú tí ó ṣèlérí fún àwọn baba wa, àti láti rántí májẹ̀mú rẹ̀ mímọ́,
Are milosrdan pălăngă preci anoštri, šă u ispunulit savezu aluj svănt.
73 ìbúra tí ó ti bú fún Abrahamu baba wa,
Ăm zakletvă kari u dat lu Abraham, alu predaku anostru:
74 láti gbà wá lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wa, kí àwa kí ó lè máa sìn láìfòyà,
să nji izbavalaskă dăm mănj alu dužmanj, să pučenj poslužulenj pă jăl făr dă frikă,
75 ni ìwà mímọ́ àti ní òdodo níwájú rẹ̀, ní ọjọ́ ayé wa gbogbo.
šă să kustănj svănt šă đirept ăm toći zăljilje dă kustu anostru.
76 “Àti ìwọ, ọmọ mi, wòlíì Ọ̀gá-ògo jùlọ ni a ó máa pè ọ́: nítorí ìwọ ni yóò ṣáájú Olúwa láti tún ọ̀nà rẹ̀ ṣe;
Šă tu Ivan fišjoru amnjov, tu vi fi čimat proroku alu Maj Mari Dimizov, kă tu vi meržji ăm nenće alu Domnuluj šă să ăj đireš kalje aluj,
77 láti fi ìmọ̀ ìgbàlà fún àwọn ènìyàn rẹ̀ fún ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ wọn,
Tu vi da alu lume lu Dimizov, Hir fălos dă spasalala šă dă jirtala dă grehurlje alor.
78 nítorí ìyọ́nú Ọlọ́run wà; nípa èyí tí ìlà-oòrùn láti òkè wá bojú wò wá,
Kutotu asta ăj dă rănd dă sufljitu milos alu Dimizovu anostru, ka sorilje kari svitlizešči u vinji afară dăm nor pă noj sus
79 Láti fi ìmọ́lẹ̀ fún àwọn tí ó jókòó ní òkùnkùn àti ní òjìji ikú, àti láti fi ẹsẹ̀ wa lé ọ̀nà àlàáfíà.”
u da lumină alu eje kari šađi ăm tunjerik, šă ăm umbra alu morči. Nju punji pišjorilje anoštri pă kalje dă putuljală.”
80 Ọmọ náà sì dàgbà, ó sì le ní ọkàn, ó sì ń gbé ní ijù títí ó fi di ọjọ́ ìfihàn rẹ̀ fún Israẹli.
Ivan u kriskut šă su ămbălurit ăm duh. Kusta ăm pustinjă păn šje nu su arătat javno alu Izraelc.

< Luke 1 >