< Leviticus 5 >
1 “‘Bí ẹnìkan bá dẹ́ṣẹ̀ nítorí pé kò sọ̀rọ̀ nígbà tí a bi í ní gbangba pé kó jẹ́rìí nípa nǹkan tó rí tàbí nǹkan tó mọ̀ nípa ìṣẹ̀lẹ̀ kan, a ó di ẹ̀bi rẹ̀ rù ú.
“‘Mũndũ angĩaga kũruta ũira rĩrĩa etĩtwo arute ũira igũrũ rĩa ũndũ oonete kana akaigua, mũndũ ũcio nĩehĩtie, na nĩagacookererwo nĩ wĩhia ũcio wake.
2 “‘Tàbí bí ẹnìkan bá fọwọ́ kan ohun tí a kà sí àìmọ́ yálà òkú ẹranko aláìmọ́ tàbí òkú ẹran ọ̀sìn aláìmọ́ tàbí òkú ẹ̀dá yówù tó ń rìn lórí ilẹ̀ bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹni náà kò mọ̀, ó ti di aláìmọ́, ó sì ti jẹ̀bi.
“‘Kana mũndũ angĩhutia kĩndũ o nakĩ kĩrĩ thaahu, kĩrĩ kĩimba kĩa nyamũ ya gĩthaka ĩrĩ thaahu kana kĩa ũhiũ ũrĩ thaahu, kana gĩa ciũmbe iria itambaga thĩ irĩ thaahu, o na aakorwo ndooĩ ũndũ ũcio, mũndũ ũcio nĩanyiitĩtwo nĩ thaahu na nĩahĩtĩtie.
3 Tàbí bí ó bá fọwọ́ kan ohun àìmọ́ ti ènìyàn, ohunkóhun tó lè mú ènìyàn di aláìmọ́, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹni náà kò mọ̀, nígbà tí ó bá mọ̀ nípa rẹ̀ yóò jẹ̀bi.
“‘Kana angĩhutia kĩndũ kĩrĩ thaahu kiumĩte harĩ mũndũ, kĩndũ o nakĩ kĩrĩa kĩngĩmũthaahia, o na akorwo ũndũ ũcio ndaũũĩ-rĩ, hĩndĩ ĩrĩa akaaũmenya, nĩagatuĩka nĩahĩtĩtie.
4 Tàbí bí ẹni kan bá búra láti ṣe ohun kan láì ronú lé e lórí, yálà ohun tó dára tàbí ohun búburú, nínú ọ̀rọ̀ yówù tó ti búra láì kíyèsi ara, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, kò mọ̀ nípa rẹ̀ tẹ́lẹ̀, bí ó ti wù kó rí, nígbà tó bá mọ̀ yóò jẹ̀bi.
“‘Kana mũndũ angĩĩhĩta gwĩka ũndũ o na ũrĩkũ atawĩcirĩtie wega, ũrĩ ũndũ mwega kana mũũru, ũndũ-inĩ o wothe ũrĩa mũndũ angĩhiũha kwĩhĩta, o na angĩkorwo atekũũmenya-rĩ, rĩrĩa akaaũmenya, nĩagatuĩka nĩahĩtĩtie ũndũ-inĩ ũcio.
5 Bí ẹnikẹ́ni bá jẹ̀bi ọ̀kan nínú àwọn nǹkan wọ̀nyí, ó gbọdọ̀ jẹ́wọ́ irú ọ̀nà tó ti dẹ́ṣẹ̀
“‘Rĩrĩa mũndũ ahĩtĩtie na njĩra ĩmwe ya macio-rĩ, no nginya oimbũre ũndũ ũrĩa ehĩtie naguo,
6 àti pé gẹ́gẹ́ bí ìtánràn fún ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ṣẹ̀, ó gbọdọ̀ mú wa fún Olúwa, abo àgùntàn tàbí abo ewúrẹ́ láti inú agbo ẹran wá gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, àlùfáà yóò sì ṣe ètùtù fún ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ṣẹ̀.
na nĩ ũndũ wa rĩĩhia rĩu ekĩte, no nginya arehere Jehova kamwatĩ kana mbũri kuuma rũũru-inĩ, rĩrĩ iruta rĩa kũhoroherio mehia; nake mũthĩnjĩri-Ngai nĩakamũhoroheria mehia make.
7 “‘Bí kò bá lágbára àti mú ọ̀dọ́-àgùntàn wá, kí ó mú àdàbà méjì tàbí ọmọ ẹyẹlé méjì fún Olúwa gẹ́gẹ́ bí ìtánràn fún ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀—ọ̀kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, èkejì fún ẹbọ sísun.
“‘Angĩkorwo ndangĩona kagondu, nĩakarehera Jehova ndirahũgĩ igĩrĩ kana tũtutuura twĩrĩ, rĩrĩ irĩhi rĩa wĩhia wake, ĩmwe ĩrĩ ya iruta rĩa kũhoroherio mehia na ĩrĩa ĩngĩ ĩrĩ ya iruta rĩa njino.
8 Kí ó kó wọn wá fún àlùfáà tí yóò kọ́kọ́ rú ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ kí ó yín in lọ́rùn, ṣùgbọ́n kí ó má já orí rẹ̀ tan,
Nĩagacirehera mũthĩnjĩri-Ngai, ũrĩa ũkaamba kũruta ĩrĩa ya iruta rĩa kũhoroherio mehia. Nĩakamĩthiora ngingo yunĩke no ndakamĩtinanie,
9 kí ó sì wọ́n díẹ̀ lára ẹ̀jẹ̀ ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ náà sí ẹ̀gbẹ́ pẹpẹ, ìyókù ẹ̀jẹ̀ náà ni kí ó ro sí ìsàlẹ̀ pẹpẹ. Ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ ni.
na nĩagacooka aminjaminje thakame ĩmwe ya iruta rĩu rĩa mehia mwena-inĩ wa kĩgongona, na thakame ĩyo ĩngĩ amĩite thĩ gĩtina-inĩ gĩa kĩgongona. Rĩu nĩrĩo iruta rĩa kũhoroherio mehia.
10 Lẹ́yìn èyí àlùfáà yóò wá rú ẹbọ sísun gẹ́gẹ́ bí ìlànà, yóò sì ṣe ètùtù fún un nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ṣẹ̀, a ó sì dáríjì í.
Mũthĩnjĩri-Ngai nĩagacooka arute ĩyo ĩngĩ ĩrĩ iruta rĩa njino o ta ũrĩa gũtuĩtwo, na amũhoroherie mehia marĩa ekĩte, nake nĩakarekerwo.
11 “‘Bí ó bá sì jẹ́ pé kò ní agbára àti mú àdàbà méjì tàbí ọmọ ẹyẹlé méjì wá, kí ó mú ìdámẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára wá fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ rẹ, kò gbọdọ̀ fi òróró tàbí tùràrí sí i nítorí pé ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ ni.
“‘No rĩrĩ, angĩkorwo ndangĩona ndirahũgĩ igĩrĩ kana tũtutuura twĩrĩ, nĩakĩrute gĩcunjĩ gĩa ikũmi kĩa eba ya mũtu ũrĩa mũhinyu mũno ũrĩ iruta rĩa mehia make. Ndakawĩkĩre maguta kana ũbani, nĩ ũndũ rĩu nĩ iruta rĩa kũhoroherio mehia.
12 Kí ó gbé e wá sí ọ̀dọ̀ àlùfáà, àlùfáà yóò sì bu ẹ̀kúnwọ́ ìyẹ̀fun gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ìrántí, kí ó sì sun ún lórí pẹpẹ, gẹ́gẹ́ bí ẹbọ tí a fi iná sun sí Olúwa. Ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ ni.
Nĩakaũtwarĩra mũthĩnjĩri-Ngai, nake arũme ngundi yaguo ũtuĩke gĩcunjĩ gĩa kĩririkano acooke aũcinĩre kĩgongona-inĩ igũrũ rĩa maruta marĩa marutĩirwo Jehova na mwaki. Rĩu nĩrĩo iruta rĩa kũhoroherio mehia.
13 Báyìí ni àlùfáà yóò ṣe ètùtù fún ẹni náà fún èyíkéyìí nínú àwọn ẹ̀ṣẹ̀ tí ó dá, a ó sì dáríjì í: ìyókù sì jẹ́ ti àlùfáà, bí ẹbọ ohun jíjẹ.’”
Ũguo nĩguo mũthĩnjĩri-Ngai akaahoroheria mũndũ ũcio rĩĩhia o rĩothe rĩa macio angĩkorwo ekĩte, nake nĩakarekerwo. Matigari ma iruta rĩu magaatuĩka ma mũthĩnjĩri-Ngai, o ta ũrĩa gwĩkagwo hĩndĩ ya iruta rĩa mũtu.’”
Ningĩ Jehova akĩĩra Musa atĩrĩ:
15 “Nígbà tí ẹnìkan bá dẹ́ṣẹ̀ ìrékọjá tí ó sì ṣe láìmọ̀ ní ti àwọn ohun mímọ́ Olúwa, kí ó mú àgbò láti inú agbo ẹran wá fún Olúwa gẹ́gẹ́ bí ìtánràn, àgbò tí kò lábùkù tí ó sì níye lórí gẹ́gẹ́ bí iye owó ibi mímọ́. Ẹbọ ẹ̀bi ni.
“Hĩndĩ ĩrĩa mũndũ angĩhĩtia na ehie atekwenda wĩhia ũkoniĩ indo iria nyamũrĩre Jehova-rĩ, nĩakarehera Jehova ndũrũme ĩrĩ iruta rĩa irĩhi rĩa ihĩtia kuuma rũũru-inĩ, ndũrũme ĩtarĩ na kaũũgũ, ĩkorwo ĩrĩ ya thogora ũrĩa mũiganĩru wa betha, kũringana na cekeri ya handũ-harĩa-haamũre. Rĩu nĩrĩo iruta rĩa ihĩtia.
16 Kí ó ṣe àtúnṣe nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ti ṣẹ̀ nínú ti àwọn ohun mímọ́, kí ó sì fi ìdámárùn-ún kún iye rẹ̀, kí ó sì kó gbogbo rẹ̀ fún àlùfáà. Àlùfáà yóò sì fi àgbò ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ náà ṣe ètùtù fún, a ó sì dáríjì í.
No nginya arĩhe irĩhi nĩ ũndũ wa ũndũ ũrĩa aagĩte kũhingia ũkoniĩ indo iria nyamũre, na ongerere gĩcunjĩ gĩa ithano gĩa thogora wa kĩndũ kĩu ararĩha, na acinengere mũthĩnjĩri-Ngai ciothe, ũrĩa ũkamũhoroheria na ndũrũme ĩyo ya iruta rĩa mahĩtia, nake nĩakarekerwo.
17 “Bí ẹnìkan bá dẹ́ṣẹ̀ tí ó sì ṣe ohun tí kó yẹ ko ṣe sí ọ̀kan nínú òfin Olúwa, bí kò tilẹ̀ mọ̀, ó jẹ̀bi, yóò sì ru ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀
“Mũndũ angĩĩhia eke ũndũ ũrĩa mũkananie thĩinĩ wa maathani mothe ma Jehova o na angĩkorwo ndaraũmenya-rĩ, nĩagacookererwo nĩ mahĩtia macio ekĩte.
18 kí ó mú àgbò kan láti inú agbo ẹran wá sọ́dọ̀ àlùfáà, fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ àgbò tí kò lábùkù tí ó sì níye lórí bí iye owó ibi mímọ́. Báyìí ni àlùfáà yóò ṣe ètùtù fún ẹni náà, fún àṣìṣe tí ó ṣe láìmọ̀, a ó sì dáríjì í.
Nĩakarehera mũthĩnjĩri-Ngai ndũrũme ya iruta rĩa mahĩtia kuuma rũũru-inĩ, ndũrũme ĩtarĩ na kaũũgũ na ya thogora ũrĩa wagĩrĩire. Ũguo nĩguo mũthĩnjĩri-Ngai akaahoroheria mũndũ ũcio nĩ ũndũ wa mahĩtia marĩa ekĩte atekwenda, nake nĩakarekerwo.
19 Ẹbọ ẹ̀bi ni, ó ti jẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ṣẹ̀ sí Olúwa.”
Rĩu nĩrĩo iruta rĩa mahĩtia; ti-itherũ mũndũ ũcio nĩahĩtĩirie Jehova.”