< Leviticus 7 >

1 “‘Wọ̀nyí ni àwọn ìlànà fún rírú ẹbọ ẹ̀bi, tí ó jẹ́ mímọ́ jùlọ.
Dabe Ima: ne Iasu gobele salasu hou da hadigidafa. Hagudu da ilia hamoma: ne sia: i dedei diala.
2 Níbi tí wọn ti ń pa ẹran ẹbọ sísun ni kí ẹ ti pa ẹran ẹbọ ẹ̀bi, kí ẹ sì wọ́n ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ yí pẹpẹ náà ká.
Dilia Dabe Ima: ne Iasu ohe amo oloda ea gagoe (north) la: idi (amoga ilia da gobele salasu ohe medole legesa) amoga medole legele, ea maga: me amo oloda ea la: idi la: idi biyaduyale gala amoga sogaga: la: gaganoma: mu.
3 Gbogbo ọ̀rá rẹ̀ ni kí ẹ sun, ọ̀rá ìrù rẹ̀ àti ọ̀rá tí ó bo nǹkan inú rẹ̀.
4 Kíndìnrín méjèèjì pẹ̀lú ọ̀rá tí ó wà lẹ́bàá ìhà rẹ̀, àti ọ̀rá tí ó bo ẹ̀dọ̀, kí ó yọ ọ́ pẹ̀lú àwọn kíndìnrín.
Amasea, ea sefe huluane amola ea sefe la: go amola dialumagaisa amola ea fogome ganumui amola sefe amoga diala amola habe ea la: idi noga: iwane gala amo dasega: le, oloda da: iya gobesima: mu.
5 Àlùfáà yóò sun wọ́n lórí pẹpẹ gẹ́gẹ́ bí ọrẹ tí a fi iná sun sí Olúwa. Ẹbọ ẹ̀bi ni.
Gobele salasu dunu da oloda da: iya sefe huluane Hina Godema Dabe Ima: ne Iasu hamoma: ne, gobesima: mu.
6 Gbogbo ọkùnrin ní ìdílé àlùfáà ló lè jẹ ẹ́ ní ibi mímọ́, ó jẹ́ mímọ́ jùlọ.
Nowa da gobele salasu dunu fi amo ganodini gawali gala da amo manu da defea. Be amo da hadigi sogebi amo ganodini manu da defea. Bai amo iasu da hadigidafa.
7 “‘Òfin yìí kan náà ló wà fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ àti ẹbọ ẹ̀bi: méjèèjì jẹ́ tí àlùfáà, tó fi wọ́n ṣe ètùtù.
Hamoma: ne sia: i afadafa da Dabe Ima: ne Iasu amola Wadela: i Hou Da: be Ima: ne Iasu amoga ouligisa. Amo da nowa gobele salasu dunu da gobele salasu hamoi galea, amo hu da ea:
8 Àlùfáà tó rú ẹbọ sísun fún ẹnikẹ́ni le è mú awọ ẹran ìrúbọ náà.
Gobele salasu dunu da ohe Hina Godema ima: ne gobele salasea, e da amo ea gadofo lamu.
9 Gbogbo ẹbọ ohun jíjẹ tí a bá yan lórí ààrò, àti gbogbo èyí tí a yan nínú apẹ, àti nínú àwopẹ̀tẹ́, ni kí ó jẹ́ ti àlùfáà tí ó rú ẹbọ náà.
Gala: ine Iasu amola amo da gobele nasu ganodini gobei o ofodo ganodini o agi gobesu agoai da: iya gobei amo ha: i manu huluane da gobele salasu dunu amo da Godema gobele sali, amo ea:
10 Bẹ́ẹ̀ náà ni ẹbọ ohun jíjẹ yálà a fi òróró pò ó tàbí èyí tó jẹ́ gbígbẹ, wọ́n jẹ́ ti gbogbo ọmọ Aaroni.
Be Gala: ine Iasu hame gobei (susuligi gilisi o hafoga: i) amo huluane da Elane gobele salasu dunu fi ilia: Amo fifili defele ima: mu.
11 “‘Wọ̀nyí ni àwọn ìlànà fún ọrẹ àlàáfíà tí ẹnikẹ́ni bá gbé wá síwájú Olúwa.
Hagudu da Hahawane Gilisili Olofole Iasu Hina Godema ima: ne hamoma: ne sia: i dedei diala.
12 “‘Bí ẹni náà bá gbé e wá gẹ́gẹ́ bí àfihàn ọkàn ọpẹ́, pẹ̀lú ẹbọ ọpẹ́ yìí, ó gbọdọ̀ mú àkàrà aláìwú tí a fi òróró pò wá àti àkàrà aláìwú fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ tí a dà òróró sí àti àkàrà tí a fi ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára tí a fi òróró pò ṣe.
Nowa dunu da Godema nodoma: ne amo Iasu imunusa: dawa: sea, e da ohe gobele salimusa: amola agi ga: gi (yisidi hame gilisi) gaguli misa: mu. Amo agi ga: gi da falaua amola olife susuligi amoga hamoi o belowagi amoga olife susuligi da legei o falaua ga: gi amola olife susuligi gilisi amoga hamoi.
13 Pẹ̀lú ọrẹ àlàáfíà rẹ̀, kí ó tún mú àkàrà wíwú wá fún ọpẹ́,
Amola eno, e da agi ga: gi yisidi hame gilisi amo gobei gaguli misa: mu.
14 kí ó mú ọ̀kọ̀ọ̀kan nínú oríṣìíríṣìí ọrẹ àlàáfíà rẹ wá gẹ́gẹ́ bí ẹ̀bùn fún Olúwa, ó jẹ́ tí àlùfáà tí ó wọ́n ẹ̀jẹ̀ ọrẹ àlàáfíà.
E da agi ga: gi hisu hisu amo fifili, Hina Godema dawa: ma: ne Ema imunu. Amo agi ga: gi da gobele salasu dunu amo da ohe ea maga: me lale, oloda la: idiga sogaga: la: gaganosa, amo dunu ea:
15 Ẹran ọrẹ àlàáfíà ti ọpẹ́ yìí ni wọ́n gbọdọ̀ jẹ ní ọjọ́ gan an tí wọ́n rú ẹbọ, kò gbọdọ̀ ṣẹ́ ẹran kankan kù di àárọ̀ ọjọ́ kejì.
Ohe ea hu da eso amoga e da gobele sali amo mai dagoi ba: ma: mu. Golale, hahabe, eno hu hame mai dialumu da sema bagade.
16 “‘Ṣùgbọ́n bí ó bá jẹ́ pé ó mú ọrẹ wá, nítorí ẹ̀jẹ́ tó jẹ́ tàbí kí ó jẹ́ ọrẹ àtinúwá, wọn yóò jẹ ẹbọ náà ní ọjọ́ tí wọ́n rú ẹbọ yìí, ṣùgbọ́n wọ́n lè jẹ èyí tó ṣẹ́kù ní ọjọ́ kejì.
Be dunu da ea sia: ilegei dafawaneyale ba: ma: ne o udigili hahawane ima: ne, Hahawane Gilisili Olofole Iasu gaguli masea, amo esoga ha: i manu hame mai diala, amo aya esoga manu da defea.
17 Gbogbo ẹran tó bá ṣẹ́kù di ọjọ́ kẹta ní ẹ gbọdọ̀ sun.
Be hu da eso osodayale dialebe ba: sea, amo gobesima: mu.
18 Bí ẹ bá jẹ ọ̀kankan nínú ẹran ọrẹ àlàáfíà ní ọjọ́ kẹta, kò ni jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà. A kò ní í kà á sí fún ẹni tó rú ẹbọ náà, nítorí pé ó jẹ́ àìmọ́, ẹnikẹ́ni tó bá sì jẹ ẹ́, ni a ó di ẹ̀bi rẹ̀ rù.
Be dunu da eso osodayale amoga hu nasea, Gode da iabe dunu ea iasu hame lamu. Hina Gode da ea wadela: i hou hame gogolema: ne olofomu. Be E da amo iasu ledo hamoi dagoi ba: mu. Amola nowa dunu da amo nasea, se nabimu.
19 “‘Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ẹran tí ó bá ti kan ohun tí a kà sí àìmọ́, sísun ni kí ẹ sun ún. Ẹnikẹ́ni tí a ti kà sí mímọ́ le è jẹ nínú ẹran tí ó kù.
Be ledo hamoi liligi da Godema Iasu hu amo digili ba: sea, amo hu mae moma: ne sia: ma. Amo hu gobesima: mu. Nowa dunu da Hina Gode Ea sema defele dodofei dagoi ba: sea, da Godema Iasu bu manu defele ba: mu.
20 Ṣùgbọ́n bí ẹni tí kò mọ́ bá jẹ́ ẹran ọrẹ àlàáfíà tí ó jẹ́ tí Olúwa, a ó gé irú ẹni bẹ́ẹ̀ kúrò lára àwọn ènìyàn rẹ̀.
Be nowa da ledo gala hame dodofei ba: sea, amo hu nasea, e da Gode Ea Fidafa amoga afafai dagoi ba: mu.
21 Bí ẹnikẹ́ni bá fọwọ́ kan ohun aláìmọ́ yálà ohun àìmọ́ ti ènìyàn, ẹranko aláìmọ́, ohun àìmọ́ yówù kí ó jẹ́ tàbí ohunkóhun tí ó jẹ́ ìríra, tí ó sì tún jẹ́ ẹran ọrẹ àlàáfíà tó jẹ́ ti Olúwa, a ó gé irú ẹni bẹ́ẹ̀ kúrò lára àwọn ènìyàn rẹ.’”
Amola, nowa da ledo hamoi liligi (dunuga o ohega hamoi) digili ba: lu, amo hu udigili nasea, e amola da Gode Ea Fidafa amoga afafai dagoi ba: mu.
22 Olúwa sọ fún Mose pé,
Hina Gode da Mousesema (Isala: ili fi dunuma alofele ima: ne) hagudu dedei hamoma: ne sia: i olelei.
23 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Ẹ má ṣe jẹ ọ̀rá màlúù, àgùntàn tàbí ewúrẹ́.
Bulamagau, sibi amola goudi, ilia sefe maedafa moma: ne sia: ma.
24 Ẹ lè lo ọ̀rá ẹran tó kú fúnra rẹ̀ tàbí èyí tí ẹranko igbó pa, fún nǹkan mìíràn, ṣùgbọ́n ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ẹ́.
Ohe amo da hisu bogoi o sigua ohega medole legei, amo ea sefe mae moma: ne sia: ma. Be ea sefe eno hou hamomusa: lamu da defea.
25 Ẹnikẹ́ni tó bá jẹ ọ̀rá ẹran tí a fi rú ẹbọ sísun sí Olúwa ni ẹ gbọdọ̀ gé kúrò lára àwọn ènìyàn rẹ̀.
Nowa da ohe amo Hina Godema ha: i manu iasu imunusa: ilegei galu, amo ea sefe nasea da Gode Ea Fidafa amoga afafai dagoi ba: mu.
26 Ẹ kò sì gbọdọ̀ jẹ ẹ̀jẹ̀ ẹyẹ tàbí ẹran ní gbogbo ibi tí ẹ bá ń gbé.
Isala: ili dunu da habodili esalea, sio o ohe ilia maga: me manu da sema bagade.
27 Bí ẹnikẹ́ni bá jẹ ẹ̀jẹ̀, a ó gé ẹni bẹ́ẹ̀ kúrò lára àwọn ènìyàn rẹ̀.’”
Nowa da amo sema wadela: sea, da Gode Ea Fidafa amoga afafai dagoi ba: mu.
28 Olúwa sọ fún Mose pé,
Amola Hina Gode da Mousesema Isala: ili fi dunuma alofele ima: ne amo hagudu dedei hamoma: ne sia: i olelei.
29 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Ẹnikẹ́ni tó bá mú ọrẹ àlàáfíà wá fún Olúwa.
Nowa da Hahawane Gilisili Olofole Iasu imunusa: dawa: sea, e da amo fifilalu, fifi afae Hina Godema imunusa: gaguli misa: mu.
30 Pẹ̀lú ọwọ́ ara rẹ̀ ni kí ó fi mú ọrẹ tí a fi iná sun wá fún Olúwa, kí ó mú ọ̀rá àti igẹ̀, kí ó sì fi igẹ̀ yìí níwájú Olúwa bí ọrẹ fífì.
E da amo hi loboga ha: i manu iasu gaguli misa: mu. E da amo ohe ea sefe amola ea bidegi gaguli misini, Hina Godema ima: ne sia: ma.
31 Àlùfáà yóò sun ọ̀rá náà lórí pẹpẹ ṣùgbọ́n igẹ̀ ẹran náà jẹ́ ti Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀,
Gobele salasu dunu da sefe amo oloda da: iya gobesimu. Be bidegi amo da gobele salasu dunu ea:
32 kí ẹ fún àlùfáà ní itan ọ̀tún lára ọrẹ àlàáfíà yín gẹ́gẹ́ bí ìpín tiyín fún àlùfáà.
33 Ọmọ Aaroni ẹni tí ó rú ẹbọ ẹ̀jẹ̀ àti ọ̀rá ọrẹ àlàáfíà ni kí ó ni itan ọ̀tún gẹ́gẹ́ bí ìpín tirẹ̀.
Amo ohe ea emodafa e da gobele salasu dunu amo da maga: me amola sefe Hahawane Gilisili Olofole Ima: ne iaha, amo ema imunu.
34 Nínú ọrẹ àlàáfíà àwọn ọmọ Israẹli, mo ti ya igẹ̀ tí a fi àti itan tí ẹ mú wá sọ́tọ̀ fún Aaroni àlùfáà àti àwọn ọmọ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìpín wọn ní gbogbo ìgbà láti ọ̀dọ̀ ara Israẹli.’”
Ohe ea bidegi amola emodafa amo ele da iasu noga: idafa amo Hina Gode da Isala: ili fi dunu ilima lale, gobele salasu fi dunu ilima iaha. Amo hou da mae yolesili, dialumu.
35 Èyí ni ìpín tí a yà sọ́tọ̀ fún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ nínú ẹbọ tí a finá sun sí Olúwa lọ́jọ́ tí wọ́n mú wọn wá láti sin Olúwa gẹ́gẹ́ bí àlùfáà.
Amo da ha: i manu Hina Godema iasu, amo fifili, Elane amola egefelali, amo ilia gobele salasu dunu ilegesu eso amoga iasu.
36 Lọ́jọ́ tí a fi òróró yàn wọ́n, ni Olúwa ti pa á láṣẹ pé kí àwọn ọmọ Israẹli máa fún wọn ní àwọn nǹkan wọ̀nyí gẹ́gẹ́ bí ìpín wọn ìgbà gbogbo fún àwọn ìran tó ń bọ̀.
Amo esoga, Hina Gode da Isala: ili dunu ilima ilia da iasu fifili, amo fifi gobele salasu dunuma ima: ne sia: i. Amo hamoma: ne sia: i da Isala: ili dunu ilima fa: no eso huluane mae yolesili, ouligima: ne sia: ma
37 Nítorí náà, àwọn nǹkan wọ̀nyí jẹ́ ìlànà fún ẹbọ sísun, ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, ẹbọ ẹ̀bi, ìfinijoyè àlùfáà àti ẹbọ àlàáfíà
Defea! Amo da Wadela: i Hou Dabe Ima: ne Iasu, Gala: ine Iasu, Wadela: i Hou Gogolema: ne Olofoma: ne Iasu, Mae Dawa: le Wadela: i Hamoi Iasu, Dabe Ima: ne Iasu amola Hahawane Gilisili Olofole Iasu ilia hamoma: ne sia: i huluane dedei diala.
38 èyí tí Olúwa fún Mose lórí òkè Sinai lọ́jọ́ tí Olúwa pa á láṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli pé kí wọ́n máa mú ọrẹ wọn wá fún Olúwa ni ijù Sinai.
Sainai Goumi, hafoga: i soge ganodini, amogawi Hina Gode da amo hamoma: ne sia: i huluane Mousesema i dagoi. Eso amoga E da Isala: ili dunu ilia iasu ima: ne sia: i, E da amo hamoma: ne sia: i Mousesema i.

< Leviticus 7 >